< 2 Thessalonians 1 >

1 Paulu, Sila àti Timotiu, Sí ìjọ Tẹsalonika, nínú Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi Olúwa:
پَولَح سِلْوانَسْتِیمَتھِیَشْچیتِنامانو وَیَمْ اَسْمَدِییَتاتَمْ اِیشْوَرَں پْرَبھُں یِیشُکھْرِیشْٹَنْچاشْرِتاں تھِشَلَنِیکِناں سَمِتِں پْرَتِ پَتْرَں لِکھامَح۔
2 Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa.
اَسْماکَں تاتَ اِیشْوَرَح پْرَبھُ رْیِیشُکھْرِیشْٹَشْچَ یُشْماسْوَنُگْرَہَں شانْتِنْچَ کْرِیاسْتاں۔
3 Ó yẹ kí a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará, àní gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, nítorí pé ìgbàgbọ́ yín ń dàgbà gidigidi, àti ìfẹ́ olúkúlùkù yín sí ara yín ń di púpọ̀.
ہے بھْراتَرَح، یُشْماکَں کرِتے سَرْوَّدا یَتھایوگْیَمْ اِیشْوَرَسْیَ دھَنْیَوادو سْمابھِح کَرْتَّوْیَح، یَتو ہیتو رْیُشْماکَں وِشْواسَ اُتَّروتَّرَں وَرْدّھَتے پَرَسْپَرَمْ ایکَیکَسْیَ پْریمَ چَ بَہُپھَلَں بھَوَتِ۔
4 Nítorí náà, àwa tìkára wa ń fi yín ṣògo nínú ìjọ Ọlọ́run, nítorí sùúrù àti ìgbàgbọ́ yín nínú gbogbo inúnibíni àti wàhálà yín tí ẹ̀yin náà ń fi ara dà.
تَسْمادْ یُشْمابھِ رْیاوَنْتَ اُپَدْرَوَکْلیشاح سَہْیَنْتے تیشُ یَدْ دھےرْیَّں یَشْچَ وِشْواسَح پْرَکاشْیَتے تَتْکارَنادْ وَیَمْ اِیشْوَرِییَسَمِتِشُ یُشْمابھِح شْلاگھامَہے۔
5 Àwọn nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ẹ̀rí pé òdodo ni ìdájọ́ Ọlọ́run àti pé nítorí èyí ni a ó kà yín yẹ fún ìjọba Ọlọ́run, nítorí èyí tí ẹ̀yin pẹ̀lú ṣe ń jìyà.
تَچّیشْوَرَسْیَ نْیایَوِچارَسْیَ پْرَمانَں بھَوَتِ یَتو یُویَں یَسْیَ کرِتے دُحکھَں سَہَدھْوَں تَسْییشْوَرِییَراجْیَسْیَ یوگْیا بھَوَتھَ۔
6 Olódodo ni Ọlọ́run: Òun yóò pọ́n àwọn tí ń pọ́n yín lójú, lójú,
یَتَح سْوَکِییَسْوَرْگَدُوتاناں بَلَیح سَہِتَسْیَ پْرَبھو رْیِیشوح سْوَرْگادْ آگَمَنَکالے یُشْماکَں کْلیشَکیبھْیَح کْلیشینَ پھَلَدانَں سارْدّھَمَسْمابھِشْچَ
7 Òun yóò sì fi ìtura fún ẹ̀yin tí a ti pọ́n lójú àti fún àwa náà pẹ̀lú. Èyí yóò sì ṣe nígbà ìfarahàn Jesu Olúwa láti ọ̀run wá fún wá nínú ọwọ́ iná pẹ̀lú àwọn angẹli alágbára.
کْلِشْیَمانیبھْیو یُشْمَبھْیَں شانْتِدانَمْ اِیشْوَرینَ نْیایَّں بھوتْسْیَتے؛
8 Òun yóò fi ìyà jẹ àwọn tí kò mọ Ọlọ́run àti àwọn tí ń ṣe àìgbọ́ràn sí ìyìnrere Jesu Olúwa wa.
تَدانِیمْ اِیشْوَرانَبھِجْنیبھْیو سْمَتْپْرَبھو رْیِیشُکھْرِیشْٹَسْیَ سُسَںواداگْراہَکیبھْیَشْچَ لوکیبھْیو جاجْوَلْیَمانینَ وَہْنِنا سَمُچِتَں پھَلَں یِیشُنا داسْیَتے؛
9 A ó fi ìparun àìnípẹ̀kun jẹ wọ́n ní yà, a ó sì ṣe wọn mọ̀ kúrò níwájú Olúwa àti inú ògo agbára rẹ̀, (aiōnios g166)
تے چَ پْرَبھو رْوَدَناتْ پَراکْرَمَیُکْتَوِبھَواچَّ سَداتَنَوِناشَرُوپَں دَنْڈَں لَپْسْیَنْتے، (aiōnios g166)
10 ní ọjọ́ tí yóò jẹ́ ẹni tí a ó yìn lógo nínú àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ àti ẹni àwòyanu ní àárín gbogbo àwọn tí ó ti gbàgbọ́. Èyí kò yọ yín sílẹ̀, nítorí ẹ ti gba ẹ̀rí tí a jẹ́ sí yín gbọ́.
کِنْتُ تَسْمِنْ دِنے سْوَکِییَپَوِتْرَلوکیشُ وِراجِتُں یُشْمانْ اَپَراںشْچَ سَرْوّانْ وِشْواسِلوکانْ وِسْماپَیِتُنْچَ سَ آگَمِشْیَتِ یَتو سْماکَں پْرَمانے یُشْمابھِ رْوِشْواسوکارِ۔
11 Nítorí èyí, àwa pẹ̀lú ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo, pé kí Ọlọ́run wa kí ó lè kà yín yẹ fún ìpè rẹ̀, àti pé nípa agbára rẹ̀, òun yóò mú gbogbo èrò rere yín ṣẹ àti gbogbo ohun tí ìgbàgbọ́ bá rú jáde.
اَتوسْماکَمْ اِیشْوَرو یُشْمانْ تَسْیاہْوانَسْیَ یوگْیانْ کَروتُ سَوجَنْیَسْیَ شُبھَپھَلَں وِشْواسَسْیَ گُنَنْچَ پَراکْرَمینَ سادھَیَتْوِتِ پْرارْتھَناسْمابھِح سَرْوَّدا یُشْمَنِّمِتَّں کْرِیَتے،
12 Wọ̀nyí ni àdúrà wa, kí orúkọ Jesu Olúwa wa lè di yíyìn lógo nínú yín àti ẹ̀yin nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run àti ti Jesu Kristi Olúwa.
یَتَسْتَتھا سَتْیَسْماکَمْ اِیشْوَرَسْیَ پْرَبھو رْیِیشُکھْرِیشْٹَسْیَ چانُگْرَہادْ اَسْمَتْپْرَبھو رْیِیشُکھْرِیشْٹَسْیَ نامْنو گَورَوَں یُشْماسُ یُشْماکَمَپِ گَورَوَں تَسْمِنْ پْرَکاشِشْیَتے۔

< 2 Thessalonians 1 >