< 2 Samuel 7 >

1 Ó sì ṣe, nígbà tí ọba ń gbé ní ilé rẹ̀, tí Olúwa sì fún un ní ìsinmi yíkákiri kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Na rĩrĩ, thuutha wa mũthamaki gũikara nyũmba yake ya ũthamaki, nake Jehova akamũhe ũhurũko agatiga gũũkĩrĩrwo nĩ thũ ciake ciothe iria ciamũrigiicĩirie-rĩ,
2 Ọba sì wí fún Natani wòlíì pé, “Sá wò ó, èmi ń gbé inú ilẹ̀ tí a fi kedari kọ́, ṣùgbọ́n àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run ń gbé inú ibi tí a fi aṣọ gé.”
akĩĩra mũnabii Nathani atĩrĩ, “Niĩ njikaraga nyũmba ya ũthamaki yaakĩtwo na mĩtarakwa, o rĩrĩa ithandũkũ rĩa Ngai rĩigĩtwo hema-inĩ.”
3 Natani sì wí fún ọba pé, “Lọ, kí o sì ṣe gbogbo èyí tí ó wà ní ọkàn rẹ, nítorí pé Olúwa wà pẹ̀lú rẹ.”
Nathani agĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Ũndũ ũrĩa ũreciiria, gwĩka ĩka guo tondũ Jehova arĩ hamwe nawe.”
4 Ó sì ṣe ní òru náà, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Natani wá pé,
Ũtukũ ũcio kiugo kĩa Jehova gĩgĩkinyĩra Nathani, akĩĩrwo atĩrĩ:
5 “Lọ, sọ fún ìránṣẹ́ mi, fún Dafidi pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, ìwọ ó ha kọ́ ilé fún mi tí èmi yóò gbé.
“Thiĩ ũkeere ndungata yakwa Daudi atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga ũũ: Anga we nĩwe ũkũnjakĩra nyũmba nĩguo ndĩmĩtũũre?
6 Nítorí pé, èmi kò ì ti gbé inú ilé kan láti ọjọ́ tí èmi ti mú àwọn ọmọ Israẹli gòkè ti ilẹ̀ Ejibiti wá, títí di òní yìí, ṣùgbọ́n èmi ti ń rìn nínú àgọ́, fún ibùgbé mi.
Niĩ ndirĩ ndatũũra nyũmba kuuma mũthenya ũrĩa ndaarutire andũ a Isiraeli kuuma bũrũri wa Misiri nginya ũmũthĩ. Ndũũraga thiiaga kũndũ na kũndũ ndĩ hema-inĩ arĩ yo gĩtũũro gĩakwa.
7 Ní ibi gbogbo tí èmi ti ń rìn pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ǹjẹ́ èmi ti bá ọ̀kan nínú ẹ̀yà Israẹli, tí èmi pa àṣẹ fún láti máa bọ́ àwọn ènìyàn mi àní Israẹli, sọ̀rọ̀ pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin kò fi kedari kọ́ ilé fún mi.”’
Kũrĩa guothe ndanathiĩ na andũ a Isiraeli othe-rĩ, ndĩ ndooria mũtongoria o na ũmwe wao, arĩa ndaathire marĩithagie andũ akwa a Isiraeli, atĩrĩ, “Mwagĩte kũnjakĩra nyũmba ya mĩtarakwa nĩkĩ?”’
8 “Ǹjẹ́, nítorí náà, báyìí ni ìwọ yóò sì wí fún ìránṣẹ́ mi àní Dafidi pé, ‘Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, Èmi ti mú ìwọ kúrò láti inú agbo àgùntàn wá láti má tẹ̀lé àwọn àgùntàn, mo sì fi ọ́ jẹ olórí àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli.
“Na rĩrĩ, ĩra ndungata yakwa Daudi atĩrĩ, ‘Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga ũũ: Ndaakũrutire rũũru-inĩ ngĩgũtigithia kũrũmĩrĩra mahiũ nĩguo ũtuĩke mwathi wa andũ akwa a Isiraeli.
9 Èmi sì wà pẹ̀lú rẹ níbikíbi tí ìwọ ń lọ, èmi sá à gé gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ kúrò níwájú rẹ, èmi sì ti sọ orúkọ rẹ di ńlá, gẹ́gẹ́ bí orúkọ àwọn ènìyàn ńlá tí ó wà ní ayé.
Nĩ ngoretwo nawe o kũrĩa guothe wanathiĩ, na ngakwehereria thũ ciaku ciothe ikeehera mbere yaku. Rĩu nĩngũtũma rĩĩtwa rĩaku rĩtuĩke inene, o ta marĩĩtwa ma andũ arĩa anene mũno a thĩ.
10 Èmi ó sì yan ibìkan fún àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli, èmi ó sì gbìn wọ́n, wọn ó sì má gbé bí ibùjókòó tiwọn, wọn kì yóò sì sípò padà mọ́; àwọn ọmọ ènìyàn búburú kì yóò sì pọ́n wọn lójúmọ́, bí ìgbà àtijọ́.
Na nĩngaahe andũ akwa a Isiraeli handũ, na ndĩmahaande wega nĩgeetha magĩe na mũciĩ wao kĩũmbe, na matigacooka gũthĩĩnĩka. Andũ aaganu matigacooka kũmahinyĩrĩria rĩngĩ, o ta ũrĩa maatũire meekaga kĩambĩrĩria-inĩ,
11 Àti gẹ́gẹ́ bí àkókò ìgbà tí èmi ti fi àṣẹ fún àwọn onídàájọ́ lórí àwọn ènìyàn mi, àní Israẹli, èmi fi ìsinmi fún ọ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ. “‘Olúwa sì wí fún ọ pé Olúwa yóò kọ ilé kan fún ọ.
o na ũrĩa matũire meekaga kuuma rĩrĩa ndathuurire atongoria a gũtongoragia andũ akwa a Isiraeli. Ningĩ nĩngakũhe ũhurũko kuuma kũrĩ thũ ciaku ciothe. “‘Jehova egũkwĩra atĩ Jehova we mwene nĩwe ũkaarũgamia nyũmba yaku:
12 Nígbà tí ọjọ́ rẹ bá pé, tí ìwọ ó sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ, èmi yóò sì gbé irú-ọmọ rẹ lékè lẹ́yìn rẹ, èyí tí ó ti inú rẹ jáde wá, èmi yóò sì fi ìdí ìjọba rẹ kalẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa matukũ maku magaathira, ũhurũke hamwe na maithe maku, nĩngarahũra mbeũ yaku ĩcooke ithenya rĩaku, ĩrĩa ĩkoima mũthiimo waku wee mwene, na nĩngarũgamia ũthamaki wake.
13 Òun ó sì kọ́ ilé fún orúkọ mi, èmi yóò sì fi ìdí ìjọba rẹ kalẹ̀ láéláé.
Ũcio nĩwe ũgaaka nyũmba ĩtanĩtio na Rĩĩtwa Rĩakwa, na nĩngarũgamia gĩtĩ kĩa ũnene wake nginya tene.
14 Èmi ó máa ṣe baba fún un, òun yóò sì máa jẹ́ ọmọ mi. Bí òun bá dẹ́ṣẹ̀, èmi yóò sì fi ọ̀pá ènìyàn nà án, àti ìnà àwọn ọmọ ènìyàn.
Nĩngatuĩka ithe, nake atuĩke mũrũ wakwa. Hĩndĩ ĩrĩa ageeka ũũru, ngaamũherithia na rũthanju rwa andũ, na ahũũrwo mahũũra nĩ andũ.
15 Ṣùgbọ́n àánú mi kì yóò yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí èmi ti mú un kúrò lọ́dọ̀ Saulu, tí èmi ti mú kúrò níwájú rẹ.
No rĩrĩ, wendo wakwa ndũrĩ hĩndĩ ũkeeherio kũrĩ we, ta ũrĩa ndaaweheririe harĩ Saũlũ, ũrĩa ndeheririe mbere yaku.
16 A ó sì fi ìdílé rẹ àti ìjọba rẹ múlẹ̀ níwájú rẹ títí láé, a ó sì fi ìdí ìtẹ́ rẹ múlẹ̀ títí láé.’”
Nyũmba yaku na ũthamaki waku igũtũũra mbere yakwa nginya tene; o nakĩo gĩtĩ gĩaku kĩa ũnene gĩgũtũũra kĩrĩ kĩrũmu wega nginya tene.’”
17 Gẹ́gẹ́ bí gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, àti gẹ́gẹ́ bí gbogbo ìran yìí, bẹ́ẹ̀ ni Natani sì sọ fún Dafidi.
Nake Nathani akĩĩra Daudi ciugo ciothe cia ũguũrio ũcio.
18 Dafidi ọba sì wọlé lọ, ó sì dúró níwájú Olúwa, ó sì wí pé, “Olúwa Olódùmarè, ta ni èmi, àti kí sì ni ìdílé mi, tí ìwọ fi mú mi di ìsinsin yìí?
Nake Mũthamaki Daudi agĩtoonya, agĩikara thĩ mbere ya Jehova, akiuga atĩrĩ: “Niĩ ndĩkĩrĩ ũ, Wee Mwathani Jehova, nayo nyũmba yakwa-rĩ, ĩkĩrĩ kĩ, atĩ nĩkĩo ũnginyĩtie nginya haha?
19 Nǹkan kékeré ni èyí sá à jásí lójú rẹ, Olúwa Olódùmarè; ìwọ sì ti sọ nípa ìdílé ìránṣẹ́ rẹ pẹ̀lú ní ti àkókò tí o jìnnà. Èyí ha ṣe ìwà ènìyàn bí, Olúwa Olódùmarè?
Na rĩrĩ, Wee Mwathani Jehova, wonete ũndũ ũcio ta ũrĩ mũnini maitho-inĩ maku, nawe ũgacooka kwaria ũhoro wa matukũ marĩa magooka makoniĩ nyũmba ya ndungata yaku. Ningĩ Wee Mwathani Jehova ĩno nĩyo njĩra yaku ĩrĩa waragĩria andũ nayo?
20 “Àti kín ní ó tún kù tí Dafidi ìbá tún máa wí fún ọ? Ìwọ, Olúwa Olódùmarè mọ̀ ìránṣẹ́ rẹ.
“Nĩ atĩa ũngĩ Daudi angĩkwĩra? Nĩgũkorwo Wee Mwathani Jehova, nĩũĩ ndungata yaku.
21 Nítorí ọ̀rọ̀ rẹ, àti gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn rẹ, ni ìwọ ṣe ṣe gbogbo nǹkan ńlá wọ̀nyí, kí ìránṣẹ́ rẹ lè mọ̀.
Nĩ ũndũ wa kiugo gĩaku, na kũringana na wendo waku, nĩwĩkĩte ũndũ ũyũ mũnene ũguo, na ũkaũmenyithia ndungata yaku.
22 “Ìwọ sì tóbi, Olúwa Olódùmarè! Kò sì sí ẹni tí ó dàbí rẹ, kò sì sí Ọlọ́run kan lẹ́yìn rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí àwa fi etí wá gbọ́.
“Wee Mwathani Jehova, kaĩ ũkĩrĩ mũnene-ĩ! Gũtirĩ ũngĩ tawe, na gũtirĩ Ngai ũngĩ tiga wee, o ta ũrĩa tũiguĩte na matũ maitũ.
23 Orílẹ̀-èdè kan wo ni ó sì ń bẹ ní ayé tí ó dàbí àwọn ènìyàn rẹ, àní Israẹli, àwọn tí Ọlọ́run lọ rà padà láti sọ wọ́n di ènìyàn rẹ̀, àti láti sọ wọ́n ní orúkọ, àti láti ṣe nǹkan ńlá fún un yín, àti nǹkan ìyanu fún ilé rẹ̀, níwájú àwọn ènìyàn rẹ, tí ìwọ ti rà padà fún ara rẹ láti Ejibiti wá, àní àwọn orílẹ̀-èdè àti àwọn òrìṣà wọn.
Na nũũ ũhaana ta andũ aku a Isiraeli, rũrĩrĩ rũmwe gũkũ thĩ rũrĩa Ngai waruo aakũũrire rũtuĩke andũ ake, nĩgeetha wĩgĩĩre igweta, na wĩke maũndũ manene ma magegania na ma gwĩtigĩrwo, na ũndũ wa kũingata ndũrĩrĩ na ngai ciao ciehere mbere ya andũ aku, arĩa wakũũrire kuuma bũrũri wa Misiri?
24 Ìwọ sì fi ìdí àwọn ènìyàn rẹ, àní Israẹli kalẹ̀ fún ara rẹ láti sọ wọ́n di ènìyàn rẹ títí láé; ìwọ Olúwa sì wá di Ọlọ́run fún wọn.
Wee nĩũrũgamĩtie andũ aku a Isiraeli matuĩke andũ aku nginya tene, nawe, Wee Jehova nĩũtuĩkĩte Ngai wao.
25 “Ǹjẹ́, Olúwa Ọlọ́run, jẹ́ kí ọ̀rọ̀ náà tí ìwọ sọ ní ti ìránṣẹ́ rẹ, àti ní ti ìdílé rẹ̀, kí ó dúró títí láé, kí ó sí ṣe bí ìwọ ti wí.
“Na rĩrĩ, Jehova Ngai, tũma kĩĩranĩro kĩrĩa wĩranĩire gĩkoniĩ ndungata yaku na nyũmba yake kĩrũme nginya tene. Na wĩke o ta ũguo wĩranĩire,
26 Jẹ́ kí orúkọ rẹ ó ga títí láé, pé, ‘Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ọlọ́run lórí Israẹli!’ Sì jẹ́ kí a fi ìdílé Dafidi ìránṣẹ́ rẹ múlẹ̀ níwájú rẹ.
nĩgeetha rĩĩtwa rĩaku rĩnenehe nginya tene. Ningĩ andũ nĩmakoiga atĩrĩ, ‘Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩwe Ngai wa Isiraeli!’ Nayo nyũmba ya ndungata yaku Daudi nĩĩkehaanda mbere yaku.
27 “Nítorí pé ìwọ, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli ti sọ létí ìránṣẹ́ rẹ, pé, ‘Èmí ó kọ́ ilé kan fún ọ.’ Nítorí náà ni ìránṣẹ́ rẹ sì ṣe ní i lọ́kàn rẹ̀ láti gbàdúrà yìí sí ọ.
“Wee Jehova Mwene-Hinya-Wothe, Ngai wa Isiraeli, nĩũguũrĩirie ndungata yaku ũndũ ũyũ, ũkoiga atĩrĩ, ‘Nĩngagwakĩra nyũmba.’ Nĩ ũndũ ũcio ndungata yaku nĩĩgĩĩte na ũmĩrĩru wa kũhooya ihooya rĩrĩ.
28 Ǹjẹ́, Olúwa Olódùmarè, ìwọ ni Ọlọ́run náà, àwọn ọ̀rọ̀ rẹ sì jásí òtítọ́, ìwọ sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ nǹkan rere yìí fún ìránṣẹ́ rẹ.
Wee Mwathani Jehova, Wee nĩwe Ngai! Ciugo ciaku nĩciakwĩhokwo, na nĩwĩrĩire ndungata yaku maũndũ macio mega.
29 Ǹjẹ́, jẹ́ kí ó wù ọ́ láti bùkún ìdílé ìránṣẹ́ rẹ, kí ó wà títí láé níwájú rẹ, nítorí ìwọ, Olúwa Olódùmarè, ni ó ti sọ ọ́: sì jẹ́ kí ìbùkún wà ní ìdílé ìránṣẹ́ rẹ títí láé, nípasẹ̀ ìbùkún rẹ.”
Rĩu nĩwonete kwagĩrĩire ũrathime nyũmba ya ndungata yaku, nĩgeetha ĩtũũre mbere yaku nginya tene maitho-inĩ maku; nĩgũkorwo Wee Mwathani Jehova nĩwe warĩtie, na nĩ ũndũ wa kĩrathimo gĩaku, nyũmba ya ndungata yaku ĩtũũre ĩraathimĩtwo nginya tene.”

< 2 Samuel 7 >