< Acts 16 >
1 Ó sì wá sí Dabe àti Lysra: sí kíyèsi i, ọmọ-ẹ̀yìn kan wà níbẹ̀, tí a ń pè ní Timotiu, ọmọ obìnrin kan tí í ṣe Júù, tí ó gbàgbọ́; ṣùgbọ́n Giriki ní baba rẹ̀.
Bulus tak bou Darbe kange listira, la nii bwankako kange co ti ki Timoti wiwi, bibwe nawiye Yahuda wo nii bilenke, dila Tee ce Baheline.
2 Ẹni tí a ròhìn rẹ̀ ní rere lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin tí ó wà ní Lysra àti Ikoniomu.
Cii tok dikero kenti dorcer nyi nubo wo Listira kange Ikoniya.
3 Òun ni Paulu fẹ́ kí ó bá òun lọ; ó sì mú un, ó sì kọ ọ́ ní ilà, nítorí àwọn Júù tí ó wà ní agbègbè wọ̀nyí, nítorí gbogbo wọn mọ̀ pé, Giriki ni baba rẹ̀.
Bulus cui naci ya yam kange co, la cin to cho, cin biye cinen laro ker yahudawa wo fiye tini curo nineu. wori gwamce nyimom ki tece nii heline.
4 Bí wọn sì ti ń la àwọn ìlú lọ, wọ́n ń fi àwọn àṣẹ, tí a tí pinnu láti ọ̀dọ̀ àwọn aposteli àti àwọn alàgbà tí ó wà ní Jerusalẹmu, lé wọn lọ́wọ́ láti máa pa wọ́n mọ́.
Kambo ci cukenti mor cinanlore, ciin nerang nyal tinimbo nob tomangebo wo kange. nubo dur tinimbo wo mor Ursalima ciya cike ri, naci bwangten.
5 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìjọ sì fẹsẹ̀múlẹ̀ ní ìgbàgbọ́, wọn sí ń pọ̀ sí i ní iye lójoojúmọ́.
La nubo bikur wabereu fiya bikwan neret mor bilenke la ciin kila cii cobten ti diye ki diye.
6 Wọ́n sì la agbègbè Frigia já, àti Galatia, nítorí tí Ẹ̀mí Mímọ́ kọ̀ fún wọn láti sọ ọ̀rọ̀ náà ni Asia.
Bulus kange nubo tikan co tiyeu ya mor cungko Phrygia kange Galatiaya, wori yuwa tangbe kwamako ywanmci tokka ker cero cunga ko Asia.
7 Nígbà tí wọ́n dé ọ̀kánkán Misia, wọ́n gbìyànjú láti lọ sí Bitinia, ṣùgbọ́n Ẹ̀mí Jesu kò gbà fún wọn.
Ki kwama wo cii bow bidom kange Misiyari, cii cuwa na ci do mor Bitiniya, dila yuwa tangbe Yesu ywamci.
8 Nígbà tí wọ́n sì kọjá lẹ́bàá Misia, wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ sí Troasi.
Kambo ci dou Mysia ri, ciin yirau mor cinanlor Troas.
9 Ìran kan si hàn sì Paulu ni òru, ọkùnrin kan ará Makedonia dúró, ó sì ń bẹ̀ ẹ́, wí pé, “Rékọjá wá sí Makedonia, kí o sí ràn wá lọ́wọ́!”
Bulus ma dukumbo ki kume; nii Makidoniya tiim wi, kinong coti ki, “Bou fou Makidoniya na mwi tikang nyo”.
10 Nígbà tí ó sì tí rí ìran náà, lọ́gán ó múra láti lọ sí Makedonia, a ka á sí pé, Ọlọ́run tí pè wá láti wàásù ìyìnrere fún wọn.
Kambo Bulus to dumeri, dangjang do naci yaken Makidoniya, cin kwabi nercer ki kwama cuo nyo nyi tok ker cero Makidoniya.
11 Nítorí náà nígbà tí àwa ṣíkọ̀ ní Troasi a ba ọ̀nà tààrà lọ sí Samotrakea, ni ọjọ́ kejì a sì dé Neapoli;
Kambo ci dob mor Troas ri, nyin yaken ciyer nyin yaken Samothrace, la cel fini ceri nyin bow Neapolis.
12 láti ibẹ̀ àwa sì lọ si Filipi, tí í ṣe ìlú Makedonia, olú ìlú ìhà ibẹ̀, ìlú lábẹ́ Romu, àwa sì jókòó ní ìlú yìí fún ọjọ́ mélòó kan.
La nyi kwen wiri nyin cuo Philippi, wo co cinan lor Makidoniya, cinan lor la tangnumbo mor biten Roma; La nyin cerum wi cinan lor nen kume ni kila.
13 Lọ́jọ́ ìsinmi, àwa sí jáde lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú náà, lẹ́bàá odò kan, níbi tí a rò pé ibi àdúrà wà; àwa sí jókòó, a sì bá àwọn obìnrin tí o péjọ sọ̀rọ̀.
Ki diye fobka Yahudawa ri nyin cer ken nyilo cinan lor kong chaci ki kwa nere ki nysn fiya fiye kwobka dilo wi. La nyin yiken ri, nyon tok ker. kange natubo wo mwerum wiyeu.
14 Àti obìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Lidia, elése àlùkò, ará ìlú Tiatira, ẹni tí ó sin Ọlọ́run, ó gbọ́ ọ̀rọ̀ wa, ọkàn ẹni tí Olúwa ṣí láti fetísí ohun tí a tí ẹnu Paulu sọ.
Nawiye kange dendo ki Lidiya, wo wiye kwilen tiyeu, ci ceru cinan lor Tiyatira, wo wab kwamatiyeu, cuwa tu nuwa nyo. La Teluwe wumom neer cero cin cuwa tu ki dike Bulus tok tiyeu nen.
15 Nígbà tí a sí bamitiisi rẹ̀, àti àwọn ara ilé rẹ̀, ó bẹ̀ wá, wí pé, “Bí ẹ̀yin bá kà mí ni olóòtítọ́ sí Olúwa, ẹ wá si ilé mi, kí ẹ sí wọ̀ níbẹ̀!” O sí rọ̀ wá.
Kambo co kange nubo loceri, cin kenyo ciki, no kom ciya komki min yilam ki bilenke kwama nin di kom bou ko cerum lomi. “La cin dok nyo nyin ciya.
16 Bí àwa tí n lọ sí ibi àdúrà náà, ọmọbìnrin kan tí o ní ẹ̀mí àfọ̀ṣẹ, pàdé wa, ẹni tí ó fi àfọ̀ṣẹ mú èrè púpọ̀ wá fún àwọn ọ̀gá rẹ̀.
Nyori, ki kwamawo nyin yaken ti fiye kwob ka diloke, bibuya canga kange woki ninga tokake wab kang nyo. Ci bou teluwe ce nen ti ki kyemer ducce ki to kako ci totiyeu.
17 Òun náà ni ó ń tọ Paulu àti àwa lẹ́hìn, ó sì ń kígbe, pé, “Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ni ìránṣẹ́ Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo, tí ń kéde ọ̀nà ìgbàlà fún yin!”
La bubiya wo bwnag ten Bulus ti kange nyo la ci kwabang dir, ti ki “Nubo buro cangab kwama dureb. ciki yi kom nure fuloka”.
18 Ó sì ń ṣe èyí lọ́jọ́ púpọ̀, ṣùgbọ́n nígbà tí inú Paulu bàjẹ́, tí ó sì yípadà, ó wí fún ẹ̀mí náà pé, “Mo pàṣẹ fún ọ ní orúkọ Jesu Kristi kí o jáde kúrò lára rẹ̀!” Ó sí jáde ni wákàtí kan náà.
Ciki mai nyo ki kume tini kila. Dila kambo Bulus kangum neer cero kayam meri, yi kangi la yico “mi nyal nenti ki den Yesu Kiristi, ceru cinen”. La ciin cerum ki kwama co.
19 Nígbà tí àwọn ọ̀gá rẹ̀ sì rí i pé, ìgbẹ́kẹ̀lé èrè wọn pin, wọ́n mú Paulu àti Sila, wọn sì wọ́ wọn lọ sí ọjà tọ àwọn aláṣẹ lọ.
Kambo teb teluweb cebo tori yoka neerek fiya ka mweb kemerceu cuwe ri, ciin tam Bulus kange cila kwob kanci yaken ki cii fiye tubo miyem diker tiye kabum nob bolangeb.
20 Nígbà tí wọ́n sì mú wọn tọ àwọn onídàájọ́ lọ, wọ́n wí pé, “Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí tí í ṣe Júù, wọ́n ń yọ ìlú wa lẹ́nu jọjọ,
kambo ci bou ki ci ka bum nob bolangebri, cii ki “Nubo buro kum cnag cinan lor beroti. ciin yahudawa.
21 wọ́n sì ń kọ́ni ní àṣà tí kò yẹ fún wa, àwa ẹni tí í ṣe ara Romu, láti gbà àti láti tẹ̀lé.”
Cii merang nure ti wo kebo dong-dong kange dike nubo Roma ciye ciya cuko naci bwang tenneu.
22 Ọ̀pọ̀ ènìyàn sí jùmọ̀ dìde sì Paulu àti Sila. Àwọn olórí sí fà wọ́n ní aṣọ ya, wọ́n sí pàṣẹ pé, ki a fi ọ̀gọ̀ lù wọ́n.
La mwerkan nubo ko gwam kwinang Bulus ce kange Silas, nob bolangebo wob rangum kwilen cero cii nen ri ne nyallo naci makanci ki Belyange kwamangi nyeu.
23 Nígbà tí wọ́n sì lù wọ́n púpọ̀, wọ́n sọ wọ́n sínú túbú, wọ́n kìlọ̀ fún onítúbú kí ó pa wọ́n mọ́ dáradára.
Kambo malli ciyeri? Ciin dokken cii mor Furcina, ri ciin yi nii to furcina tiyeu na kii ca kum cii yorak.
24 Nígbà tí ó gbọ́ irú ìkìlọ̀ bẹ́ẹ̀, ó sọ̀ wọ́n sínú túbú tí inú lọ́hùn, ó sí kan àbà mọ wọ́n lẹ́sẹ̀.
kambo ci yo nyallo weri, nii to ka Furcinako dokken cii kuwe more ri cin kum na tini ceko.
25 Ṣùgbọ́n láàrín ọ̀gànjọ́ Paulu àti Sila ń gbàdúrà, wọ́n sì ń kọrin ìyìn si Ọlọ́run, àwọn ara túbú sì ń tẹ́tí sí wọn.
Kina ciinkume Bulus kange Silas, kwob dilo rila cii ka nuwe wabka kwama tii la tangnum nubo furcinau cuwa tuu nuwa ciiti.
26 Lójijì ilẹ̀ mímì ńlá sì mi, tó bẹ́ẹ̀ tí ìpìlẹ̀ ilé túbú mì tìtì: lọ́gán, gbogbo ìlẹ̀kùn sì ṣí, ìdè gbogbo wọn sì tú sílẹ̀.
Dang jangri ka mikanka dor bitiner wo dok kwar kur furcinau mikangume la danjang nyilok tininmbo gwam womangum kang nubo bwambwabeu kwiya.
27 Nígbà tí onítúbú si tají, tí o sì ri pé, àwọn ìlẹ̀kùn túbú tí ṣí sílẹ̀, ó fa idà rẹ̀ yọ, ó sì fẹ́ pa ara rẹ̀, ó ṣe bí àwọn ara túbú ti sálọ.
Nii to furcinatiyeu yuram dumbo ri, cin to nyiloko wumom, la cin co ku kulen cero ri, cin cui naci twallum dor cero, wori cin kwabi ki nubo furcinau cirangum.
28 Ṣùgbọ́n Paulu gbé ohun rẹ̀ sókè, wí pé, “Má ṣe pa ara rẹ lára: nítorí gbogbo wa ń bẹ níhìn-ín yìí!”
La Bulus kwa cinen dir kibi kwan ki, “Nuware dor mwe ro nen twirak, wori nyin wi fou gwam nye.
29 Nígbà tí ó sì béèrè iná, ó bẹ́ wọ inú ilé, ó ń wárìrì, ó wólẹ̀ níwájú Paulu àti Sila.
Nii to furcina tiyeu me naci bo cinen ki kirak, la cin doken mor wulom mor taiye, ciin cungi kabum Bulus kange Silas.
30 Ó sì mú wọn jáde, ó ní, “Alàgbà, kín ni ki èmi ṣe ki n lè là?”
La ciin coku ci kaleri, ciki “Nubo dur miik nye ma mati nami fiya fuloka?
31 Wọ́n sì wí fún un pé, “Gbá Jesu Kristi Olúwa gbọ́, a ó sì gbà ọ́ là, ìwọ àti àwọn ará ilé rẹ pẹ̀lú.”
Ciin yico ki “Neken bilenke teluwe Yesu nen, namwi fiya fuloka mo kang nubo lomeu gwam.
32 Wọ́n sì sọ ọ̀rọ̀ Olúwa fún un, àti fún gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀.
Ciin yico ker Teluwero, kange nubo loceu gwam.
33 Ó sì mú wọn ní wákàtí náà lóru, ó wẹ ọgbẹ́ wọn; a sì bamitiisi rẹ̀, àti gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ lójúkan náà.
La nii yo furcina tiyeu tu ci ki kume cuo, la cin nirom dercero, ri co loce gwam cin yum mwem kwamam bo dang jang.
34 Ó sì mú wọn wá sí ilé rẹ̀, ó sì gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú wọn, ó sì yọ̀ gidigidi pẹ̀lú gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, nítorí ó gba Ọlọ́run gbọ́.
la kambo ci bou ti Bulus kange Silas loco ri, ci tik cinen carito kaciye, cin bilangi ducce kange nubo mor luwe ceu, wori cin ne bilenke kwama nen.
35 Ṣùgbọ́n nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn onídàájọ́ rán àwọn ọlọ́pàá pé, “Tú àwọn ènìyàn náà sílẹ̀.”
La kambo fini celumeri, nob bolangebo tom nobo to cinanlor tiye nen ker, ciki “Dob nubo co a yaken ti”.
36 Onítúbú sì sọ ọ̀rọ̀ náà fún Paulu, wí pé, “Àwọn onídàájọ́ ránṣẹ́ pé kí á da ìwọ àti Sila sílẹ̀. Ǹjẹ́ nísinsin yìí ẹ jáde kí ẹ sì máa lọ ní àlàáfíà.”
nii to furcinan tiyeu yi Bulus kero couki “Nob bolangebo tunguo tomange minen na dob kom ko yakenti. na weu dila kom ceru ri nako yakenti ki luma.
37 Ṣùgbọ́n Paulu wí fún wọn pé, “Wọ́n lù wá ni gbangba, wọ́n sì sọ wá sínú túbú ni àìjẹ̀bi, àwa ẹni tí ì ṣe ara Romu. Ṣe nísinsin yìí wọ́n fẹ́ tì wá jáde níkọ̀kọ̀? Rara! Ṣùgbọ́n kí àwọn tìkára wọn wá mú wa jáde!”
Dila Bulus kane silas ciya cinen ki “Cii malli nyo nyanglang bolang mani, ri nyi nubo Roma keneu- la ciin mer ken nyo mor furcina. La ciki cui wona weu naci yoken ki yurangka ka? mani nyo! Ciya bou ki bwici naci cok nyo kale”.
38 Àwọn ọlọ́pàá sì sọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn onídàájọ́: ẹ̀rù sì bà wọ́n, nígbà tí wọ́n gbọ́ pé ará Romu ni Paulu àti Sila.
La nii to kakkawo ya yi nob bolangebo kereburo. Kambo ci nuwa ki Bulus kange Silas nubo Roam ri cin cuwam tai.
39 Wọ́n sì wá, wọ́n ṣìpẹ̀ lọ́dọ̀ wọ́n, wọn sì mú wọn jáde, wọ́n sì bẹ̀ wọ́n pé, ki wọn jáde kúrò ni ìlú náà.
Nob bolangebo bou la ciin ken ci rila cii cokangum kale, la cin yici ki ciya cerum mor cinan loro nen.
40 Paulu àti Sila sì jáde nínú túbú, wọ́n sì wọ ilé Lidia lọ, nígbà tí wọn sì tí rí àwọn arákùnrin, wọ́n tù wọ́n nínú, wọn sì jáde kúrò.
La Bulus kange Silas cerangum furcina ri cin bou to Lidiya. Kambo Bulus kange Silas to nuberi, ciin neci bikwan neret, cin dubom cinan loro.