< Acts 11 >
1 Àwọn aposteli àti àwọn arákùnrin ti ó wà ni Judea sì gbọ́ pé àwọn aláìkọlà pẹ̀lú ti gba ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
Rosullar wǝ pütkül Yǝⱨudiyǝdiki baxⱪa ⱪerindaxlar [yat] ǝlliklǝrningmu Hudaning sɵz-kalamini ⱪobul ⱪilƣanliⱪini anglidi.
2 Nígbà tí Peteru sì gòkè wá sí Jerusalẹmu, àwọn ti ìkọlà ń bá a wíjọ́
Xunga, Petrus Yerusalemƣa ⱪaytⱪanda, hǝtnilik bolƣan [ixǝngüqilǝr] uni ǝyibkǝ buyrup:
3 wí pé, “Ìwọ wọlé tọ àwọn ènìyàn aláìkọlà lọ, ó sì bá wọn jẹun.”
— Sǝn hǝtnǝ ⱪilinmiƣan adǝmlǝrning ɵyidǝ meⱨman bolup, ular bilǝn ⱨǝmdastihan boldung?! — dedi.
4 Ṣùgbọ́n Peteru bẹ̀rẹ̀ sí là á yé wọn lẹ́sẹẹsẹ, wí pé,
Biraⱪ Petrus pütün ixni baxtin-ahiriƣiqǝ ularƣa bir-birlǝp qüxǝndürüp
5 “Èmi wà ni ìlú Joppa, mo ń gbàdúrà, mo rí ìran kan lójúran. Ohun èlò kan sọ̀kalẹ̀ bí ewé tákàdá ńlá, tí a ti igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá; ó sì wá títí de ọ̀dọ̀ mi.
mundaⱪ dedi: — Yoppa xǝⱨiridǝ dua ⱪiliwatⱪinimda, ƣayibanǝ kɵrünüx meni oriwelip, bir alamǝtni kɵrdüm. Kǝng dastihandǝk bir nǝrsǝ tɵt burjikidin baƣlanƣan ⱨalda asmandin qüxüp, mening yenimda tohtidi.
6 Mo tẹjúmọ́ ọn, mo sì fiyèsí i, mo sí rí ẹran ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin, àti ẹranko igbó, àti ohun tí ń rákò, àti ẹyẹ ojú ọ̀run.
Uningƣa kɵz tikip ⱪarisam, iqidǝ ⱨǝrhil tɵt putluⱪ ⱨaywanlar, yawayi ⱨaywanatlar, yǝr beƣirliƣuqilar, asmandiki uqar-ⱪanatlarmu bar ikǝn.
7 Mo sì gbọ́ ohùn kan ti ó fọ̀ sí mi pé, ‘Dìde, Peteru: máa pa, kí ó sì máa jẹ.’
Andin: «Ornungdin tur Petrus, ulardin soyup yǝ!» degǝn bir awazni anglidim.
8 “Ṣùgbọ́n mo dáhùn wí pé, ‘Rara Olúwa! Nítorí ohun èèwọ̀ tàbí ohun aláìmọ́ kan kò wọ ẹnu mi rí láéláé.’
Mǝn: «Yaⱪ Rǝb, ⱨǝrgiz bolmaydu! Mǝn ⱨeqⱪaqan ⱨǝrⱪandaⱪ napak yaki ⱨaram nǝrsini aƣzimƣa alƣan ǝmǝsmǝn!» dedim.
9 “Ṣùgbọ́n ohùn kan dáhùn nígbà ẹ̀ẹ̀kejì láti ọ̀run wá pé, ‘Ohun tí Ọlọ́run bá ti wẹ̀mọ́, kí ìwọ má ṣe pè é ní àìmọ́.’
Biraⱪ manga yǝnǝ: «Huda ⱨalal dǝp pakliƣan nǝrsini sǝn ⱨaram demǝ!» degǝn awaz anglandi.
10 Èyí sì ṣẹlẹ̀ nígbà mẹ́ta; a sì tún fa gbogbo rẹ̀ sókè ọ̀run.
Bu ix üq ⱪetim xundaⱪ tǝkrarlinip, ahir bularning ⱨǝmmisi asmanƣa ⱪaytidin tartip ketildi.
11 “Sì wò ó, lójúkan náà ọkùnrin mẹ́ta dúró níwájú ilé ti a gbé wà, ti a rán láti Kesarea sí mi.
Mana dǝl xu qaƣda, Ⱪǝysǝriyǝdin meni qaⱪirixⱪa ǝwǝtilgǝn üq kixi mǝn turƣan ɵyning aldiƣa kǝldi.
12 Ẹ̀mí sì wí fún mi pé, kí èmi bá wọn lọ, ki èmi má ṣe kọminú ohunkóhun. Àwọn arákùnrin mẹ́fà wọ̀nyí sì bá mi lọ, a sì wọ ilé ọkùnrin náà.
Muⱪǝddǝs Roⱨ meni ⱨeq ikkilǝnmǝy ular bilǝn billǝ berixⱪa buyrudi. Muxu altǝ ⱪerindaxmu mǝn bilǝn billǝ bardi. [Ⱪǝysǝriyǝgǝ yetip kelip], ⱨeliⱪi adǝmning ɵyigǝ kirduⱪ.
13 Ó sì sọ fún wa bí òun ti rí angẹli kan tí ó dúró ní ilé rẹ̀, tí ó sì wí pé, ‘Ránṣẹ́ lọ sí Joppa, kí ó sì pe Simoni tí àpèlé rẹ̀ jẹ́ Peteru;
Bu kixi bizgǝ ɵzining ɵyidǝ payda bolup turƣan bir pǝrixtini ⱪandaⱪ kɵrgǝnlikini eytti. Pǝrixtǝ uningƣa: «sǝn Yoppaƣa adǝm ǝwǝtip, Petrus dǝpmu atilidiƣan Simon isimlik bir adǝmni qaⱪirtip kǝl,
14 ẹni tí yóò sọ ọ̀rọ̀ fún ọ, nípa èyí tí a ó fi gba ìwọ àti gbogbo ilé rẹ là.’
u sanga seni wǝ pütkül ailǝnggǝ nijatliⱪ yǝtküzidiƣan bir hǝwǝrni eytip beridu» degǝnikǝn.
15 “Bí mo sì ti bẹ̀rẹ̀ sì sọ, Ẹ̀mí Mímọ́ sì bà lé wọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti bà lé wa ni àtètèkọ́ṣe.
Mǝn gǝpni baxliƣinimda, Muⱪǝddǝs Roⱨ huddi baxta bizning üstimizgǝ qüxkinidǝk, ularƣimu qüxti.
16 Nígbà náà ni mo rántí ọ̀rọ̀ Olúwa, bí ó ti wí pé, ‘Johanu fi omi bamitiisi nítòótọ́; ṣùgbọ́n a ó fi Ẹ̀mí Mímọ́ bamitiisi yín.’
Xu qaƣda, Rǝbning sɵz-kalamini, yǝni: «Yǝⱨya kixilǝrni suƣa qɵmüldürgǝn, lekin silǝr bolsanglar Muⱪǝddǝs Roⱨⱪa qɵmüldürülisilǝr» deginini esimgǝ aldim.
17 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run sì ti fi irú ẹ̀bùn kan náà fún wọn bí ó ti fi fún àwa pẹ̀lú nígbà tí a gba Jesu Kristi Olúwa gbọ́, ta ni èmi tí n ó fi rò pé mo le è de Ọlọ́run ní ọ̀nà?”
Xunga, ǝgǝr Huda ǝmdi muxularƣa biz Rǝb Əysa Mǝsiⱨkǝ etiⱪad ⱪilƣinimizdin keyin bizgǝ bǝrgǝn iltipatⱪa ohxax iltipat ata ⱪilƣan bolsa, Hudani tosalƣudǝk mǝn zadi kim idim?
18 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, wọ́n sì pa ẹnu wọn mọ́, wọ́n sì yin Ọlọ́run ògo wí pé, “Ǹjẹ́ Ọlọ́run fi ìrònúpìwàdà sí ìyè fún àwọn aláìkọlà pẹ̀lú!”
Ular bu sɵzlǝrni angliƣanda, ǝyiblǝxtin tohtap, Hudaƣa mǝdⱨiyǝ oⱪup: — Bǝrⱨǝⱪ, Huda ǝllǝrgimu ⱨayatliⱪⱪa elip baridiƣan towa ⱪilixni nesip ⱪiliptu! — deyixti.
19 Nítorí náà àwọn tí a sì túká kiri nípasẹ̀ inúnibíni tí ó dìde ní ti Stefanu, wọ́n rìn títí de Fonisia, àti Saipurọsi, àti Antioku, wọn kò sọ ọ̀rọ̀ náà fún ẹnìkan bí kò ṣe fún kìkì àwọn Júù.
U qaƣda, Istipanning ixi bilǝn ziyankǝxlikkǝ uqrap ⱨǝrⱪaysi jaylarƣa tarⱪilip kǝtkǝnlǝr Fǝnikiyǝ rayoni, Siprus arili wǝ Antakya xǝⱨiri ⱪatarliⱪ jaylarƣiqǝ yetip berip, bu jaylarda sɵz-kalamni pǝⱪǝt Yǝⱨudiylarƣila yǝtküzǝtti.
20 Ṣùgbọ́n àwọn kan ń bẹ nínú wọn tí ó jẹ́ ará Saipurọsi àti Kirene; nígbà tí wọ́n dé Antioku, wọ́n sọ̀rọ̀ fún àwọn Helleni pẹ̀lú, wọ́n ń wàásù ìròyìn ayọ̀ nípa Jesu Olúwa.
Lekin ulardin Siprus arili wǝ Kurini xǝⱨiridin kǝlgǝn bǝzilǝr Antakya xǝⱨirigǝ barƣanda, Rǝb Əysaning hux hǝwirini Greklǝrgimu yǝtküzdi.
21 Ọwọ́ Olúwa sì wà pẹ̀lú wọn, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn sì gbàgbọ́, wọ́n sì yípadà sí Olúwa.
Rǝbning ⱪoli ular bilǝn billǝ bolup, tolimu nurƣun kixilǝr ixinip towa ⱪilip Rǝbgǝ baƣlandi.
22 Ìròyìn nípa wọn sì dé etí ìjọ ti ó wà ni Jerusalẹmu; wọ́n sì rán Barnaba lọ títí dé Antioku;
Bu hǝwǝr Yerusalemdiki jamaǝtning ⱪuliⱪiƣa yetip kǝldi. Xuning bilǝn ular Barnabasni Antakyaƣiqǝ arilap ɵtüxkǝ ǝwǝtti.
23 Nígbà ti ó dé ti ó sì rí ẹ̀rí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run, ó yọ̀, ó sì gba gbogbo wọn níyànjú pé, pẹ̀lú ìpinnu ọkàn ni kí wọn fi ara mọ́ Olúwa.
Barnabas yetip berip, Hudaning meⱨir-xǝpⱪitini kɵrüp, huxal boldi. U ularning ⱨǝmmisini jan-dilidin ⱪǝt’iylik bilǝn Rǝbgǝ qing baƣlinixⱪa riƣbǝtlǝndürdi.
24 Nítorí òun jẹ́ ènìyàn rere, ó sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ àti fún ìgbàgbọ́; ènìyàn púpọ̀ ni a sì kà kún Olúwa.
Qünki u Muⱪǝddǝs Roⱨⱪa wǝ iman-ixǝnqkǝ toldurulƣan bolup, yahxi bir adǝm idi. Xuning bilǝn zor bir top adǝmlǝr Rǝbgǝ ⱪoxuldi.
25 Barnaba sì jáde lọ sí Tarsu láti wá Saulu,
Xuning bilǝn Barnabas Tarsus xǝⱨirigǝ Saulni izdǝp bardi.
26 nígbà tí ó sì rí i, ó mú un wá sí Antioku. Fún ọdún kan gbáko ni wọ́n fi ń bá ìjọ péjọpọ̀, tí wọ́n sì kọ́ ènìyàn púpọ̀. Ní Antioku ni a sì kọ́kọ́ ti pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ni “Kristiani.”
Uni tepip Antakyaƣa elip kǝldi; xundaⱪ boldiki, ikkiylǝn jamaǝt bilǝn billǝ saⱪ bir yil yiƣilip, nurƣun adǝmgǝ tǝlim bǝrdi. Muhlislarning «Hristianlar» dǝp tunji atilixi Antakyadin baxlandi.
27 Ní ọjọ́ wọ̀nyí ni àwọn wòlíì sì ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ wá sí Antioku.
U künlǝrdǝ bǝzi pǝyƣǝmbǝrlǝr Yerusalemdin Antakyaƣa qüxüp kǝldi.
28 Nígbà tí ọ̀kan nínú wọn, ti a ń pè ni Agabu sí dìde, ó ti ipa Ẹ̀mí sọ pé, ìyàn ńlá yóò mú yíká gbogbo ilẹ̀ Romu. (Èyí sì ṣẹlẹ̀ nígbà ìṣèjọba Kilaudiu.)
Bulardin Agabus isimlik birǝylǝn otturiƣa qiⱪip, Roⱨning wǝⱨiyini yǝtküzüp, ⱪattiⱪ bir aqarqiliⱪning pütkül dunyani basidiƣanliⱪini aldin eytti (bu aqarqiliⱪ dǝrwǝⱪǝ «Klawdiyus Ⱪǝysǝr» ⱨɵküm sürgǝn waⱪitta yüz bǝrdi).
29 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sì pinnu, olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí agbára rẹ̀ ti tó, láti rán ìrànlọ́wọ́ sí àwọn arákùnrin tí ó wà ní Judea.
Buning bilǝn [Antakyadiki] muhlislarning ⱨǝrbiri ɵz ⱪurbiƣa ⱪarap pul yiƣip, Yǝⱨudiyǝdǝ turuwatⱪan ⱪerindaxlarƣa yardǝm berixni ⱪarar ⱪildi.
30 Wọn sì ṣe bẹ́ẹ̀, wọn sì fi ẹ̀bùn ránṣẹ́ sí àwọn àgbà láti ọwọ́ Barnaba àti Saulu.
Ular bu ⱪararni ada ⱪilip, ianini Barnabas wǝ Saulning ⱪoli arⱪiliⱪ [Yǝⱨudiyǝdiki jamaǝt] aⱪsaⱪalliriƣa yǝtküzüp bǝrdi.