< Acts 22 >

1 “Ẹ̀yin ará àti baba, ẹ gbọ́ tí ẹnu mi nísinsin yìí.”
LALAJE mañelo yan mañaena, jingog y dumefiendeyo pago guiya jamyo!
2 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ pé ó ń bá wọn sọ̀rọ̀ ni èdè Aramaiki, wọ́n túbọ̀ dákẹ́ jẹ́ẹ́. Nígbà náà ni ó wí pé,
(Ya anae majungog na mancuinentuse sija ni y fino Hebreo, ninafanmamatquilo mas; ) ya ilegña:
3 “Júù ni èmi í ṣe, a bí mi ni Tarsu ìlú kan ní Kilikia, ṣùgbọ́n tí a tọ́ mi dàgbà ni ìlú yìí. Ní abẹ́ ẹsẹ̀ Gamalieli ni a sì gbé kọ́ mi ní òfin àwọn baba wa, tí mo sì ní ìtara fún Ọlọ́run àní gẹ́gẹ́ bí gbogbo yin tí rí ni òní.
Guajo magajet taotao na Judio, mafañagon Tarso, un siuda guiya Silisia; lao mapogsaeyo güine na siuda gui adeng Gamaliel, mafanagüeyo taemanoja y minagajet y lay y mañaenata, ya eggoyo para as Yuus, taegüenao iya jamyo pago na jaane.
4 Mo sì ṣe inúnibíni sí àwọn ènìyàn tí ń tọ ọ̀nà yìí dé ojú ikú wọn, mo dè tọkùnrin tobìnrin wọ́n, mo sì fi wọ́n sínú túbú,
Ya jupetsigue sija gui este jinanao asta junafanmapuno, jugogode ya juentrerega gui catset y lalaje yan y famalaoan.
5 àní bí olórí àlùfáà pẹ̀lú gbogbo àjọ àwọn alàgbà tí lè jẹ́ mi ní ẹ̀rí. Mo tilẹ̀ gba ìwé àṣẹ lọ́wọ́ wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn arákùnrin wọn ní Damasku láti mú àwọn tí ó wà níbẹ̀ ní dídè wá sí Jerusalẹmu, láti jẹ wọ́n ní yà.
Ya parejoja y magas mamale locue numaeyo testimonio, yan todo y manada y manamco: guinin iya sija locue nae manresibeyo catta para y mañelo, ya jumanaoyo para Damasco, para jucone ayo sija ni y sinedajo güije ya jugode guato Jerusalem para ufanmasapet.
6 “Bí èmi tí súnmọ́ etí Damasku níwọ̀n ọjọ́-kanrí, lójijì ìmọ́lẹ̀ ńlá láti ọ̀run wá mọ́lẹ̀ yí mi ká.
Ya susede anae jumajanaoyo, ya esta jijotyo para Damasco gui taloane, enseguidas manina güije guinin y langet un dangculon candet gui oriyajo,
7 Mo sì ṣubú lulẹ̀, mo sì gbọ́ ohùn kan tí ó wí fún mi pé, ‘Saulu, Saulu èéṣe tí ìwọ fi ń ṣe inúnibíni sí mi?’
Ya podongyo gui jilo tano, ya jujungog un inagang na ilegña nu guajo: Saulo, Saulo, sa jafa na unpetsisigueyo?
8 “Mo sì béèrè pé, ‘Ta ni ìwọ, Olúwa?’ “Ó sì dá mi lóhùn pé, ‘Èmi ni Jesu tí Nasareti, ẹni tí ìwọ ń ṣe inúnibíni sí.’
Ya juope ilegco: Jayejao Señot? Ya ilegña nu güajo: Guajo si Jesus Nasareno ni y unpetsisigue.
9 Àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú mi rí ìmọ́lẹ̀ náà nítòótọ́, ṣùgbọ́n wọn kò gbọ́ ohùn ẹni tí ń bá mi sọ̀rọ̀.
Ya ayo y mangachochongjo jalie magajet y candet, ya ninafanmaañao; lao ti jajungog y inagang ayo y cumuentuseyo.
10 “Mo sí béèrè pé, ‘Kín ni kí èmí kí ó ṣe, Olúwa?’ “Olúwa sì wí fún mi pé, ‘Dìde, kí o sì lọ sí Damasku; níbẹ̀ ni a ó sì ti sọ ohun gbogbo fún ọ tí a yàn fún ọ láti ṣe.’
Ya ilegco: Jafa jufatinas Señot? Ya y Señot ilegña nu guajo: Cajulo ya janao falag Damasco; ya ayonae umasangane todo güinaja ni y matancho para chechomo.
11 Àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú mi fà mí lọ́wọ́ wọ Damasku lọ nítorí tí èmi kò lè ríran nítorí ìtànṣán ìmọ́lẹ̀ náà ti fọ́ mi ní ojú.
Ya anae ti siñayo manlie pot y minalag y candet, mapipetyo ni ayo sija y guinin mangachochongjo, ya maconeyo guato Damasco.
12 “Ọkùnrin kan tí a ń pè ní Anania tọ̀ mí wá, ẹni tó jẹ́ olùfọkànsìn ti òfin, tí ó sì lórúkọ rere lọ́dọ̀ gbogbo àwọn Júù tí ó ń gbé ibẹ̀.
Ya si Ananias, un taotao na deboto jaftaemanoja y lay, ya guaja mauleg na testimonio para todo y Judios sija ni y mañasaga güije,
13 Ó sì dúró tì mí, ó sì wí fún mi pé, ‘Arákùnrin Saulu, gba ìríran!’ Ní ẹsẹ̀ kan náà, mo sì ṣí ojú sí òkè mo sì lè rí i.
Mato guiya guajo, ya tumojgue, ya ilegña nu guajo: Chelujo Saulo, resibe y liniemo. Ya ayoja na ora nae juatan güe.
14 “Nígbà náà ni ó wí pé: ‘Ọlọ́run àwọn baba wa ti yàn ọ́ láti mọ ìfẹ́ rẹ̀, àti láti ri Ẹni òdodo náà, àti láti gbọ́ ọ̀rọ̀ láti ẹnu rẹ̀.
Ya ilegña: Y Yuus mañaenata umayegjao, na para untungo y minalagoña, ya unlie Ayo Tunas, yan unjungog y inagang y pachotña.
15 Ìwọ yóò jẹ́ ẹlẹ́rìí rẹ̀ fún gbogbo ènìyàn, nínú ohun tí ìwọ tí rí tí ìwọ sì ti gbọ́.
Sa jago utestiguña todo gui taotao, jafa y liniemo yan y jiningogmo.
16 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, kín ni ìwọ ń dúró dè? Dìde, kí a sì bamitiisi rẹ̀, kí ó sì wẹ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nù, kí ó sì máa pe orúkọ rẹ̀.’
Ya pago jafa na sumasagajaoja? Cajulo ya unmatagpange, ya ufinagase y isaomo, agang y naanña.
17 “Nígbà tí mo padà wá sí Jerusalẹmu tí mo ǹ gbàdúrà ní tẹmpili, mo bọ́ sí ojúran,
Ya susede anae tumaloyo guato Jerusalem, ya mientras mananaetaeyo gui templo, malingo y jinasoco,
18 mo sì rí Olúwa, ó ń sọ̀rọ̀ fún mi pé, ‘Kíá! Jáde kúrò ní Jerusalẹmu kánkán, nítorí wọn kì yóò gba ẹ̀rí rẹ nípa mi gbọ́.’
Ya julie güe, ya ilegña nu guajo: Laguse, ya unjanao juyong Jerusalem; sa ti manmalago maresibe y testemoniumo pot guajo.
19 “Èmi sì wí pé, ‘Olúwa, àwọn ènìyàn wọ̀nyí pàápàá mọ̀ pé èmi ti lọ láti inú Sinagọgu kan sí èkejì láti máa sọ wọ́n sínú túbú àti láti máa lu àwọn tí ó gbà ọ́ gbọ́.
Ya ilegco: Señot, jatungoja sija na manpresoyo yan mañaulag gui cada sinagoga ni ayo sija y jumonggue jao;
20 Nígbà tí a sì ta ẹ̀jẹ̀ Stefanu ẹlẹ́rìí rẹ sílẹ̀, èmi náà pẹ̀lú dúró níbẹ̀, mo sì ní ohùn sí ikú rẹ̀, mo sì ń ṣe ìtọ́jú aṣọ àwọn ẹni tí ó pa á.’
Ya anae machuda y jâgâ Esteban ni y testigomo, estabajayo na tumotojgue gui oriya, ya jucousienteja y mapunoña, ya juadaje y magagon ayo sija y pumuno güe.
21 “Nígbà náà ni Olúwa wí fún mi pé, ‘Máa lọ; nítorí èmi ó rán ọ sí àwọn aláìkọlà lókèèrè réré.’”
Ya ilegña nu guajo: Janao; sa guajo tumagojao chago desde este para y Gentiles.
22 Wọ́n sì fi etí sí ọ̀rọ̀ Paulu títí tí ó fi sọ ọ̀rọ̀ yìí. Nígbà yìí ni wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sì kígbe wí pé, “Ẹ mu ẹni yìí kúrò láyé! Kò yẹ kí ó wà láààyè!”
Ya majungog güe asta este na sinangan, ya entonses jajatsa y inagangñija, ya ilegñija: Najanao ayo na taotao gui jilo tano, sa ti combiene na ulâlâ.
23 Bí wọ́n sì ti ń kígbe, tí wọ́n sì ń jú aṣọ wọn káàkiri, tí wọ́n ń ku eruku sí ojú ọ̀run,
Ya anae managang, yan jayute y magagonñija, ya manmanyute oda gui aire,
24 olórí ogun pàṣẹ pé kí a mú Paulu wá sínú àgọ́ àwọn ológun. Ó sì pàṣẹ kí wọ́n ó lù ú, kí wọn fi ọ̀rọ̀ wa lẹ́nu wò, kí òun ba à lè mọ ìdí tí wọ́n fi ń kígbe lé e lórí bẹ́ẹ̀.
Y magas inetnon jatago na umacone güe guato gui jalom castiyo, ya manago na umasaulag para umaegsamina, para utungo pot jafa causa na manaagang contra güiya.
25 Bí wọ́n sí tí fi ọṣán dè é, Paulu bí balógun ọ̀rún tí ó dúró tì í pé, “Ó ha tọ́ fún yín láti na ẹni tí i ṣe ará Romu ni àìdálẹ́bi bí?”
Ya anae magode güe ni y coreas, ilegña si Pablo ni y senturion ni y tumotojgue gui oriya: Tunas para jago na unsaulag un taotao na Romano sin umacondena?
26 Nígbà tí balógun ọ̀rún sì gbọ́ èyí, ó lọ wí fún olórí ogun pé, “Kín ni ó fẹ́ ṣe yìí: nítorí ọkùnrin yìí ará Romu ní i ṣe?”
Ya anae jajungog ayo y senturion, mapos ya jasangane y magas inetnon ilegña: Adaje jafa y unquequechogüe, sa este na taotao Romano.
27 Alábojútó-ogun sì dé, ó sì bí Paulu pé, “Sọ fún mi, ará Romu ni ìwọ jẹ́ bí?” Ó sì wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni.”
Ayonae y magas inetnon mato ya ilegña: Sanganeyo, jago Romano? Ya güiya ilegña: Junggan.
28 Alábojútó-ogun sì dáhùn wí pé, “Owó púpọ̀ ni mo fi ra ọlá ìbílẹ̀ yìí.” Paulu wí pé, “Ṣùgbọ́n a bí mi sínú rẹ̀ ni.”
Ya y magas inetnon manope ilegña: Pot y minegae salape na juchule este na linebre. Ya si Pablo ilegña: Lao guajo Romanoyo na finañago.
29 Nítorí náà àwọn tí ó múra láti fi ọ̀rọ̀ wa lẹ́nu wò fàsẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀: lójúkan náà. Olórí ogun pẹ̀lú sì bẹ̀rù nígbà tí ó mọ̀ pé ọmọ ìbílẹ̀ Romu ní Paulu i ṣe, àti nítorí ó tí dè é.
Ayonae manjanao guiya güiya ayo sija y para umegsamina güe: ya y magas inetnon ninamaañao locue, despues di jatungo na Romano, sa güiya munamagode.
30 Ní ọjọ́ kejì, nítorí tí olórí ogun fẹ́ mọ̀ dájúdájú ohun tí àwọn Júù ń fi Paulu sùn sí, ó tú u sílẹ̀, ó pàṣẹ kí àwọn olórí àlùfáà àti gbogbo ìgbìmọ̀ péjọ, nígbà náà ni ó mú Paulu sọ̀kalẹ̀, ó sì mú un dúró níwájú wọn.
Ya y inagpaña, malago na utungo magajet cao jafa na mafaaela güe ni y Judios, ya masotta gui mapresuña, ya manago na ufanmato y magas mamale, yan y mangachongña, ya macone papa si Pablo ya mapolo gui menañija.

< Acts 22 >