< Acts 20 >

1 Nígbà tí ariwo náà sí rọlẹ̀, Paulu ránṣẹ́ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú, ó dágbére fún wọn, ó dìde láti lọ sí Makedonia.
Nazyamaliha efujo zila uPaulo wabhakwizya amanyili wabhazinzya amoyo wabhalaga wabhala hu Makedonia.
2 Nígbà tí ó sì tí la apá ìhà wọ̀nyí kọjá, tí ó sì ti fi ọ̀rọ̀ púpọ̀ gbà wọ́n ní ìyànjú, ó wá sí ilẹ̀ Giriki.
Nawashila amikoa ego abhazinzya amoyo amanyili wabhala hu Yunani.
3 Ó sì dúró níbẹ̀ ní oṣù mẹ́ta, nígbà tí àwọn Júù sì dènà dè é, bí ó ti ń pète àti bá ọkọ̀ ojú omi lọ sí Siria, ó pinnu rẹ̀ láti gbà Makedonia padà lọ.
Pawakhala amezi gatatu zyahapangwa embibhi na Wayahudi napalamilaga ashuule hwidala lya muminzi, abhale hu Shamu, sigawabhala uhwo washilila hu Makedonia.
4 Sopateru ará Berea ọmọ Pirusi sì bá a lọ dé Asia, àti nínú àwọn ará Tẹsalonika, Aristarku àti Sekundu, àti Gaiusi ará Dabe, àti Timotiu; Tikiku àti Tirofimu ará Asia.
Bhashulile nabho paka hu Asia bhahali bha Sopatro, mwana wa Pirho yafumile hu Berea; Aristariko nu Sekundo, bhonti bhafumile hwa akristi bha hu Thesalonike; Gayo wa hu Derbe; u Timotheo; Tikiko nu Trofimo bhafumile hu Asia.
5 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí tí lọ síwájú, wọ́n dúró dè wá ni Troasi.
Lelo abhantu ebha bhatagaliye bhatihulaga hula hu Troa.
6 Àwa sì ṣíkọ̀ láti Filipi lọ lẹ́yìn àjọ àìwúkàrà, a sì dé ọ̀dọ̀ wọn ní Troasi ni ọjọ́ méje.
Hwidala ilya minzi afume hu Filipi nazyashila ensiku ezye mabumunda gasi gabhaponyizye ehamila isiku ilya sanu tafiha hu Troa. Taakhiye uhwo ensiku saba.
7 Ọjọ́ èkínní ọ̀sẹ̀ nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn péjọ láti bu àkàrà, Paulu sì wàásù fún wọn, ó múra láti lọ ní ọjọ́ kejì: ó sì fa ọ̀rọ̀ rẹ̀ gùn títí di àárín ọ̀gànjọ́.
Isiku ila muhungu patabhuungine alye amabumunda, u Paulo alumbiliye na Waamini. Alikuwa akipanga kuondoka kesho yake, hivyo akaendelea kuongea tee paka nu siku uwapahati.
8 Fìtílà púpọ̀ sì wà ní iyàrá òkè náà, níbi tí wọn gbé péjọ sí.
Zyahali ihozyo zinyinji hwatakhiye hwigulu.
9 Ọ̀dọ́mọkùnrin kan tí a ń pè ní Eutiku sì jókòó lójú fèrèsé, oorun sì wọ̀ ọ́ lára; bí Paulu sì ti pẹ́ ní ìwàásù, ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lójú oorun, ó ṣubú láti òkè kẹta wá sílẹ̀, a sì gbé e dìde ní òkú.
U kijana umo itawa lyakwe yu Utiko, akhiitwe nu tulo akhiiye ambali pidilisha pamande walagala pansi afume igulu ilya tatu na bhabhala hutole bhega afwiye.
10 Nígbà tí Paulu sì sọ̀kalẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ tì i, ó sì gbé e mọ́ra, ó ní, “Ẹ má ṣe yọ ara yín lẹ́nu; nítorí tí òun wà láààyè.”
Lelo uPaulo wope wiha pansi, wa hwigolosya puula ufwe wabhabhuula waga musahiile umwoyo unu mwomi.”
11 Nígbà tí ó sì tún gòkè lọ, ó sì jẹ oúnjẹ Olúwa, ó sì sọ̀rọ̀ pẹ́ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́, nígbà náà ni ó sì lọ.
Wazubha hwigulu antele wamensula ibumunda walya nawayanga nabho paka ninzansha wasogola.
12 Wọ́n sì mú ọmọkùnrin náà lọ sílẹ̀ láààyè, inú gbogbo wọn sì dùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Bhaleta ukijana ula shamwomi bhasungwa tee.
13 Nígbà ti àwa sì ṣáájú, àwa sì ṣíkọ̀ lọ sì Asosi, níbẹ̀ ni a ti lérò láti gba Paulu sínú ọkọ̀: nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó tí pinnu rẹ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ bá ti ọ̀nà-ẹsẹ̀ lọ.
Ate tatagaalila ne meli tabhala hu Aso, tapanjile humweje uPaulo, umwene ajendile hunsi inyoomu shapanjile umwene.
14 Nígbà tí ó sì pàdé wa ní Asosi, a gbà á sínú ọkọ̀, a sì wá sí Miletu.
Natatangana nawo Aso, tapashila mumeli tabhala nawo hu Mitilene.
15 Nígbà tí a sì ṣíkọ̀ kúrò níbẹ̀, ní ọjọ́ kejì a dé ọ̀kánkán Kiosi; ní ọjọ́ kejì rẹ̀ a dé Samosi, ni ọjọ́ kejì rẹ̀ a sì dé Miletu.
Ate tasogola afume uhwo isiku ilya bhili tafiha hu kisiwa she Kio. Isiku ilyamwabho tafiha hu kisiwa she Samo, shandao lwakwe tafiha hu Mileto.
16 Paulu ṣa ti pinnu rẹ̀ láti bá ọkọ̀ ojú omi kọjá sí Efesu, nítorí ki ó má ba à lo àkókò kankan ni Asia: nítorí tí ó ń yára bí yóò ṣe ṣe é ṣe fún un láti wà ní Jerusalẹmu lọ́jọ́ Pentikosti.
U Paulo ahamuya ashuulile ashilile hu Efeso, siga ahanzaga atumile umuda gwagwonti uhwo, ali nu piliganu uwabhale hu Yerusalemu hu shikulukulu she Pentekoste.
17 Ní àti Miletu ni Paulu ti ránṣẹ́ sí Efesu, láti pé àwọn alàgbà ìjọ wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Afume hu Mileto atumile abhantu hu Efeso nabhakwizye azee bhi kanisa.
18 Nígbà tí wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin tìkára yín mọ̀, láti ọjọ́ kìn-ín-ní tí mo tí dé Asia, bí mo ti bá yín gbé, ní gbogbo àkókò náà.
Nabhafiha wabhabhuula huje mwe mumenye ahwande pihandiye ulwahwande ahwinze ipa pa Asia shanahali hulimwe ensiku zyonti.
19 Bí mo ti ń fi ìrẹ̀lẹ̀ inú gbogbo sin Olúwa, àti omijé púpọ̀, pẹ̀lú ìdánwò, tí ó bá mi, nípa rìkíṣí àwọn Júù.
Imbombile imbombo ya Ngulubhi huunyenyekevu wonti na hwiyisye na humansozi na malabha gaganajile hwa Yahudi.
20 Bí èmí kò ti fàsẹ́yìn láti sọ ohunkóhun tí ó ṣàǹfààní fún un yín, àti láti máa kọ́ ọ yín ní gbangba àti láti ilé dé ilé.
Mumenye shanali mwigushe hulimwe, ihabhabhuulaga shila hantu, sigana bhafishile nahamo najendaga shila nyumba abhamanyizye.
21 Tí mo ń sọ fún àwọn Júù, àti fún àwọn Giriki pẹ̀lú, ní ti ìrònúpìwàdà sí Ọlọ́run, àti ti ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi Olúwa wa.
Mumenye shanabhadamilaga Ayahudi na Yunani, aje bhalambe na humwitishe Ungulubhi bhabhe nu lwitiho hwa Yesu Kilisti.
22 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, ẹ̀mí mi ń fà sì Jerusalẹmu, láìmọ̀ ohun tí yóò bá mi níbẹ̀.
Enyii eshi ane shehumweteha Umpepo Ufinjile aje embale hu Yerusalemu nantele sigaaenzimenye zyazibhanaje uhwo,
23 Bí kò ṣe bí Ẹ̀mí Mímọ́ tí ń sọ ní ìlú gbogbo pé, ìdè àti ìyà ń bẹ fún mi.
pipo Umpepo Ufinjile ambuula shila muji gwimbala huje empengo zihuguula, na malabha.
24 Ṣùgbọ́n èmi kò ka ọkàn mi sí nǹkan rárá bi ohun tí ó ṣọ̀wọ́n fún mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí mo tí gbà lọ́dọ̀ Jesu Olúwa, láti máa ròyìn ìyìnrere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
Lelo ane siga insibiliye amaisha gane huje gali ne thamani ani ihwanza aje imale imbombo yakwe sheshinza yamahejeliya huwa mwene uYesu Kilisti naiyanje ineema ya Ngulubhi.
25 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, èmi mọ̀ pé gbogbo yín, láàrín ẹni tí èmi tí ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, kì yóò rí ojú mi mọ́.
Eshi, enyaa, bhaala bhonti, bhanabha bhuulile izu lya Ngulubhi sigamwaindola amaso gane nantele.
26 Nítorí náà mo pè yín ṣe ẹlẹ́rìí lónìí yìí pé, ọrùn mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn gbogbo.
Embabhuula eshi huje sigana iongwa hushauli yenyu.
27 Nítorí tí èmi kò fàsẹ́yìn láti sọ gbogbo ìpinnu Ọlọ́run fún un yin.
Ane sigahwizu wiliye abhabhuule izu lya Ngulubhi.
28 Ẹ kíyèsára yin, àti sí gbogbo agbo tí Ẹ̀mí Mímọ́ fi yín ṣe alábojútó rẹ̀, láti máa tọ́jú ìjọ Ọlọ́run, tí ó tí fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ rà.
Eshi mubhanje maso mubhene hwa mubhene nalila ipuga Ungulubhi lya bhapiiye aje mulidimaje, mulyenyaje ipuga lya Yesu lyalikalile hwidanda lyake yuyo.
29 Nítorí tí èmi mọ̀ pé, lẹ́yìn lílọ mi, ìkookò búburú yóò wọ àárín yín, yóò sì tú agbo ká.
Iminye huje ane nanasogola enkanyaga zyayinza sigazyaibhasajila.
30 Láàrín ẹ̀yin tìkára yín ni àwọn ènìyàn yóò sì dìde, tí wọn yóò máa sọ̀rọ̀-òdì, láti fa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sẹ́yìn wọn.
Iminye huje bhamo mulimwe mwomu bhaibha bhabhaibhatezya aje mubhalondozyoje abhene.
31 Nítorí náà ẹ máa ṣọ́ra, ki ẹ sì máa rántí pé, fún ọdún mẹ́ta, èmi kò dẹ́kun láti máa fi omijé kìlọ̀ fún olúkúlùkù ní ọ̀sán àti ní òru.
mubhe maso. Ane siganaleshile abhamanyizye shila muntu nabhamanyizizye usiku na pasanya.
32 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo fi yín lé Ọlọ́run lọ́wọ́ àti ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, tí ó lè gbé yín dúró, tí ó sì lè fún yín ní ìní láàrín gbogbo àwọn tí a sọ di mímọ́.
Eshi ane embabhiha hwa Ngulubhi na hwizu elyelusajilo lwakwe lyalibhajiye abhzenje nabhapele ugaali nabhabhishe bhafinje hwa Ngulubhi.
33 Èmí kò ṣe ojúkòkòrò fàdákà, tàbí wúrà, tàbí aṣọ ẹnikẹ́ni.
Siga nazilishe ihela, edhahabu na menda.
34 Ẹ̀yin tìkára yín sá à mọ̀ pé, ọwọ́ mi wọ̀nyí ni mo fi ṣiṣẹ́ láti fi pèsè fún àìní mi, àti tí àwọn tí ó wà pẹ̀lú mi.
Mumenye huje amakhono gane gampeliile vyanahanzaga nabhombaga imbombo nabhavwe abhanji bhabhali pamo nanee.
35 Nínú ohun gbogbo mo fi àpẹẹrẹ fún un yín pé, nípa ṣíṣe iṣẹ́ bẹ́ẹ̀, ó yẹ kí ẹ máa ran àwọn aláìlera lọ́wọ́, ki ẹ sì máa rántí ọ̀rọ̀ Jesu Olúwa, bí òun tìkára rẹ̀ tí wí pé, ‘Láti fún ni ní ìbùkún ju láti gbà lọ.’”
Nabhamanyizizye abhombe imbombo nabhavwe bhasigabhajiye abhombe embombo, ne manyizyo zya Yesu izyaje shinza afumye ashile aposhele.”
36 Nígbà tí ó sì tí wí nǹkan wọ̀nyí, ó kúnlẹ̀, ó sì bá gbogbo wọn gbàdúrà.
Nawayanga nabho wafugamila amafugamo uuta nabho.
37 Gbogbo wọn sì sọkún gidigidi, wọ́n sì rọ̀ mọ́ Paulu lọ́rùn, wọ́n sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
Bhonti bhalila bhagwila uPaulo munsingo bhabusu.
38 Inú wọn sì bàjẹ́ jùlọ fún ọ̀rọ̀ tí ó sọ pé, wọn kì yóò rí ojú òun mọ́, wọ́n sì sìn ín títí dé inú ọkọ̀.
Bhazugumiye tee payanjile huje siga mwaindo nantele amaso gane, bhalolela mumeli.

< Acts 20 >