< 2 Thessalonians 1 >
1 Paulu, Sila àti Timotiu, Sí ìjọ Tẹsalonika, nínú Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi Olúwa:
Ja, Paweł, wraz z Sylwanem i Tymoteuszem, piszę do kościoła Tesaloniczan, który należy do Boga, naszego Ojca, i Pana, Jezusa Chrystusa.
2 Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa.
Niech Bóg, nasz Ojciec, i Pan, Jezus Chrystus, obdarzają was łaską i pokojem!
3 Ó yẹ kí a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará, àní gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, nítorí pé ìgbàgbọ́ yín ń dàgbà gidigidi, àti ìfẹ́ olúkúlùkù yín sí ara yín ń di púpọ̀.
Przyjaciele, coraz bardziej wierzycie Panu a wasza wzajemna miłość ciągle wzrasta! Naprawdę mamy powód do tego, aby zawsze dziękować za was Bogu!
4 Nítorí náà, àwa tìkára wa ń fi yín ṣògo nínú ìjọ Ọlọ́run, nítorí sùúrù àti ìgbàgbọ́ yín nínú gbogbo inúnibíni àti wàhálà yín tí ẹ̀yin náà ń fi ara dà.
Odwiedzając inne kościoły, z dumą opowiadamy o tym, że nawet prześladowania i trudności nie są w stanie osłabić waszej wytrwałości i wiary.
5 Àwọn nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ẹ̀rí pé òdodo ni ìdájọ́ Ọlọ́run àti pé nítorí èyí ni a ó kà yín yẹ fún ìjọba Ọlọ́run, nítorí èyí tí ẹ̀yin pẹ̀lú ṣe ń jìyà.
A wszystko to świadczy o sprawiedliwości Bożego sądu. Skoro cierpicie dla Jego królestwa, znaczy to, że jesteście godni do niego wejść.
6 Olódodo ni Ọlọ́run: Òun yóò pọ́n àwọn tí ń pọ́n yín lójú, lójú,
Sprawiedliwe też jest to, że Bóg ukaże tych, którzy was prześladują,
7 Òun yóò sì fi ìtura fún ẹ̀yin tí a ti pọ́n lójú àti fún àwa náà pẹ̀lú. Èyí yóò sì ṣe nígbà ìfarahàn Jesu Olúwa láti ọ̀run wá fún wá nínú ọwọ́ iná pẹ̀lú àwọn angẹli alágbára.
a wam—i nam również—da odpocząć po tych wszystkich trudnościach. Stanie się to wtedy, gdy nasz Pan, Jezus, zstąpi z nieba razem z potężnymi aniołami.
8 Òun yóò fi ìyà jẹ àwọn tí kò mọ Ọlọ́run àti àwọn tí ń ṣe àìgbọ́ràn sí ìyìnrere Jesu Olúwa wa.
Wówczas w płomieniach ognia ukarze tych, którzy zlekceważyli Boga i odrzucili Jego dobrą nowinę.
9 A ó fi ìparun àìnípẹ̀kun jẹ wọ́n ní yà, a ó sì ṣe wọn mọ̀ kúrò níwájú Olúwa àti inú ògo agbára rẹ̀, (aiōnios )
Ludzie ci zostaną skazani na wieczną zagładę—zostaną odcięci od obecności, majestatu i potęgi Pana. (aiōnios )
10 ní ọjọ́ tí yóò jẹ́ ẹni tí a ó yìn lógo nínú àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ àti ẹni àwòyanu ní àárín gbogbo àwọn tí ó ti gbàgbọ́. Èyí kò yọ yín sílẹ̀, nítorí ẹ ti gba ẹ̀rí tí a jẹ́ sí yín gbọ́.
W owym dniu Pan przyjdzie, aby odebrać chwałę i uwielbienie od swoich świętych i od wszystkich, którzy Mu uwierzyli. Wy również będziecie wśród nich, bo uwierzyliście w to, co wam przekazaliśmy.
11 Nítorí èyí, àwa pẹ̀lú ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo, pé kí Ọlọ́run wa kí ó lè kà yín yẹ fún ìpè rẹ̀, àti pé nípa agbára rẹ̀, òun yóò mú gbogbo èrò rere yín ṣẹ àti gbogbo ohun tí ìgbàgbọ́ bá rú jáde.
Dlatego nieustannie modlimy się o was, abyście postępowali w sposób zgodny z waszym powołaniem i aby Bóg dał wam moc do wykonania tego, co zamierzacie i czego już się podjęliście. Są to bowiem czyny będące skutkiem waszej wiary.
12 Wọ̀nyí ni àdúrà wa, kí orúkọ Jesu Olúwa wa lè di yíyìn lógo nínú yín àti ẹ̀yin nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run àti ti Jesu Kristi Olúwa.
Postępując tak, oddacie chwałę naszemu Panu, Jezusowi Chrystusowi, a On otoczy chwałą również was. Wszystko to jest możliwe wyłącznie dzięki łasce, okazanej nam przez naszego Boga oraz Jezusa Chrystusa, naszego Pana.