< 3 John 1 >

1 Alàgbà, Sì Gaiusi, olùfẹ́, ẹni tí mo fẹ́ nínú òtítọ́.
ⲁ̅ⲡⲓ⳿ⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲛⲅⲁⲓⲟⲥ ⲡⲓⲁⲅⲁⲡⲏⲧⲟⲥ ⲫⲏ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⳿ⲉϯⲙⲉⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ.
2 Olùfẹ́, èmi ń gbàdúrà pé nínú ohun gbogbo kí o lè máa dára fún ọ, kí o sì máa wà ni ìlera, àní bí o tí dára fún ọkàn rẹ.
ⲃ̅ⲡⲁⲙⲉⲛⲣⲓⲧ ϯⲧⲱⲃϩ ⲉⲑⲃⲉ ϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲑⲣⲉ ⲛⲉⲕⲙⲱⲓⲧ ⲥⲱⲟⲩⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲟⲩϫⲁⲓ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲉ ⲛⲉⲛⲙⲱⲓⲧ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲯⲩⲭⲏ ⲥⲟⲩⲧⲱⲛ.
3 Nítorí mo yọ̀ gidigidi, nígbà tí àwọn arákùnrin dé tí wọn sì jẹ́rìí sí ìwà òtítọ́ inú rẹ̀, àní bí ìwọ tí ń rìn nínú òtítọ́.
ⲅ̅ⲁⲓⲣⲁϣⲓ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ ⲉⲧⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁⲩⲉⲣⲙⲉⲑⲣⲉ ϧⲁ ⲧⲉⲕⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲑⲟⲕ ⲉⲧⲉⲕⲙⲟϣⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ.
4 Èmi ni ayọ̀ tí ó tayọ, láti máa gbọ́ pé, àwọn ọmọ mi ń rìn nínú òtítọ́.
ⲇ̅⳿ⲙⲙⲟⲛϯ ⳿ϩⲙⲟⲧ ⲅⲁⲣ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲛⲛⲓϣϯ ⳿ⲉⲫⲁⲓ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲁⲥⲱⲧⲉⲙ ⲉⲑⲃⲉ ⲛⲁϣⲏⲣⲓ ϫⲉ ⲥⲉⲙⲟϣⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ.
5 Olùfẹ́, ìwọ ń ṣe olóòtítọ́ nínú iṣẹ́ tí ìwọ ń ṣe fún àwọn tí ń ṣe ará, àti pàápàá fún àwọn tí ń ṣe àlejò.
ⲉ̅ⲡⲓⲁⲅⲁⲡⲏⲧⲟⲥ ⲟⲩϩⲱⲃ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲧⲟⲥ ⲉⲧⲉⲕ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲉⲕⲉⲣϩⲱⲃ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲁⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓϣⲉⲙⲙⲱⲟⲩ.
6 Tí wọn ń jẹ́rìí sí ìfẹ́ rẹ̀ níwájú ìjọ, bí ìwọ bá ń pèsè fún wọn ní ọ̀nà àjò wọn gẹ́gẹ́ bí ó tí yẹ nínú Ọlọ́run.
ⲋ̅ⲛⲁⲓ ⲉⲧⲁⲩⲉⲣⲙⲉⲑⲣⲉ ϧⲁ ⲧⲉⲕⲁⲅⲁⲡⲏ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲉⲕ⳿ⲕⲗⲏⲥⲓⲁ ⲛⲁⲓ ⲉⲧⲉ ⲕⲁⲗⲱⲥ ⳿ⲭⲛⲁⲁⲓⲥ ⲉⲕ⳿ⲧⲫⲟ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ⲙ⳿ⲡϣⲁ ⳿ⲙⲫϯ.
7 Nítorí pé, nítorí iṣẹ́ Kristi ni wọ́n ṣe jáde lọ, láìgba ohunkóhun lọ́wọ́ àwọn aláìkọlà.
ⲍ̅ⲉⲧⲁⲩ⳿ⲓ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲡⲓⲣⲁⲛ ⳿ⲛⲥⲉϭⲓ ⳿ϩⲗⲓ ⲁⲛ ⳿ⲛⲧⲉⲛ ⲛⲓⲉⲑⲛⲓⲕⲟⲥ.
8 Nítorí náà, ó yẹ kí àwa fi inú rere gba irú àwọn wọ̀nyí, kí àwa lè jẹ́ alábáṣiṣẹ́pọ̀ pẹ̀lú òtítọ́.
ⲏ̅⳿ⲁⲛⲟⲛ ⲟⲩⲛ ⳿ⲥϣⲉ ⲛⲁⲛ ⳿ⲉϣⲉⲡ ⲛⲁⲓⲟⲩⲟⲛ ⳿ⲙⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⳿ⲉⲣⲟⲛ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲉⲣ⳿ϣⲫⲏⲣ ⳿ⲛⲉⲣϩⲱⲃ ⳿ⲉϯⲙⲉⲑⲙⲏⲓ.
9 Èmi kọ̀wé sí ìjọ ṣùgbọ́n Diotirefe, ẹni tí ó fẹ́ láti jẹ́ ẹni pàtàkì jùlọ, kò gbà wá.
ⲑ̅ⲁⲕ⳿ⲥϧⲁⲓ ⳿ⲛⲟⲩϩⲱⲃ ⳿ⲛϯⲉⲕ⳿ⲕⲗⲏⲥⲓⲁ ⲁⲗⲗⲁ ⲇⲓⲟⲧⲣⲉⲫⲏⲥ ⲡⲓⲙⲁⲓⲉⲣϩⲟⲩⲓⲧ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ⳿ϥϣⲏⲡ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲁⲛ.
10 Nítorí náà bí mo bá dé, èmi yóò mú iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ṣe wá sì ìrántí rẹ, tí ó ń sọ ọ̀rọ̀ búburú àti ìsọkúsọ sí wa, èyí kò sì tún tẹ́ ẹ lọ́rùn, síbẹ̀ òun fúnra rẹ̀ kọ̀ láti gba àwọn ará, àwọn tí ó sì ń fẹ́ gbà wọ́n, ó ń dá wọn lẹ́kun, ó sì ń lé wọn kúrò nínú ìjọ.
ⲓ̅ⲉⲑⲃⲉⲫⲁⲓ ⲁⲓϣⲁⲛ⳿ⲓ ϯⲛⲁ⳿ⲑⲣⲉϥⲉⲣ⳿ⲫⲙⲉⲩⲓ ⳿ⲛⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲧⲉϥ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲉϥⲉⲣ⳿ⲫⲗⲟⲓⲁⲣⲓⲛ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ϧⲉⲛ ϩⲁⲛⲥⲁϫⲓ ⳿ⲙⲡⲟⲛⲏⲣⲟⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ϥⲕⲏⲛ ⲁⲛ ϧⲉⲛ ⲛⲁⲓ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⳿ϥϣⲱⲡ ⳿ⲛⲛⲓ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲏⲉⲑⲟⲩⲱϣ ⳿ⲉϣⲟⲡⲟⲩ ⳿ϥⲭⲱ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥⲥⲓϯ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ϯⲉⲕ⳿ⲕⲗⲏⲥⲓⲁ.
11 Olùfẹ́, má ṣe ṣe àfarawé ohun tí í ṣe ibi bí kò ṣe ohun tí ṣe rere. Ẹni tí ó bá ń ṣe rere ti Ọlọ́run ni; ẹni tí ó ba ń ṣe búburú kò rí Ọlọ́run.
ⲓ̅ⲁ̅ⲡⲁⲙⲉⲛⲣⲓⲧ ⳿ⲙⲡⲉⲣⲧⲉⲛⲑⲱⲛⲕ ⳿ⲉⲡⲓⲡⲉⲧϩⲱⲟⲩ ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲉⲡⲓⲡⲉⲑⲛⲁⲛⲉϥ ⲫⲏⲉⲧ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲡⲉⲑⲛⲁⲛⲉϥ ⲟⲩ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲫϯ ⲡⲉ ⲫⲏ ⲇⲉ ⲉⲧ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲡⲉⲧϩⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲡⲉϥⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲫϯ.
12 Demetriusi ní ẹ̀rí rere lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn àti ní ti òtítọ́ fúnra rẹ̀ pẹ̀lú; nítòótọ́, àwa pẹ̀lú sì gba ẹ̀rí rẹ̀ jẹ́; ẹ̀yin sì mọ̀ pé, òtítọ́ ni ẹ̀rí wa.
ⲓ̅ⲃ̅ⲁⲩⲉⲣⲙⲉⲑⲣⲉ ⳿ⲛⲇⲓⲙⲏⲧⲣⲓⲟⲥ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ϩⲓⲧⲉⲛ ⳿ⲑⲙⲏⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲁⲛⲟⲛ ⲧⲉⲛⲉⲣⲙⲉⲑⲣⲉ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲕⲥⲱⲟⲩⲛ ϫⲉ ⲧⲉⲛⲙⲉⲧⲙⲉⲑⲣⲉ ⲟⲩⲙⲏⲓ ⲧⲉ.
13 Èmí ní ohun púpọ̀ láti kọ sínú ìwé sí ọ, ṣùgbọ́n èmi kò fẹ́ fi kálàmù àti tawada kọ wọ́n sínú ìwé.
ⲓ̅ⲅ̅⳿ⲉⲟⲩⲟⲛϯ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲉ⳿ⲥϧⲏⲧⲟⲩ ⲛⲁⲕ ⲡⲉ ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲛϯⲟⲩⲱϣ ⲁⲛ ⳿ⲉ⳿ⲥϧⲁⲓ ⲛⲁⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲗⲁ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲕⲁϣ.
14 Mo ni ìrètí láti rí ọ láìpẹ́, tí àwa yóò sì sọ̀rọ̀ lójúkojú. Àlàáfíà fún ọ. Àwọn ọ̀rẹ́ wa tó wà níbí kí ọ. Kí àwọn ọ̀rẹ́ wa tó wà lọ́dọ̀ rẹ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
ⲓ̅ⲇ̅ϯⲉⲣϩⲉⲗⲡⲓⲥ ⲇⲉ ⲥⲁⲧⲟⲧ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲉⲛⲉⲣⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲣⲟ ⲟⲩⲃⲉ ⲣⲟ. ⳿ⲧϩⲓⲣⲏⲛⲏ ⲛⲁⲕ ⲥⲉϣⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓ⳿ϣⲫⲉⲣ ϣⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲛⲓ⳿ϣⲫⲉⲣ ⲕⲁⲧⲁ ⲛⲟⲩⲣⲁⲛ ⲓⲱⲁⲛⲛⲟⲩ ⲉⲡⲓⲥⲧⲟⲗ ⲅ̅

< 3 John 1 >