< Acts 19 >

1 Nígbà ti Apollo wà ni Kọrinti, ti Paulu kọjá lọ sí apá òkè ìlú, ó sì wá sí Efesu, o sì rí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn kan;
Na rĩrĩ, hĩndĩ ĩyo Apolo arĩ kũu Korinitho, Paũlũ akĩgerera njĩra ĩrĩa yatuĩkanĩirie mwena wa rũgongo agĩthiĩ nginya Efeso. Aakinya kũu agĩkora arutwo amwe kuo.
2 o wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ha gba Ẹ̀mí Mímọ́ náà nígbà tí ẹ̀yin gbàgbọ́?” Wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò gbọ́ rárá pé Ẹ̀mí Mímọ́ kan wà.”
Akĩmooria atĩrĩ, “Nĩmwamũkĩrire Roho Mũtheru rĩrĩa mwetĩkirie?” Nao makĩmũcookeria atĩrĩ, “Aca, ithuĩ o na tũtirĩ twaigua atĩ nĩ kũrĩ Roho Mũtheru.”
3 Ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ irú bamitiisi wo ni a bamitiisi yín sí?” Wọ́n sì wí pé, “Sí bamitiisi tí Johanu.”
Nĩ ũndũ ũcio Paũlũ akĩmooria atĩrĩ, “Mwakĩbatithirio ũbatithio ũrĩkũ?” Nao makĩmũcookeria atĩrĩ, “Twabatithirio ũbatithio wa Johana.”
4 Paulu sí wí pé, “Nítòótọ́, ní Johanu fi bamitiisi tí ìrònúpìwàdà bamitiisi, ó ń wí fún àwọn ènìyàn pé, kí wọ́n gba ẹni tí ń bọ̀ lẹ́yìn òun gbọ́, èyí sì ni Kristi Jesu.”
Paũlũ akĩmeera atĩrĩ, “Ũbatithio wa Johana warĩ ũbatithio wa kwĩrira kwa mehia. Eeraga andũ metĩkie ũrĩa ũgũũka thuutha wake, nake nĩwe Jesũ.”
5 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́, a bamitiisi wọn lórúkọ Jesu Olúwa.
Rĩrĩa maaiguire ũguo, makĩbatithio thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Mwathani Jesũ.
6 Nígbà tí Paulu sì gbé ọwọ́ lé wọn, Ẹ̀mí Mímọ́ sì bà lé wọn, wọ́n sì ń fọ́ èdè mìíràn, wọ́n sì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa Paũlũ aamaigĩrĩire moko, Roho Mũtheru akĩmaikũrũkĩra, nao makĩaria na thiomi ingĩ na makĩratha mohoro.
7 Iye àwọn ọkùnrin náà gbogbo tó méjìlá.
Nao othe maarĩ ta andũ ikũmi na eerĩ.
8 Nígbà tí ó sì wọ inú Sinagọgu lọ ó fi ìgboyà sọ̀rọ̀ ni oṣù mẹ́ta, ó ń fi ọ̀rọ̀ wé ọ̀rọ̀, ó sì ń yí wọn lọ́kàn padà sí nǹkan tí i ṣe tí ìjọba Ọlọ́run.
Paũlũ agĩtoonya thunagogi, na ihinda rĩa mĩeri ĩtatũ akĩaria na ũcamba kuo, akĩgeragia kũringĩrĩria andũ ũhoro wa ũthamaki wa Ngai.
9 Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkàn àwọn mìíràn nínú wọn di líle, tí wọn kò sì gbàgbọ́, tí wọn ń sọ̀rọ̀ ibi sí ọ̀nà náà níwájú ìjọ ènìyàn, ó lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó sì ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sọ́tọ̀, ó sì ń sọ àsọyé lójoojúmọ́ ni ilé ìwé Tirannusi.
No amwe ao makĩũmia ngoro; makĩaga gwĩtĩkia na magĩcambia Njĩra ĩyo mbere ya kĩrĩndĩ. Nĩ ũndũ ũcio Paũlũ akĩmeherera. Akĩoya arutwo agĩthiĩ nao nyũmba ĩrĩa yathomithagĩrio andũ ya Turano, akaaranagĩria na andũ o mũthenya arĩ kuo.
10 Èyí n lọ bẹ́ẹ̀ fún ìwọ̀n ọdún méjì; tó bẹ́ẹ̀ tí gbogbo àwọn tí ń gbé Asia gbọ́ ọ̀rọ̀ Jesu Olúwa, àti àwọn Júù àti àwọn Giriki.
Ũndũ ũyũ nĩwathiire na mbere ihinda ta rĩa mĩaka ĩĩrĩ, o nginya Ayahudi na Ayunani othe arĩa maatũũraga bũrũri wa Asia makĩigua kiugo kĩa Mwathani.
11 Ọlọ́run sì tí ọwọ́ Paulu ṣe àwọn àkànṣe iṣẹ́ ìyanu,
Ngai nĩaringire ciama cia mwanya agereire harĩ Paũlũ,
12 tó bẹ́ẹ̀ tí a fi ń mú aṣọ àti aṣọ ìnuwọ́ rẹ̀ tọ àwọn ọlọkùnrùn lọ, ààrùn sì fi wọ́n sílẹ̀, àwọn ẹ̀mí búburú sì jáde kúrò lára wọn.
o nginya itambaya na nguo iria ciahutagia mwĩrĩ wake igatwarĩrwo andũ arĩa maarĩ arũaru, nao makahona mĩrimũ yao na ngoma thũku ikamatiga.
13 Ṣùgbọ́n àwọn Júù kan n lọ káàkiri láti máa le ẹ̀mí èṣù jáde, wọn dáwọ́lé àdábọwọ́ ara wọn, láti pé orúkọ Jesu Olúwa sí àwọn tí ó ni ẹ̀mí búburú, wí pé, “Àwa fi orúkọ Jesu tí Paulu ń wàásù fi yín bú.”
Na rĩrĩ, Ayahudi amwe arĩa maathiiaga makĩingataga ngoma thũku makĩgeria kũhũthĩra rĩĩtwa rĩa Mwathani Jesũ harĩ andũ arĩa maarĩ na ndaimono. Moigaga atĩrĩ, “Thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jesũ, ũrĩa ũhunjagio nĩ Paũlũ, ndagwatha uume.”
14 Àwọn méje kan sì wà, tí wọn ń ṣe bẹ́ẹ̀, àwọn ọmọ ẹnìkan tí a ń pè ni Sikẹfa, tí í ṣe olórí àlùfáà gíga láàrín àwọn Júù.
Ariũ mũgwanja a Mũyahudi wetagwo Sikeva, warĩ mũthĩnjĩri-Ngai mũnene, nĩmekaga ũguo.
15 Ẹ̀mí búburú náà sì dáhùn, ó ní “Jesu èmi mọ̀ ọ́n, mo sì mọ Paulu pẹ̀lú, ṣùgbọ́n ta ni ẹ̀yin?”
Mũthenya ũmwe, ngoma thũku ĩkĩmacookeria ĩkĩmeera atĩrĩ, “Jesũ nĩndĩmũũĩ na nĩnjũũĩ ũhoro wa Paũlũ, no inyuĩ mũrĩ a?”
16 Nígbà tí ọkùnrin tí ẹ̀mí búburú náà wà lára rẹ̀ sì fò mọ́ wọn, ó pa kúúrù mọ́ wọn, ó sì borí wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sá jáde kúrò ní ilé náà ní ìhòhò pẹ̀lú ni ìfarapa.
Hĩndĩ ĩyo mũndũ ũcio warĩ na ngoma thũku akĩmarũgĩrĩra akĩmatooria othe. Akĩmahũũra mũno nginya makiuma nyũmba ĩyo makĩũra marĩ njaga makiuraga thakame.
17 Ìròyìn yìí sì di mí mọ̀ fún gbogbo àwọn Júù àti àwọn ará Giriki pẹ̀lú tí ó ṣe àtìpó ní Efesu; ẹ̀rù sì ba gbogbo wọn, a sì gbé orúkọ Jesu Olúwa ga.
Rĩrĩa Ayahudi na Ayunani arĩa maatũũraga Efeso maamenyire ũhoro ũcio, othe makĩiyũrwo nĩ guoya, narĩo rĩĩtwa rĩa Mwathani Jesũ rĩgĩtũũgĩrio.
18 Ọ̀pọ̀ àwọn tí wọ́n gbàgbọ́ sì wá, wọ́n jẹ́wọ́, wọ́n sì fi iṣẹ́ wọn hàn.
Andũ aingĩ a arĩa meetĩkirie makĩyumĩria na makiumbũra waganu wao matekũhitha.
19 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn tí ń ṣe alálúpàyídà ni ó kó ìwé wọn jọ, wọ́n dáná sun wọ́n lójú gbogbo ènìyàn. Wọ́n sì ṣírò iye wọn, wọ́n sì rí i, ó jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìwọ̀n fàdákà.
Andũ aingĩ arĩa maaragũraga, magĩcookanĩrĩria mabuku mao na makĩmacinĩra mbere ya andũ othe. Rĩrĩa maatarire thogora wa mabuku macio, magĩkinyia durakima ngiri mĩrongo ĩtano.
20 Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ Olúwa gbèrú tí o sí gbilẹ̀ si í gidigidi.
Kiugo kĩa Mwathani gĩkĩhunja mũno na njĩra ĩyo na gĩkĩgĩa na hinya.
21 Ǹjẹ́ bí nǹkan wọ̀nyí tí parí tan, Paulu pinnu nínú ọkàn rẹ̀ pé, nígbà tí òun bá kọjá ní Makedonia àti Akaia, òun ó lọ sí Jerusalẹmu, ó wí pé, “Lẹ́yìn ìgbà tí mo bá dé ibẹ̀, èmi kò lè ṣàìmá dé Romu pẹ̀lú.”
Thuutha wa maũndũ macio mothe gwĩkĩka, Paũlũ agĩtua itua rĩa gũthiĩ Jerusalemu, atuĩkanĩirie Makedonia na Akaia. Akiuga atĩrĩ, “Ndaarĩkia gũkinya kũu, no nginya ngaacooka thiĩ Roma.”
22 Nígbà tí ó sì tí rán méjì nínú àwọn tí ń ṣe ìránṣẹ́ fún un lọ sí Makedonia, Timotiu àti Erastu, òun tìkára rẹ̀ dúró díẹ̀ ní ilẹ̀ Asia.
Agĩtũma andũ eerĩ a arĩa maamũteithagĩrĩria, na nĩo Timotheo na Erasito, mathiĩ Makedonia, nake agĩikaranga kũu bũrũri wa Asia gwa kahinda kanini.
23 Ní àkókò náà ìrúkèrúdò díẹ̀ kan wà nítorí ọ̀nà náà.
Ihinda-inĩ rĩu nĩ kwagĩire na thogothogo nene ĩkoniĩ ũhoro wa Njĩra ĩyo.
24 Nítorí ọkùnrin kan tí a ń pè ní Demetriusi, alágbẹ̀dẹ fàdákà, tí o máa ń fi fàdákà ṣe ilé òrìṣà fún Artemisi, ó mú ère tí kò mọ níwọ̀n wá fún àwọn oníṣọ̀nà.
Mũturi wa indo cia betha wetagwo Demeterio, ũrĩa wathondekaga tũmĩhianano twa betha twa Aritemi, nĩatũmaga andũ arĩa maaturaga indo icio magĩe na wonjoria mũnene.
25 Nígbà tí ó pè wọ́n jọ, àti irú àwọn oníṣẹ́-ọnà bẹ́ẹ̀, ó wí pé, “Alàgbà, ẹ̀yin mọ̀ pé nípa iṣẹ́ ọnà yìí ni àwa fi ní ọrọ̀ wa.
Nake agĩcookanĩrĩria andũ acio maaturaga indo icio, hamwe na aruti a wĩra arĩa maarutaga wĩra ũhaanaine na wao, akĩmeera atĩrĩ, “Andũ aya, inyuĩ nĩmũũĩ nĩtuonaga uumithio mũnene kuuma kũrĩ wonjoria ũyũ.
26 Ẹ̀yin sì rí i, ẹ sì gbọ́ pé, kì í ṣe ni Efesu nìkan ṣoṣo ni, ṣùgbọ́n ó fẹ́rẹ jẹ́ gbogbo Asia ni Paulu yìí ń yí ọ̀pọ̀ ènìyàn lọ́kàn padà, tí ó sì ń dárí wọn wí pé, ohun tí a fi ọwọ́ ṣe, kì í ṣe Ọlọ́run.
Na nĩmũrona na mũkaigua ũrĩa mũndũ ũyũ ũretwo Paũlũ aiguithĩtie na akahĩtithia andũ aingĩ gũkũ Efeso, na makĩria bũrũri wothe wa Asia akiugaga atĩ ngai iria ithondeketwo nĩ mũndũ ti ngai o na hanini.
27 Kì í sì ṣe pé kìkì iṣẹ́ ọnà wa yìí ni ó wà nínú ewu dídí asán; ṣùgbọ́n tẹmpili Artemisi òrìṣà ńlá yóò di gígàn pẹ̀lú, àti gbogbo ọláńlá rẹ̀ yóò sì run, ẹni tí gbogbo Asia àti gbogbo ayé ń bọ.”
Ũgwati ũrĩa ũrĩ ho nĩ atĩ to wonjoria witũ wiki ũkũmenererio, no o na hekarũ ya ngai ya mũndũ-wa-nja ĩrĩa nene ĩĩtagwo Aritemi nĩĩkwagithio kĩene, na ngai ĩyo ya mũndũ-wa-nja yo nyene, ĩrĩa ĩhooyagwo bũrũri-inĩ wothe wa Asia, na thĩ yothe, nĩĩkũimwo ũkaru wayo.”
28 Nígbà tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n kún fún ìbínú, wọ́n kígbe, wí pé, “Òrìṣà ńlá ni Artemisi ti ará Efesu!”
Rĩrĩa maaiguire ũguo, makĩngʼũrĩka mũno na makĩanĩrĩra, makiugaga atĩrĩ: “Aritemi wa Aefeso nĩ mũnene!”
29 Gbogbo ìlú náà sì kún fún ìrúkèrúdò: wọ́n sì fi ọkàn kan rọ́ wọn sí inú ilé ìṣeré, wọ́n sì mú Gaiusi àti Aristarku ara Makedonia, àwọn ẹlẹgbẹ́ Paulu nínú ìrìnàjò.
Na thuutha wa kahinda kanini itũũra rĩu rĩkĩiyũra inegene. Andũ acio othe makĩnyiita Gayo na Arisitariko arĩa moimĩte Makedonia na Paũlũ, nao makĩhanyũka marĩ ngoro ĩmwe magĩtoonya nyũmba ĩrĩa yagomanagwo nĩ ũndũ wa kuona mĩago.
30 Nígbà ti Paulu sì ń fẹ́ wọ àárín àwọn ènìyàn lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn kọ̀ fún un.
Paũlũ nĩendaga kwĩyumĩria mbere ya kĩrĩndĩ kĩu, no arutwo makĩmũgiria.
31 Àwọn olórí kan ara Asia, tí i ṣe ọ̀rẹ́ rẹ̀, ránṣẹ́ sí i, wọ́n bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó má ṣe fi ara rẹ̀ wéwu nínú ilé ìṣeré náà.
O na anene amwe a bũrũri wa Asia arĩa maarĩ arata a Paũlũ makĩmũtũmanĩra, makĩmũthaitha ndakagerie gũtoonya nyũmba ĩyo yagomanagwo nĩ ũndũ wa kuona mĩago.
32 Ǹjẹ́ àwọn kan ń wí ohun kan, àwọn mìíràn ń wí òmíràn: nítorí àjọ di rúdurùdu; ọ̀pọ̀ ènìyàn ni kò sì mọ̀ ìdí ohun tí wọ́n tilẹ̀ fi péjọpọ̀.
Kĩũngano kĩu gĩkĩaga ũiguano: Amwe maanagĩrĩra makoiga ũũ, na arĩa angĩ makoiga ũũ. Andũ arĩa aingĩ o na matiamenyaga gĩtũmi gĩa gũkorwo hau.
33 Àwọn kan nínú àwùjọ Júù ti Aleksanderu síwájú, wọn si pàṣẹ fun láti sọ̀rọ̀. Ó juwọ́ sí wọn láti dákẹ́ kí ó ba lè wí tẹnu rẹ̀ fun àwọn ènìyàn.
Ayahudi makiumĩria Alekisanda mbere ya kĩrĩndĩ, na andũ amwe a kĩrĩndĩ kĩu makĩanĩrĩra makĩmwĩra ũrĩa egwĩka. Nake akĩmakiria na moko nĩgeetha eyarĩrĩrie mbere yao.
34 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n mọ̀ pé Júù ni, gbogbo wọn ni ohùn kan, bẹ̀rẹ̀ sí kígbe fún bi wákàtí méjì pé, “Òrìṣà ńlá ni Artemisi tí ará Efesu!”
No rĩrĩa maamenyire atĩ aarĩ Mũyahudi, othe makĩanĩrĩra na mũgambo ũmwe ihinda ta rĩa mathaa meerĩ makiugaga atĩrĩ, “Aritemi wa Aefeso nĩ mũnene!”
35 Nígbà tí akọ̀wé ìlú sì mú kí ìjọ ènìyàn dákẹ́, “Ẹ̀yin ará Efesu, ta ni ẹni tí ó wà tí kò mọ̀ pé, ìlú Efesu ní í ṣe olùsìn Artemisi òrìṣà ńlá, àti tí ère tí ó ti ọ̀dọ̀ Jupiteri bọ́ sílẹ̀?
Karani wa kĩama gĩa itũũra rĩu agĩkiria kĩrĩndĩ kĩu, agĩcooka akĩmeera atĩrĩ: “Andũ aya a Efeso, githĩ thĩ yothe ndĩũĩ atĩ itũũra rĩa Efeso nĩrĩo rĩene hekarũ ĩrĩa ĩtũũragwo nĩ Aritemi ũrĩa mũnene, na mũhianano wake ũrĩa waharũrũkire kuuma igũrũ?
36 Ǹjẹ́ bi a kò tilẹ̀ sọ̀rọ̀-òdì sí nǹkan wọ̀nyí, ó yẹ kí ẹ dákẹ́, kí ẹ̀yin má ṣe fi ìkanra ṣe ohunkóhun.
Nĩ ũndũ ũcio, kuona atĩ maũndũ macio matingĩkaanĩka-rĩ, mwagĩrĩirwo nĩ gũkira, na mũtikae gwĩka ũndũ wa ihenya.
37 Nítorí ti ẹ̀yin mú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí wá, wọn kò ja ilé òrìṣà lólè, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sọ̀rọ̀-òdì sí òrìṣà wa.
Inyuĩ mwarehe andũ aya haha, o na gũtuĩka ti kũiya maiyĩte indo cia hekarũ, kana makaruma ngai iitũ ya mũndũ-wa-nja.
38 Ǹjẹ́ nítorí náà tí Demetriusi, àti àwọn oníṣẹ́-ọnà tí o wà pẹ̀lú rẹ̀ bá ní gbólóhùn asọ̀ kan sí ẹnikẹ́ni, ilé ẹjọ́ ṣí sílẹ̀, àwọn onídàájọ́ sì ń bẹ: jẹ́ kí wọn lọ fi ara wọn sùn.
Hakĩrĩ ũguo-rĩ, angĩkorwo Demeterio na andũ acio angĩ marutaga wĩra nake marĩ na mateta igũrũ rĩa mũndũ o wothe, maciirĩro nĩmahingũre na aciirithania marĩ ho. No mamathitange.
39 Ṣùgbọ́n bí ẹ ba ń wádìí ohun kan nípa ọ̀ràn mìíràn, a ó parí rẹ̀ ni àjọ tí ó tọ́.
Angĩkorwo harĩ na ũndũ ũngĩ mũngĩenda kuuga makĩria ma ũguo, ũcio no ũciirĩirwo kĩama-inĩ kĩa watho.
40 Nítorí àwa ṣa wà nínú ewu, nítorí rògbòdìyàn tí ó bẹ́ sílẹ̀ lónìí yìí; kò ṣáá ní ìdí kan tí rògbòdìyàn yìí fi bẹ́ sílẹ̀, nítorí èyí àwa kì yóò lè dáhùn fún ìwọ́jọ yìí.”
Ũrĩa kũrĩ rĩu nĩ atĩ, tũrĩ ũgwati-inĩ wa gũthitangĩrwo ngũĩ ĩno ya ũmũthĩ. Na kũrĩ ũguo tũtingĩhota kũheana ũhoro wa thogothogo ĩno, tondũ hatirĩ na gĩtũmi kĩa yo.”
41 Nígbà tí ó sì ti sọ bẹ́ẹ̀ tan, ó tú ìjọ náà ká.
Aarĩkia kuuga ũguo, akĩĩra kĩũngano kĩu gĩthiĩ, akĩniina mũcemanio.

< Acts 19 >