< 2 Samuel 8 >

1 Ó sì ṣe, lẹ́yìn èyí, Dafidi sì kọlu àwọn Filistini, ó sì tẹrí wọn ba, Dafidi sì gba Metegamima lọ́wọ́ àwọn Filistini.
Thuutha wa mahinda macio-rĩ, Daudi nĩatharĩkĩire Afilisti na akĩmatooria biũ, na agĩtunyana Methegi-Amma kuuma watho-inĩ wa Afilisti.
2 Dafidi sì kọlu Moabu, ó sì fi okùn títa kan dì wọ́n, ó sì dá wọn dùbúlẹ̀; ó sì ṣe òsùwọ̀n okùn méjì ni iye àwọn tí yóò dá sí. Àwọn ará Moabu sì ń sin Dafidi, wọn a sì máa mú ẹ̀bùn wá.
Ningĩ Daudi nĩatooririe andũ a Moabi. Agĩtũma makome thĩ na akĩmathima na ũraihu wa rũrigi. Aamathima-rĩ, ithimi igĩrĩ ciao makooragwo, na gĩthimi gĩa gatatũ mageetĩkĩrio matũũre muoyo. Nĩ ũndũ ũcio andũ a Moabi magĩtuĩka ndungata cia Daudi na makamũrehagĩra igooti.
3 Dafidi sì kọlu Hadadeseri ọmọ Rehobu, ọba Soba, bí òun sì ti ń lọ láti mú agbára rẹ̀ bọ̀ sípò ni odò Eufurate.
Daudi nĩahũũranire na Hadadezeri mũrũ wa Rehobu, mũthamaki wa Zoba, rĩrĩa aathiĩte gũcookia bũrũri ũrĩa aatunyĩtwo gũkuhĩ na Rũũĩ rwa Farati.
4 Dafidi sì gba ẹgbẹ̀rún kẹ̀kẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀, àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin ẹlẹ́ṣin, àti ogún ẹgbẹ̀rún àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀. Dafidi sì já gbogbo àwọn ẹṣin kẹ̀kẹ́ wọn ní pàtì, ṣùgbọ́n ó dá ọgọ́rùn-ún kẹ̀kẹ́ sí nínú wọn.
Nake Daudi akĩmũtunya ngaari ciake cia ita ngiri ĩmwe, na andũ a gũcitwara ngiri mũgwanja, na thigari cia magũrũ ngiri mĩrongo ĩĩrĩ. Nake agĩtemenga mbarathi icio cia mbaara magũrũ agĩtũma ithue ciothe tiga o igana rĩmwe.
5 Nígbà tí àwọn ará Siria ti Damasku sì wá láti ran Hadadeseri ọba Soba lọ́wọ́, Dafidi sì pa ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ènìyàn nínú àwọn ará Siria.
Rĩrĩa Asuriata a kuuma Dameski mookire gũteithia Hadadezeri mũthamaki wa Zoba, Daudi akĩũraga Asuriata ngiri mĩrongo ĩĩrĩ na igĩrĩ.
6 Dafidi sì fi àwọn ológun sí Siria ti Damasku, àwọn ará Siria sì wá sin Dafidi, wọn a sì máa mú ẹ̀bùn wá, Olúwa sì pa Dafidi mọ́ níbikíbi tí o ń lọ.
Akĩiga mbũtũ cia kũrangĩra ũthamaki wa Asuriata kũu Dameski. Nao Asuriata magĩtuĩka a gwathagwo nĩwe makamũrehagĩra igooti. Jehova nĩaheaga Daudi ũhootani kũrĩa guothe aathiiaga.
7 Dafidi sì gba àṣà wúrà tí ó wà lára àwọn ìránṣẹ́ Hadadeseri, ó sì gbé wọn wá sí Jerusalẹmu.
Na rĩrĩ, Daudi agĩkuua ngo cia thahabu iria ciarĩ cia atongoria a Hadadezeri agĩcirehe Jerusalemu.
8 Láti Beta, àti láti Berotai, àwọn ìlú Hadadeseri, ọba Dafidi kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ idẹ wá.
Kuuma matũũra ma Teba na Berothai, marĩa maarĩ ma Hadadezeri, Mũthamaki Daudi agĩkuua kuuma kuo indo nyingĩ mũno cia gĩcango.
9 Nígbà tí Tou ọba Hamati sì gbọ́ pé Dafidi ti pa gbogbo ogun Hadadeseri.
Rĩrĩa Tou mũthamaki wa Hamathu aaiguire atĩ Daudi nĩahootete mbũtũ ciothe cia mbaara cia Hadadezeri-rĩ,
10 Toi sì rán Joramu ọmọ rẹ̀ sí Dafidi ọba, láti kí i, àti láti súre fún un, nítorí pé ó tí bá Hadadeseri jagun, ó sì ti pa á, nítorí tí Hadadeseri sá à ti bá Toi jagun. Joramu sì ni ohun èlò fàdákà, àti ohun èlò wúrà, àti ohun èlò idẹ ní ọwọ́ rẹ̀.
agĩtũma mũriũ Joramu kũrĩ Mũthamaki Daudi akamũgeithie na amũkũngũĩre nĩ ũndũ wa kũhoota Hadadezeri, ũrĩa wakoretwo akĩrũa na Tou. Joramu akĩmũrehera indo cia betha na cia thahabu, o na cia gĩcango.
11 Dafidi ọba sì fi wọ́n fún Olúwa pẹ̀lú fàdákà, àti wúrà tí ó yà sí mímọ́, èyí tí ó ti gbà lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí ó ti ṣẹ́gun.
Mũthamaki Daudi akĩamũrĩra Jehova indo icio, o ta ũrĩa aamũrĩte betha na thahabu kuuma ndũrĩrĩ-inĩ ciothe iria aatooretie.
12 Lọ́wọ́ Siria àti lọ́wọ́ Moabu àti lọ́wọ́ àwọn ọmọ Ammoni, àti lọ́wọ́ àwọn Filistini, àti lọ́wọ́ Amaleki, àti nínú ìkógun Hadadeseri ọmọ Rehobu ọba Soba.
Nacio nĩ Edomu na Moabi, na Aamoni na Afilisti, na Amaleki. Ningĩ akĩamũra indo iria aatahĩte kuuma kũrĩ Hadadezeri mũrũ wa Rehobu mũthamaki wa Zoba.
13 Dafidi sì ní òkìkí gidigidi nígbà tí ó padà wá ilé láti ibi pípa àwọn ará Siria ní àfonífojì Iyọ̀, àwọn tí o pa jẹ́ ẹgbàá mẹ́sàn ènìyàn.
Nake Daudi akĩgĩa igweta hĩndĩ ĩrĩa oimire kũũraga andũ a Edomu ngiri ikũmi na inyanya Gĩtuamba-inĩ gĩa Cumbĩ.
14 Ó sì fi àwọn ológun sí Edomu; àti ní gbogbo Edomu yíká ni òun sì fi ológun sí, gbogbo àwọn tí ó wà ní Edomu sì wá sin Dafidi, Olúwa sì fún Dafidi ní ìṣẹ́gun níbikíbi tí ó ń lọ.
Nake akĩiga thigari cia kũrangĩra Edomu guothe, nao andũ a Edomu othe magĩtuĩka ndungata cia Daudi. Nake Jehova nĩaheaga Daudi ũhootani kũrĩa guothe aathiiaga.
15 Dafidi sì jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli; Dafidi sì ṣe ìdájọ́ àti òtítọ́ fún àwọn ènìyàn rẹ̀.
Daudi nĩathamakire Isiraeli guothe, akahũthagĩra kĩhooto, na akahingĩria andũ ake othe maũndũ marĩa maagĩrĩire.
16 Joabu ọmọ Seruiah ni ó sì ń ṣe olórí ogun; Jehoṣafati ọmọ Ahiludi sì ń ṣe akọ̀wé.
Joabu mũrũ wa Zeruia nĩwe warĩ mũnene wa ita; nake Jehoshafatu mũrũ wa Ehiludu nĩwe warĩ mwandĩki wa maũndũ ma ihinda rĩu;
17 Sadoku ọmọ Ahitubu, àti Ahimeleki ọmọ Abiatari, ni àwọn àlùfáà; Seraiah a sì máa ṣe akọ̀wé.
nake Zadoku mũrũ wa Ahitubu na Ahimeleku mũrũ wa Abiatharu maarĩ athĩnjĩri-Ngai; nake Seraia aarĩ mwandĩki.
18 Benaiah ọmọ Jehoiada ni ó sì ń ṣe olórí àwọn Kereti, àti àwọn Peleti; àwọn ọmọ Dafidi sì jẹ́ aláṣẹ.
Nake Benaia mũrũ wa Jehoiada nĩwe warĩ mũnene wa Akerethi na Apelethi; nao ariũ a Daudi maarĩ ataari a mũthamaki.

< 2 Samuel 8 >