< Acts 25 >

1 Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tí ó dé sí ilẹ̀ náà, Festu gòkè láti Kesarea lọ sì Jerusalẹmu,
Na rĩrĩ, mĩthenya ĩtatũ yathira thuutha wa Fesito gũkinya kũu bũrũri-inĩ, akiuma Kaisarea akĩambata agĩthiĩ Jerusalemu.
2 ní ibi tí àwọn olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn pàtàkì nínú àwọn Júù ti gbé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Paulu wá, wọ́n sì bẹ̀ ẹ́.
Nao athĩnjĩri-Ngai arĩa anene na atongoria a Ayahudi magĩũka harĩ we, makĩmwĩra maũndũ marĩa Paũlũ aathitangĩirwo.
3 Wọ́n tọrọ lọ́wọ́ Festu, kí ó bá le ṣe ojúrere fún wọn, kí ó bá à lè jẹ́ kí wọn mú Paulu wá sí Jerusalẹmu, wọn ń gbìmọ̀ láti dènà dè é, kí wọn sì pa á ní ọ̀nà.
Nĩmahĩkire gũthaitha Fesito atĩ nĩ ũndũ wa wega wake kũrĩ o etĩkĩre Paũlũ atwarwo Jerusalemu, nĩgũkorwo nĩmahaaragĩria kũmuoheria njĩra-inĩ mamũũrage.
4 Ṣùgbọ́n Festu dáhùn pé, “A pa Paulu mọ́ ní Kesarea, àti pé òun tìkára òun ń múra àti padà lọ ní lọ́ọ́lọ́ọ́ yìí.
Nake Fesito akĩmacookeria atĩrĩ, “Paũlũ ahingĩirwo Kaisarea, na niĩ nĩngũcooka kuo o narua.
5 Ẹ jẹ́ kí díẹ̀ nínú àwọn olórí yín bá mi sọ̀kalẹ̀ lọ láti fi ìdí ẹ̀sùn tí ẹ fi sun ọkùnrin náà múlẹ̀ níbẹ̀, bí ó bá ní ohun búburú kan tí ó wà lọ́wọ́ rẹ̀.”
Tondũ ũcio no tũthiĩ na atongoria amwe anyu nĩgeetha mathiĩ magathitangĩre mũndũ ũcio kuo, angĩkorwo nĩ harĩ ũndũ mũũru ekĩte.”
6 Lẹ́yìn tí ó sì ti gbé níwọ̀n ọjọ́ mẹ́jọ tàbí mẹ́wàá pẹ̀lú wọn, ó sọ̀kalẹ̀ lọ sì Kesarea, ni ọjọ́ kejì ó jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́, ó sì pàṣẹ pé ki a mú Paulu wá síwájú òun.
Thuutha wa gũikarania nao kũu ihinda ta rĩa mĩthenya ĩnana kana ikũmi, agĩikũrũka, agĩthiĩ Kaisarea, na mũthenya ũyũ ũngĩ akĩgomithania igooti, na agĩathana Paũlũ areehwo mbere yake.
7 Nígbà tí Paulu sì dé, àwọn Júù tí o tí Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ wá dúró yí i ká, wọ́n ǹ ka ọ̀ràn púpọ̀ tí ó sì burú sí Paulu lọ́rùn, tí wọn kò lè fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Rĩrĩa Paũlũ aakinyire, Ayahudi arĩa maikũrũkĩte kuuma Jerusalemu makĩmũrigiicĩria, na makĩmũthitangĩra maũndũ maingĩ mooru, marĩa matangĩahotire kuonania atĩ nĩ ma ma.
8 Paulu si wí tí ẹnu rẹ̀ pé, “Èmi kò ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ kan sì òfin àwọn Júù, tàbí tẹmpili, tàbí sí Kesari.”
Nake Paũlũ akĩĩyarĩrĩria, akiuga atĩrĩ: “Niĩ ndirĩ ũndũ njĩkĩte ũreganĩte na watho wa Ayahudi, o na kana wa hekarũ o na kana wa Kaisari.”
9 Ṣùgbọ́n Festu ń fẹ́ láti ní ojúrere lọ́dọ̀ àwọn Júù, ó sì dá Paulu lóhùn, wí pe, “Ìwọ ń fẹ́ gòkè lọ sì Jerusalẹmu, kí a sì ṣe ẹjọ́ nǹkan wọ̀nyí níbẹ̀ níwájú mi bí?”
Nake Fesito, akĩenda gũkenia Ayahudi akĩũria Paũlũ atĩrĩ, “Wee nĩ ũkwenda kwambata ũthiĩ Jerusalemu ngagũciirithĩrie kuo nĩ ũndũ wa maũndũ maya ũthitangĩirwo?”
10 Paulu sì wí pé, “Mo dúró níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Kesari níbi tí ó yẹ kí a ṣe ẹjọ́ mí: èmi kò ṣẹ àwọn Júù, bí ìwọ pẹ̀lú ti mọ̀ dájú.
Nake Paũlũ agĩcookia atĩrĩ, “Rĩu ndũgamĩte igooti-inĩ rĩa Kaisari, harĩa njagĩrĩirwo nĩ gũciirithĩrio. Niĩ ndihĩtĩirie Ayahudi, o ta ũrĩa wee mwene ũmenyete o wega.
11 Ǹjẹ́ bí mo bá ṣẹ̀, tí ó ṣe pe mo sì ṣe ohun kan tí ó yẹ fún ikú, èmi kò kọ̀ láti kú, ṣùgbọ́n bí kò bá sí òtítọ́ kan nínú ẹ̀sùn tí àwọn Júù yìí fi mi sùn sí, ẹnìkan kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fà mí lé wọn lọ́wọ́. Mo fi ọ̀ràn mi lọ Kesari.”
No rĩrĩ, angĩkorwo ndĩ na ihĩtia rĩa gwĩka ũndũ o wothe wa gũtũma njũragwo-rĩ, ndingĩrega gũkua. No angĩkorwo maũndũ marĩa thitangĩirwo nĩ Ayahudi aya ti ma ma-rĩ, gũtikĩrĩ mũndũ ũrĩ na gĩtũmi gĩa kũũneana kũrĩ o. Ndacookia ciira riiko kũrĩ Kaisari!”
12 Lẹ́yìn tí Festu ti bá àjọ ìgbìmọ̀ sọ̀rọ̀, ó dáhùn pe, “Ìwọ ti fi ọ̀ràn rẹ lọ Kesari. Ní ọ̀dọ̀ Kesari ni ìwọ ó lọ!”
Thuutha wa Fesito gũcookania ndundu na kĩama gĩake, akiuga atĩrĩ, “Wacookia ciira riiko kũrĩ Kaisari na kũrĩ Kaisari nĩkuo ũgũthiĩ!”
13 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan, Agrippa ọba, àti Bernike sọ̀kalẹ̀ wá sì Kesarea láti kí Festu.
Mĩthenya mĩnini yathira Mũthamaki Agiripa na Berinike magĩũka kũu Kaisarea kũnyiita Fesito ũgeni.
14 Bí wọ́n sì tí wà níbẹ̀ lọ́jọ́ púpọ̀, Festu mú ọ̀ràn Paulu wá síwájú ọba, wí pé, “Feliksi fi ọkùnrin kan sílẹ̀ nínú túbú.
Na tondũ nĩmaikaraga kũu mĩthenya mĩingĩ-rĩ, Fesito akĩhe mũthamaki ũcio ũhoro wa ciira wa Paũlũ, akĩmwĩra atĩrĩ, “Gũkũ kũrĩ na mũndũ watigirwo nĩ Felike arĩ muohe.
15 Ẹni tí àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà àwọn Júù fi sùn nígbà tí mo wà ni Jerusalẹmu, wọ́n ń fẹ́ kí èmi ó dá a lẹ́bi ikú.
Rĩrĩa ndaathiire Jerusalemu-rĩ, athĩnjĩri-Ngai arĩa anene na athuuri a Ayahudi nĩmamũthitangire, na makĩnjũũria ndĩmũtuĩre.
16 “Àwọn ẹni tí mo sì dá lóhùn pé, kì í ṣe àṣà àwọn ará Romu láti dá ẹnikẹ́ni lẹ́bi, kí ẹni tí a fi sùn náà tó ko àwọn olùfisùn rẹ̀ lójú, láti lè ri ààyè wí tí ẹnu rẹ̀, nítorí ọ̀ràn tí a kà sí i lọ́rùn.
“Na niĩ ngĩmeera atĩ ti mũtugo wa andũ a Roma kũneana mũndũ o wothe ataambĩte kũngʼethanĩra na andũ arĩa mamũthitangĩte na kũheo mweke wa kwĩyarĩrĩria ũhoro-inĩ ũrĩa athitangĩirwo.
17 Nítorí náà nígbà tí wọ́n jùmọ̀ wá sí ìhín yìí, èmi kò fi ọ̀rọ̀ náà falẹ̀ rara, níjọ́ kejì mo jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́, mo sì pàṣẹ pé kí a mú ọkùnrin náà wá.
Rĩrĩa tuokire nao gũkũ, ndiaikaririe ciira ũcio, no ndaarookire kũgomithania igooti na ngĩathana mũndũ ũcio areehwo.
18 Nígbà tí àwọn olùfisùn náà dìde, wọn kò ka ọ̀ràn búburú irú èyí tí mo rò sí i lọ́rùn.
Rĩrĩa andũ arĩa maamũthitangĩte maarũgamire kwaria, matiamũthitangĩire ũndũ o na ũmwe mũũru ta ũrĩa nderĩgĩrĩire.
19 Ṣùgbọ́n wọ́n ní ọ̀ràn kan sí i, ní ti ìsìn wọn, àti ní ti Jesu kan tí o tí kú, tí Paulu tẹnumọ́ pé ó wà láààyè.
No handũ ha ũguo, o maarĩ na maũndũ mamwe maakararanagia nake makoniĩ ũhoro wa ndini yao na makoniĩ ũhoro wa mũndũ wakuĩte wetagwo Jesũ ũrĩa Paũlũ oigaga atĩ arĩ muoyo.
20 Bí èmi kò sì tí mọ̀ bí a tí ń ṣe ìwádìí nǹkan wọ̀nyí, mo bí i lérè pé ṣe ó ń fẹ́ lọ sì Jerusalẹmu, kí a sì ṣe ẹjọ́ nǹkan wọ̀nyí níbẹ̀.
Nĩndarigirwo nĩ ũrĩa ingĩtuĩria maũndũ ta macio; nĩ ũndũ ũcio ngĩmũũria kana no eende gũthiĩ Jerusalemu agaciirithĩrio maũndũ macio aathitangĩirwo kuo.
21 Ṣùgbọ́n nígbà tí Paulu fi ọ̀ràn rẹ lọ Augustu, pé kí a pa òun mọ́ fún ìdájọ́ rẹ̀, mo pàṣẹ pe kí a pa á mọ́ títí èmi o fi lè rán an lọ sọ́dọ̀ Kesari.”
Rĩrĩa Paũlũ aacookirie ciira riiko etererio itua rĩa Mũthamaki-rĩ, ngĩathana ahingĩrwo nginya rĩrĩa ingĩahotire kũmũtwarithia kũrĩ Kaisari.”
22 Agrippa wí fún Festu pé, “Èmi pẹ̀lú fẹ́ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ọkùnrin náà tìkára mi.” Ó sì wí pé, “Ní ọ̀la ìwọ ó gbọ́ ọ.”
Hĩndĩ ĩyo Agiripa akĩĩra Fesito atĩrĩ, “No nyende kwĩiguĩra mũndũ ũcio akĩaria.” Nake Fesito agĩcookia atĩrĩ, “Nĩũkamũigua rũciũ.”
23 Ní ọjọ́ kejì, tí Agrippa àti Bernike wọ ilé ẹjọ́ ti àwọn ti ẹ̀ṣọ́ púpọ̀ pẹ̀lú àwọn olórí ogun àti àwọn ènìyàn ńlá ní ìlú, Festu pàṣẹ, wọ́n sì mú Paulu jáde.
Mũthenya ũyũ ũngĩ, Agiripa na Berinike magĩũka marĩ na mwago mũnene na magĩtoonya nyũmba ya gũciirĩrwo marĩ hamwe na anene a thigari o na athuuri a itũũra arĩa maarĩ igweta. Nake Fesito agĩathana Paũlũ areehwo.
24 Festu sì wí pé, “Agrippa ọba, àti gbogbo ẹ̀yin ènìyàn tí ó wà níhìn-ín pẹ̀lú wa, ẹ̀yin rí ọkùnrin yìí, nítorí ẹni tí gbogbo ìjọ àwọn Júù tí fi ẹ̀bẹ̀ béèrè lọ́wọ́ mi ni Jerusalẹmu àti Kesarea níhìn-ín yìí, tí wọ́n ń kígbe pé, kò yẹ fún un láti wà láààyè mọ́.
Fesito akiuga atĩrĩ, “Mũthamaki Agiripa na andũ arĩa othe mũrĩ na ithuĩ haha, nĩmũkuona mũndũ ũyũ! Nĩwe mũingĩ wothe wa Ayahudi wanjũũririe, ndĩ kũu Jerusalemu na ndĩ gũkũ Kaisarea, ngaciire ũhoro wake, ũkĩanĩrĩra ũkiugaga atĩ ndagĩrĩirwo nĩgũtũũra muoyo rĩngĩ.
25 Ṣùgbọ́n èmi rí i pe, kò ṣe ohun kan tí ó yẹ sí ikú, bí òun tìkára rẹ̀ sí tí fi ọ̀ràn rẹ̀ lọ Augustu, mo tí pinnu láti rán an lọ.
No niĩ nĩndonire atĩ ndarĩ ũndũ eekĩte wa gũtũma ooragwo, no tondũ nĩacookirie ciira riiko kũrĩ Mũthamaki, ngĩtua itua rĩa kũmũtũma Roma.
26 Ṣùgbọ́n èmi kò ri ohun kan dájúdájú láti kọ̀wé sí olúwa mi. Nítorí náà ni mo ṣe mú un jáde wá síwájú yín, àní síwájú rẹ ọba Agrippa, kí o fi jẹ́ pé lẹ́yìn tí a ba tí ṣe ìwádìí rẹ̀, èmi yóò lè rí ohun tí èmi yóò kọ.
No ndirĩ na ũndũ mũna ingĩandĩkĩra Mũthamaki Mũgaathe igũrũ rĩake. Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, ndamũrehe mbere yanyu inyuothe, na makĩria mbere yaku wee Mũthamaki Agiripa, nĩgeetha ũhoro ũyũ warĩkia gũtuĩrio, ngĩe na ũndũ ingĩandĩka.
27 Nítorí tí kò tọ́ ní ojú mi láti rán òǹdè, kí a má sì sọ ọ̀ràn tí a kà sí i lọ́rùn.”
Nĩgũkorwo ndikuona kwagĩrĩire gũtũma mũndũ muohe itekuonania maũndũ marĩa athitangĩirwo.”

< Acts 25 >