< Acts 15 >
1 Àwọn ọkùnrin kan tí Judea sọ̀kalẹ̀ wá, wọ́n sì kọ́ àwọn arákùnrin pé, “Bí kò ṣe pé a bá kọ yín ni ilà bí ìṣe Mose, ẹ̀yin kí yóò lè là.”
Bhanu fulani bhaselili kuhoma Uyahudi ni kubhamanyesya bhalongo, bhakajonha, “Mkabela kutahiribhwa kama desturi jha Musa, mwibhwesya lepi kuolibhwa.”
2 Nígbà tí Paulu àti Barnaba ni ìyapa àti ìyàn jíjà tí kò mọ níwọ̀n pẹ̀lú ara wọn, wọ́n yan Paulu àti Barnaba àti àwọn mìíràn nínú aposteli kí wọn gòkè lọ sí Jerusalẹmu, sọ́dọ̀ àwọn alàgbà nítorí ọ̀ràn yìí.
Bwakati Paulo ni Barnaba bhobhajhele na mapambano ni mjadala pamonga na bhalongo bhaamuili kujha Paulo, Barnaba ni bhangi kadhaa bhalotayi Yerusalemu kwa mitume ni bhaseya kwandabha jhe liswali e'le.
3 Nítorí náà, bí ìjọ ti rán wọn jáde lọ sí ọ̀nà wọn, wọn la Fonisia àti Samaria kọjá, wọ́n ń ròyìn ìyípadà àwọn aláìkọlà, wọ́n sì fi ayọ̀ ńlá fún gbogbo àwọn arákùnrin.
Henu kwa kulaghisibhwa kwa bhene, ni kanisa bhapetili Foinike ni Samaria bhakajha bhitangasyali furaha mbaha kwa bhalongobha bhoha.
4 Nígbà tí wọn sì dé Jerusalẹmu, ìjọ àti àwọn aposteli àti àwọn alàgbà tẹ́wọ́gbà wọ́n, wọ́n sì ròyìn ohun gbogbo tí Ọlọ́run ti ṣe nípasẹ̀ wọn.
Bho bhahidili Yerusalemu, bhakaribisibhu ni kanisa ni mitume ni bhaseya, na bhawasilishi taarifa jha mambo ghoha ambagho K'yara abhombili pamonga nabhu.
5 Ṣùgbọ́n àwọn kan nínú ẹ̀yà àwọn Farisi tí wọ́n gbàgbọ́ dìde, wọ́n ń wí pé, “A ní láti kọ wọ́n ní ilà, àti láti pàṣẹ fún wọn pé kí wọn máa pa òfin Mose mọ́.”
Lakini bhanu fulani bhabhaamini bhajhele mu likundi lya Mafarisayo bhajhemili ni kujobha, “ni muhimu kubhatahiri ni kubhaamuru bhayikamulayi sheria jha Musa,”
6 Àwọn aposteli àti àwọn alàgbà péjọ láti rí si ọ̀ràn yìí.
Hivyo mitume nibhaseya bhajhemi pamonga kulifikirila liswala e'le.
7 Nígbà tí iyàn sì di púpọ̀, Peteru dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ará, ẹ̀yin mọ̀ pé, láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn nínú yín pé, kí àwọn aláìkọlà lè gbọ́ ọ̀rọ̀ ìyìnrere láti ẹnu mi, kí wọn sì gbàgbọ́.
Baada jha majadiliano matali Petro ajhenuli ni kujobha kwa bhene, “Bhalongo mumanyili kujha kitambo kinofu kyakilotili K'yara abhombili lichaguo jha muenga, kujha kwa ndomo ghwangu mataifa bhapelekayi lilobhi lya injili, ni kuamini.
8 Ọlọ́run, tí ó jẹ́ olùmọ̀-ọkàn, sì jẹ́ wọn lẹ́rìí, ó fún wọn ni Ẹ̀mí Mímọ́, gẹ́gẹ́ bí àwa.
K'yara jha aghimanyili mioyo, ishuhudila kwa bhene, akabhapela Roho mtakatifu, kama kyaabhombili kwa tete;
9 Kò sí fi ìyàtọ̀ sí àárín àwa àti àwọn, ó ń fi ìgbàgbọ́ wẹ̀ wọ́n lọ́kàn mọ́.
na atengenisilepi utofauti kati jha tete ni bhene, akajhibhomba mioyo jhya bhene minofu kwa imani.
10 Ǹjẹ́ nítorí náà èéṣe tí ẹ̀yin o fi dán Ọlọ́run wò, láti fi àjàgà bọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn lọ́rùn, èyí tí àwọn baba wa àti àwa kò lè rù?
Kwa hiyo, kwanajhakiki mukan'jaribu K'yara kujha mubhekayi nira panani pa nsingu sya bhanafunzi ambabho hata bhadadi jhitu wala tete twibhwesyalepi kustahimili?
11 Ṣùgbọ́n àwa gbàgbọ́ pé nípa oore-ọ̀fẹ́ Olúwa Jesu àwa ó là, gẹ́gẹ́ bí àwọn.”
Lakini twikiera kujha twibetakuokolibhwa kwa neema jha Bwana Yesu, kama kyabhajhele.”
12 Gbogbo àjọ sí dákẹ́, wọ́n sì fi etí sí Barnaba àti Paulu, tí wọn ń ròyìn iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì tí Ọlọ́run tí ti ọwọ́ wọn ṣe láàrín àwọn aláìkọlà.
Kusanyiku lyoha lyagudeme bho bhakampelekesya Barnaba ni Paulo bho bhihomesya taarifa jha ishara ni maajabu ambagho K'yara abhombi pamonga nabhu kati jha bhanu bha mataifa.
13 Lẹ́yìn tí wọn sì dákẹ́, Jakọbu dáhùn, wí pé, “Ará, ẹ gbọ́ tèmi,
Bho bhalekili kulongela, Yakobo ajibili akajobha, “Bhalongo munipelekesiajhi.
14 Simeoni ti ròyìn bí Ọlọ́run ti kọ́kọ́ bojú wo àwọn aláìkọlà, láti yàn ènìyàn nínú wọn fún orúkọ rẹ̀.
Simoni ajhelekisi hoti jinsi hoti K'yara kwa neema abhasaidili mataifa ili kwamba akikabhilayi kuhoma kwa bhene bhanu kwandabha jha lihina lya bhebhe.
15 Báyìí ni ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì bá ṣe déédé; bí a ti kọ̀wé rẹ̀ pé:
Malobhi gha manabii ghikakubaliana ni e'le kama kya lilembibhu.
16 “‘Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni èmi ó padà, èmi ó sì tún àgọ́ Dafidi pa tí ó ti wó lulẹ̀: èmi ó sì tún ahoro rẹ̀ kọ́, èmi ó sì gbé e ró.
Baada jha mambo agha nibetakukerebhuka ni kujenga kabhele hema jha Daudi, jhahaguili pasi; nibetakuhinula ni kubhumala uharibufu bhwake,
17 Kí àwọn ènìyàn ìyókù lè máa wá Olúwa, àti gbogbo àwọn kèfèrí, lára ẹni tí a ń pe orúkọ mi,’ ni Olúwa wí, ta ni ó ń ṣe nǹkan wọ̀nyí,
ili kwamba bhanu bhabhasiele bhandondayi Bwana, pamonga ni bhanu bha mataifa bhabhakutibhu kwa lihina lya nene;
18 ẹni tí ó sọ gbogbo nǹkan wọ̀nyí di mímọ́ láti ọjọ́ pípẹ́ wá. (aiōn )
Efe ndo, kyaajobhili Bwana jhaabhombi mambo agha ghamanyikanayi kuhomela enzi sya muandi. (aiōn )
19 “Ǹjẹ́ ìmọ̀ràn tèmi ni pé, kí a máa ṣe yọ àwọn ti aláìkọlà ti ó yípadà sí Ọlọ́run lẹ́nu.
Efyo basi, ushauri bhwa nene ni kwamba tusibhapeli shida bhanu bha mataifa bhabhakan'geukila K'yara.
20 Ṣùgbọ́n kí a kọ̀wé si wọn, kí wọ́n fàsẹ́yìn kúrò nínú oúnjẹ tí a ṣe fún òrìṣà, àti kúrò nínú àgbèrè, àti nínú ẹ̀jẹ̀.
Lakini tujhandikayi kwa bhene kujha bhakijhepusiajhi patali ni uharibifu bhwa sanamu, tamaa sya uasherati, ni fyafiniongibhu, ni damu.
21 Nítorí òfin Mose nígbà àtijọ́ ṣá ní a ti ń wàásù rẹ̀, ni ìlú gbogbo, a máa ń kà á nínú Sinagọgu ni ọjọọjọ́ ìsinmi.”
Kuhoma fizazi fya bhasee kuna bhanu ku kila mji bhabhihubiri ni kun'soma Musa mu masinagogi khila sabato.”
22 Nígbà nà án ni ó tọ́ lójú àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà pẹ̀lú gbogbo ìjọ, láti yan ènìyàn nínú wọn, àti láti rán wọ́n lọ sí Antioku pẹ̀lú Paulu àti Barnaba: Judasi ti a ń pè àpèlé rẹ̀ ní Barsaba, àti Sila, ẹni tí ó lórúkọ nínú àwọn arákùnrin.
Kwa hiyo jhibhonekana kujha jhibhapendesi mitume ni bhaseya, pamonga ni likanisa lyaoha, ku'chagula Yuda ghaakutibhu Barnaba ni Silas bhabhajhele bhalongosi bha kanisa, nikubhalaghisya Antiokia pamonga ni Paulo ni Barnaba.
23 Wọn sì kọ ìwé lé wọn lọ́wọ́ báyìí pé, Àwọn aposteli, àti àwọn alàgbà, tí ó jẹ́ ti aláìkọlà tí ó wà ní Antioku, àti ní Siria, àti ní Kilikia.
Bhalembi naha, “Mitume bhasee ni bhalongo bhangu kwa bhalongo bha mataifa bhabhajhele Antiokia, Shamu ni Kilikia, salamu.
24 Níwọ́n bí àwa ti gbọ́ pé, àwọn kan ti ó ti ọ̀dọ̀ wa jáde wá ń fi ọ̀rọ̀ yọ yín lẹ́nu, tí wọ́n ń yí yín ní ọkàn padà (wí pé, ẹ kò gbọdọ̀ ṣàìmá kọ ilà, àti ṣàìmá pa òfin Mose mọ́), ẹni tí àwa kò fún ní àṣẹ.
Twapelili kujha bhanu fulani ambho twabhapelili lepi amri ejhu, bhabhokili kwa tete na bhabhataabisi kwa mafundisu ghaghileta shida mu nafsi sya muenga.
25 Ó yẹ lójú àwa, bí wa ti fi ìmọ̀ ṣọ̀kan láti yan ènìyàn láti rán wọn sí yín, pẹ̀lú Barnaba àti Paulu àwọn olùfẹ́ wa.
Kwa hiyo, jhibhonekana kinofu kwa tete twebhoha kuchagula bhanu bha kubhalaghisya kwa muenga pamonga ni bhapendwa bhitu Barnaba, ni Paulo.
26 Àwọn ọkùnrin ti ó fi ọkàn wọn wéwu nítorí orúkọ Olúwa wa Jesu Kristi.
Bhanu bhabhahatarisi maisha gha bhene kwa ndabha jha lihina lya Bwana Yesu Kristu.
27 Nítorí náà àwa rán Judasi àti Sila àwọn tí yóò sì fi ọ̀rọ̀ ẹnu sọ ohun kan náà fún yín.
Henu, tundaghisi Yuda ni Sila, bhibeta kubhajobhela mambo ghaghuaghu.
28 Nítorí ó dára lójú Ẹ̀mí Mímọ́, àti lójú wa, kí a má ṣe di ẹrù le é yin lórí, bí kò ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí tí ó ṣe pàtàkì;
Kwa kujha jhabhoniki kinofu kwa Roho mtakatifu ni kwa tete, kubho juu jha muenga nsighu mbaha kuliko mambo agha ghaghajhele gha lazima.
29 í ẹ̀yin fàsẹ́yìn kúrò nínú ẹran ti à pa bọ òrìṣà, àti nínú ẹ̀jẹ̀ àti nínú ohun ìlọ́lọ́rùnpa, àti nínú àgbèrè. Bí ẹ̀yin bá pa ara yín mọ́ kúrò, ẹ̀yin ó ṣe rere. Àlàáfíà.
kwamba mgeukayi kuhomela kufenu fya fipisibhu kwa sanamu, damu, fenu fya kunyongibhwa, ni uasherati. kama mwibetakwibheka patali ni efe jhibetakujha kinofu kwa muenga. kwaherini.”
30 Ǹjẹ́ nígbà tí wọ́n sì fi wọ́n sílẹ̀ láti lọ, wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá si Antioku. Nígbà tí wọn sì pé àwọn ìjọ papọ̀, wọn fi ìwé náà fún wọn.
Efyo basi, bhobhatawanyisi bhu bhaselelili Antiokia; baada jha kubhonganiya kusanyiku pamonga, bhawasilishi barua.
31 Nígbà tí wọn sì kà á, wọ́n yọ̀ fún ìtùnú náà.
Bho bhajhisomili bhahobhwiki kwandabha jha kupelibhwa muoyo.
32 Bí Judasi àti Sila tìkára wọn ti jẹ́ wòlíì pẹ̀lú, wọ́n fi ọ̀rọ̀ púpọ̀ gba àwọn arákùnrin níyànjú, wọ́n sì mú wọn lọ́kàn le.
Yuda ni Sila ni manabii, bhabhapelili muoyo bhalongo kwa malobhi ghamehele ni kubhasopela ngofu.
33 Nígbà tí wọn sì pẹ́, díẹ̀, àwọn arákùnrin rán wọn padà lọ ni àlàáfíà sí ọ̀dọ̀ àwọn tí ó rán wọn wá.
Baada jha kutama muda fulani okhu, bhatawanyisibhu kwa amani kuhoma kwa bhalongo kwa bhala bhabhalaghisi.
(Lakini jhabhonekene kinofu lepi kusiala okhu).
35 Paulu àti Barnaba sì dúró díẹ̀ ni Antioku, wọ́n ń kọ́ni, wọ́n sì ń wàásù ọ̀rọ̀, Olúwa, àti àwọn púpọ̀ mìíràn pẹ̀lú wọn.
Lakini Paulo ni bhangi bhatamili Antiokia pamonga ni bhangi bhamehele, ambapo bhanafundisi ni kuhubiri lilobhi lya Bwana.
36 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan, Paulu sì sọ fún Barnaba pé, “Jẹ́ kí a tún padà lọ bẹ àwọn arákùnrin wa wò, bí wọn ti ń ṣe sí ni ìlú gbogbo tí àwa ti wàásù ọ̀rọ̀ Olúwa.”
Baada jha magono kadhaa Paulo ajobhili kwa Barnaba, “Natukerebhukayi henu ni kubhagendela bhalongo mu khila mji pa twahubiri lilobhi lya Bwana, ni kubhabhona kyabhajhele.
37 Barnaba sì pinnu rẹ̀ láti mú Johanu lọ pẹ̀lú wọn, ẹni tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Marku.
Barnaba alondeghe kabhele kun'tola pamonga nabhu Yohana jhaakutibhu Marko.
38 Ṣùgbọ́n Paulu rò pé, kò yẹ láti mú un lọ pẹ̀lú wọn, ẹni tí ó fi wọn sílẹ̀ ni Pamfilia, tí kò sì bá wọn lọ sí iṣẹ́ náà.
Lakini Paulo afikiriri jhajhekinofu lepi kun'tola Marko, jhaabhalekili okhu pamfilia na ajhendeli lepi nabhu mu mbombo.
39 Ìjà náà sì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀, tí wọn ya ara wọn sì méjì, Barnaba sì mu Marku ó tẹ ọkọ́ létí lọ sí Saipurọsi.
Kisha apu kwahomili mabishano mabhaha kwa hiyo bhatengene, ni Barnaba an'tolili Marko ni kusafiri kwa meli mpaka Kipro.
40 Ṣùgbọ́n Paulu yan Sila, ó sì lọ, bí a ti fi lé oore-ọ̀fẹ́ Olúwa lọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin.
Lakini Paulo an'chaguili Sila ni kubhoka, baada jha kukabisibhwa ni bhalongomunu mu neema jha Bwana.
41 Ó sì la Siria àti Kilikia lọ, ó ń mú ìjọ ní ọkàn le.
Naalotili kupelela Shamu ni Kilikia, ikajha akaghasindimalisya makanisa.