< Acts 20 >

1 Nígbà tí ariwo náà sí rọlẹ̀, Paulu ránṣẹ́ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú, ó dágbére fún wọn, ó dìde láti lọ sí Makedonia.
A pošto se utiša buna, dozva Pavle uèenike, i utješivši ih oprosti se s njima, i iziðe da ide u Maæedoniju.
2 Nígbà tí ó sì tí la apá ìhà wọ̀nyí kọjá, tí ó sì ti fi ọ̀rọ̀ púpọ̀ gbà wọ́n ní ìyànjú, ó wá sí ilẹ̀ Giriki.
I prošavši one zemlje, i svjetovavši ih mnogijem rijeèima, doðe u Grèku.
3 Ó sì dúró níbẹ̀ ní oṣù mẹ́ta, nígbà tí àwọn Júù sì dènà dè é, bí ó ti ń pète àti bá ọkọ̀ ojú omi lọ sí Siria, ó pinnu rẹ̀ láti gbà Makedonia padà lọ.
Poživljevši pak onamo tri mjeseca stadoše mu Jevreji raditi o glavi kad šæaše da se odveze u Siriju, i namisli da se vrati preko Maæedonije.
4 Sopateru ará Berea ọmọ Pirusi sì bá a lọ dé Asia, àti nínú àwọn ará Tẹsalonika, Aristarku àti Sekundu, àti Gaiusi ará Dabe, àti Timotiu; Tikiku àti Tirofimu ará Asia.
I poðe s njim do Azije Sosipatar Pirov iz Verije, i Aristarh i Sekund iz Soluna, i Gaj iz Derve i Timotije, i Tihik i Trofim iz Azije.
5 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí tí lọ síwájú, wọ́n dúró dè wá ni Troasi.
Ovi otišavši naprijed èekahu nas u Troadi.
6 Àwa sì ṣíkọ̀ láti Filipi lọ lẹ́yìn àjọ àìwúkàrà, a sì dé ọ̀dọ̀ wọn ní Troasi ni ọjọ́ méje.
A mi se odvezosmo poslije dana prijesnijeh hljebova iz Filibe, i doðosmo k njima u Troadu za pet dana, i ondje ostasmo sedam dana.
7 Ọjọ́ èkínní ọ̀sẹ̀ nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn péjọ láti bu àkàrà, Paulu sì wàásù fún wọn, ó múra láti lọ ní ọjọ́ kejì: ó sì fa ọ̀rọ̀ rẹ̀ gùn títí di àárín ọ̀gànjọ́.
A u prvi dan nedjelje, kad se sabraše uèenici da lome hljeb, govoraše im Pavle, jer šæaše sjutradan da poðe, i proteže besjedu do ponoæi.
8 Fìtílà púpọ̀ sì wà ní iyàrá òkè náà, níbi tí wọn gbé péjọ sí.
I bijahu mnoge svijeæe gore u sobi gdje se bijasmo sabrali.
9 Ọ̀dọ́mọkùnrin kan tí a ń pè ní Eutiku sì jókòó lójú fèrèsé, oorun sì wọ̀ ọ́ lára; bí Paulu sì ti pẹ́ ní ìwàásù, ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lójú oorun, ó ṣubú láti òkè kẹta wá sílẹ̀, a sì gbé e dìde ní òkú.
A sjeðaše na prozoru jedno momèe, po imenu Evtih, nadvladano od tvrdoga sna, i kad Pavle govoraše mnogo, naže se u snu i pade dolje s treæega poda, i digoše ga mrtva.
10 Nígbà tí Paulu sì sọ̀kalẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ tì i, ó sì gbé e mọ́ra, ó ní, “Ẹ má ṣe yọ ara yín lẹ́nu; nítorí tí òun wà láààyè.”
A Pavle sišavši pade na nj, i zagrlivši ga reèe: ne bunite se, jer je duša njegova u njemu.
11 Nígbà tí ó sì tún gòkè lọ, ó sì jẹ oúnjẹ Olúwa, ó sì sọ̀rọ̀ pẹ́ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́, nígbà náà ni ó sì lọ.
Onda iziðe gore, i prelomivši hljeb okusi, i dovoljno govori do same zore, i tako otide.
12 Wọ́n sì mú ọmọkùnrin náà lọ sílẹ̀ láààyè, inú gbogbo wọn sì dùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
A momèe dovedoše živo, i utješiše se ne malo.
13 Nígbà ti àwa sì ṣáájú, àwa sì ṣíkọ̀ lọ sì Asosi, níbẹ̀ ni a ti lérò láti gba Paulu sínú ọkọ̀: nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó tí pinnu rẹ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ bá ti ọ̀nà-ẹsẹ̀ lọ.
A mi došavši u laðu odvezosmo se u As, i odande šæasmo da uzmemo Pavla; jer tako bješe zapovjedio, hoteæi sam da ide pješice.
14 Nígbà tí ó sì pàdé wa ní Asosi, a gbà á sínú ọkọ̀, a sì wá sí Miletu.
A kad se sasta s nama u Asu, uzesmo ga, i doðosmo u Mitilinu.
15 Nígbà tí a sì ṣíkọ̀ kúrò níbẹ̀, ní ọjọ́ kejì a dé ọ̀kánkán Kiosi; ní ọjọ́ kejì rẹ̀ a dé Samosi, ni ọjọ́ kejì rẹ̀ a sì dé Miletu.
I odande odvezavši se doðosmo sjutradan prema Hiju; a drugi dan odvezosmo se u Sam, i noæismo u Trigiliju; i sjutradan doðosmo u Milit.
16 Paulu ṣa ti pinnu rẹ̀ láti bá ọkọ̀ ojú omi kọjá sí Efesu, nítorí ki ó má ba à lo àkókò kankan ni Asia: nítorí tí ó ń yára bí yóò ṣe ṣe é ṣe fún un láti wà ní Jerusalẹmu lọ́jọ́ Pentikosti.
Jer Pavle namisli da proðemo mimo Efes da se ne bi zadržao u Aziji; jer hiæaše, ako bude moguæe, da bude o Trojièinu dne u Jerusalimu.
17 Ní àti Miletu ni Paulu ti ránṣẹ́ sí Efesu, láti pé àwọn alàgbà ìjọ wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ali iz Milita posla u Efes i dozva starješine crkvene.
18 Nígbà tí wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin tìkára yín mọ̀, láti ọjọ́ kìn-ín-ní tí mo tí dé Asia, bí mo ti bá yín gbé, ní gbogbo àkókò náà.
I kad doðoše k njemu, reèe im: vi znate od prvoga dana kad doðoh u Aziju kako s vama jednako bih
19 Bí mo ti ń fi ìrẹ̀lẹ̀ inú gbogbo sin Olúwa, àti omijé púpọ̀, pẹ̀lú ìdánwò, tí ó bá mi, nípa rìkíṣí àwọn Júù.
Služeæi Gospodu sa svakom poniznosti i mnogijem suzama i napastima koje mi se dogodiše od Jevreja koji mi raðahu o glavi;
20 Bí èmí kò ti fàsẹ́yìn láti sọ ohunkóhun tí ó ṣàǹfààní fún un yín, àti láti máa kọ́ ọ yín ní gbangba àti láti ilé dé ilé.
Kako ništa korisno ne izostavih da vam ne kažem i da vas nauèim pred narodom i po kuæama,
21 Tí mo ń sọ fún àwọn Júù, àti fún àwọn Giriki pẹ̀lú, ní ti ìrònúpìwàdà sí Ọlọ́run, àti ti ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi Olúwa wa.
Svjedoèeæi i Jevrejima i Grcima pokajanje k Bogu i vjeru u Gospoda našega Isusa Hrista.
22 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, ẹ̀mí mi ń fà sì Jerusalẹmu, láìmọ̀ ohun tí yóò bá mi níbẹ̀.
I sad evo ja svezan Duhom idem u Jerusalim ne znajuæi šta æe mi se u njemu dogoditi;
23 Bí kò ṣe bí Ẹ̀mí Mímọ́ tí ń sọ ní ìlú gbogbo pé, ìdè àti ìyà ń bẹ fún mi.
Osim da Duh sveti po svijem gradovima svjedoèi, govoreæi da me okovi i nevolje èekaju.
24 Ṣùgbọ́n èmi kò ka ọkàn mi sí nǹkan rárá bi ohun tí ó ṣọ̀wọ́n fún mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí mo tí gbà lọ́dọ̀ Jesu Olúwa, láti máa ròyìn ìyìnrere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
Ali se ni za što ne brinem, niti marim za svoj život, nego da svršim teèenje svoje s radošæu i službu koju primih od Gospoda Isusa: da posvjedoèim jevanðelje blagodati Božije.
25 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, èmi mọ̀ pé gbogbo yín, láàrín ẹni tí èmi tí ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, kì yóò rí ojú mi mọ́.
I evo sad znam da više neæete vidjeti mojega lica, vi svi po kojima prolazih propovijedajuæi carstvo Božije.
26 Nítorí náà mo pè yín ṣe ẹlẹ́rìí lónìí yìí pé, ọrùn mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn gbogbo.
Zato vam svjedoèim u današnji dan da sam ja èist od krvi sviju;
27 Nítorí tí èmi kò fàsẹ́yìn láti sọ gbogbo ìpinnu Ọlọ́run fún un yin.
Jer ne izostavih da pokažem volju Božiju.
28 Ẹ kíyèsára yin, àti sí gbogbo agbo tí Ẹ̀mí Mímọ́ fi yín ṣe alábojútó rẹ̀, láti máa tọ́jú ìjọ Ọlọ́run, tí ó tí fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ rà.
Pazite dakle na sebe i na sve stado u kome vas Duh sveti postavi vladikama da pasete crkvu Gospoda i Boga koju steèe krvlju svojom;
29 Nítorí tí èmi mọ̀ pé, lẹ́yìn lílọ mi, ìkookò búburú yóò wọ àárín yín, yóò sì tú agbo ká.
Jer ja ovo znam da æe po odlasku mome uæi meðu vas teški vuci koji neæe štedjeti stada;
30 Láàrín ẹ̀yin tìkára yín ni àwọn ènìyàn yóò sì dìde, tí wọn yóò máa sọ̀rọ̀-òdì, láti fa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sẹ́yìn wọn.
I izmeðu vas samijeh postaæe ljudi koji æe govoriti izvrnutu nauku da odvraæaju uèenike za sobom.
31 Nítorí náà ẹ máa ṣọ́ra, ki ẹ sì máa rántí pé, fún ọdún mẹ́ta, èmi kò dẹ́kun láti máa fi omijé kìlọ̀ fún olúkúlùkù ní ọ̀sán àti ní òru.
Zato gledajte i opominjite se da tri godine dan i noæ ne prestajah uèeæi sa suzama svakoga od vas.
32 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo fi yín lé Ọlọ́run lọ́wọ́ àti ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, tí ó lè gbé yín dúró, tí ó sì lè fún yín ní ìní láàrín gbogbo àwọn tí a sọ di mímọ́.
I sad vas, braæo, predajem Bogu i rijeèi blagodati njegove, koji može nazidati i dati vam našljedstvo meðu svima osveæenima.
33 Èmí kò ṣe ojúkòkòrò fàdákà, tàbí wúrà, tàbí aṣọ ẹnikẹ́ni.
Srebra, ili zlata, ili ruha ni u jednoga ne zaiskah.
34 Ẹ̀yin tìkára yín sá à mọ̀ pé, ọwọ́ mi wọ̀nyí ni mo fi ṣiṣẹ́ láti fi pèsè fún àìní mi, àti tí àwọn tí ó wà pẹ̀lú mi.
Sami znate da potrebi mojoj i onijeh koji su sa mnom bili poslužiše ove ruke moje.
35 Nínú ohun gbogbo mo fi àpẹẹrẹ fún un yín pé, nípa ṣíṣe iṣẹ́ bẹ́ẹ̀, ó yẹ kí ẹ máa ran àwọn aláìlera lọ́wọ́, ki ẹ sì máa rántí ọ̀rọ̀ Jesu Olúwa, bí òun tìkára rẹ̀ tí wí pé, ‘Láti fún ni ní ìbùkún ju láti gbà lọ.’”
Sve vam pokazah da se tako valja truditi i pomagati nemoænima, i opominjati se rijeèi Gospoda Isusa koju on reèe: mnogo je blaženije davati negoli uzimati.
36 Nígbà tí ó sì tí wí nǹkan wọ̀nyí, ó kúnlẹ̀, ó sì bá gbogbo wọn gbàdúrà.
I ovo rekavši kleèe na koljena svoja sa svima njima i pomoli se Bogu.
37 Gbogbo wọn sì sọkún gidigidi, wọ́n sì rọ̀ mọ́ Paulu lọ́rùn, wọ́n sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
A sviju stade veliki plaè i zagrlivši Pavla cjelivahu ga,
38 Inú wọn sì bàjẹ́ jùlọ fún ọ̀rọ̀ tí ó sọ pé, wọn kì yóò rí ojú òun mọ́, wọ́n sì sìn ín títí dé inú ọkọ̀.
Žalosni najviše za rijeè koju reèe da više neæe vidjeti lica njegova; i otpratiše ga u laðu.

< Acts 20 >