< 2 Samuel 6 >

1 Dafidi sì tún kó gbogbo àwọn akọni ọkùnrin ní Israẹli jọ, wọ́n sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Na ka huihuia ano e Rawiri te hunga whiriwhiri katoa o Iharaira e toru tekau mano.
2 Dafidi sì dìde, ó sì lọ àti gbogbo àwọn ènìyàn tí ń bẹ́ lọ́dọ̀ rẹ́, láti Baalahi ní Juda wá, láti mú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run tí ibẹ̀ wá, èyí tí a ń pe orúkọ rẹ̀ ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí ó jókòó láàrín àwọn kérúbù.
A ka whakatika a Rawiri ratou ko tona nuinga katoa, haere ana i Paare o Hura, tikina ana i reira te aaka a Ihowa, e huaina nei ki te Ingoa, ara ki te ingoa o Ihowa o nga mano, e noho nei i waenganui o nga kerupima.
3 Wọ́n sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run náà gun kẹ̀kẹ́ tuntun kan, wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu wá, èyí tí ó wà ní Gibeah: Ussa àti Ahio, àwọn ọmọ Abinadabu sì ń dá kẹ̀kẹ́ tuntun náà.
Na ka whakanohoia e ratou te aaka a te Atua ki runga ki te kata hou, a mauria ana i te whare o Apinarapa i Kipea; a na Uha raua ko Ahio, na nga tama a Apinarapa, i arahi te kata hou.
4 Wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu jáde wá, tí ó wà ní Gibeah, pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, Ahio sì ń rìn níwájú àpótí ẹ̀rí náà.
Na kawea ana i te whare o Apinarapa i Kipea, me te haere tahi ano ratou ko te aaka a te Atua; i haere ano a Ahio i mua i te aaka.
5 Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì ṣiré níwájú Olúwa lára gbogbo onírúurú ohun èlò orin tí a fi igi arère ṣe àti lára ìlù haapu, ní ara tambori, sisitirumu àti lára kimbali.
Na ka takaro a Rawiri ratou ko te whare katoa o Iharaira ki te aroaro o Ihowa, me te whakatangi ano i a ratou mea katoa he kauri nei te rakau, i nga hapa, i nga hatere, i nga timipera, i nga koronete, i nga himipora.
6 Nígbà tí wọ́n dé sí ilẹ̀ ìpakà Nakoni, Ussa sì na ọwọ́ rẹ̀ sí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, ó sì dìímú, nítorí tí màlúù kọsẹ̀.
A ka tae ki te patunga witi a Nakono, ka totoro a Uha ki te aaka a te Atua, a puritia ana e ia; i paheke hoki nga kau.
7 Ìbínú Olúwa sì ru sí Ussa; Ọlọ́run sì pa á níbẹ̀ nítorí ìṣísẹ̀ rẹ̀; níbẹ̀ ni ó sì kù ní ẹ̀bá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.
Na ka mura te riri o Ihowa ki a Uha, a patua iho ia i reira e te Atua mo tona he, a mate ake i reira i te taha o te aaka a te Atua.
8 Inú Dafidi sì bàjẹ́ nítorí tí Olúwa gé Ussa kúrò, ó sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Peresi-Usa títí ó fi di òní yìí.
Na ka pouri a Rawiri mo ta Ihowa tukitukinga i a Uha; na huaina ana taua wahi e ia, ko Pereteuha; koia ano tena inaianei.
9 Dafidi sì bẹ̀rù Olúwa ní ọjọ́ náà, ó sì wí pé, “Àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò ti ṣe tọ̀ mí wá?”
Na ka wehi a Rawiri i a Ihowa i taua ra, ka mea, Ma te aha e tae ake ai te aaka a Ihowa ki ahau.
10 Dafidi kò sì fẹ́ mú àpótí ẹ̀rí Olúwa sọ́dọ̀ rẹ̀ sí ìlú Dafidi; ṣùgbọ́n Dafidi sì mú un yà sí ilé Obedi-Edomu ará Gitti.
Heoi kihai a Rawiri i pai ki te tango i te aaka a Ihowa ki a ia, ki te pa o Rawiri; na kawea ketia ana e Rawiri ki te whare o Opereeroma Kiti.
11 Àpótí ẹ̀rí Olúwa sì gbé ní ilé Obedi-Edomu ará Gitti ní oṣù mẹ́ta; Olúwa sì bùkún fún Obedi-Edomu, àti gbogbo ilé rẹ̀.
E toru nga marama i noho ai te aaka a Ihowa ki te whare o Opereeroma Kiti: a ka manaakitia e Ihowa a Opereeroma ratou ko tona whare katoa.
12 A sì rò fún Dafidi ọba pé, “Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí tí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.” Dafidi sì lọ, ó sì mú àpótí ẹ̀rí náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu wá sí ìlú Dafidi pẹ̀lú ayọ̀.
A ka korerotia te korero ki a Kingi Rawiri, Kua manaakitia e Ihowa te whare o Opereeroma me ana mea katoa, he whakaaro ki te aaka a te Atua. Na ka haere a Rawiri, a kawea ana e ia te aaka a te Atua, i te whare o Opereeroma ki runga, ki te pa o R awiri, me te koa ano ia.
13 Ó sì ṣe nígbà tí àwọn ènìyàn tí ó ru àpótí ẹ̀rí Olúwa bá sì ṣí ẹsẹ̀ mẹ́fà, òun a sì fi màlúù àti ẹran àbọ́pa rú ẹbọ.
A ka ono nga hikoinga i hokoi ai nga kaiamo i te aaka a Ihowa, na ka patua e ia etahi kau me tetahi mea momona.
14 Dafidi sì fi gbogbo agbára rẹ̀ jó níwájú Olúwa; Dafidi sì wọ efodu ọ̀gbọ̀.
Na ka whakapaua katoatia tona kaha e Rawiri ki te kanikani ki te aroaro o Ihowa: i whitikiria ano he epora rinena ki a Rawiri.
15 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa gòkè wá, pẹ̀lú ìhó ayọ̀, àti pẹ̀lú ìró ìpè.
Heoi ka kawea te aaka a Ihowa e Rawiri ratou ko te whare katoa o Iharaira, me te hamama ano ratou, me te tangi ano te tetere.
16 Bí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wọ ìlú Dafidi wá; Mikali ọmọbìnrin Saulu sì wo láti ojú fèrèsé, ó sì rí Dafidi ọba ń fò sókè ó sì ń jó níwájú Olúwa; òun sì kẹ́gàn rẹ̀ ní ọkàn rẹ̀.
A, i te taenga o te aaka a Ihowa ki te pa o Rawiri, na ka titiro a Mikara, tamahine a Haora na te matapihi, a ka kite i a Kingi Rawiri e tupekepeke ana, e kanikani ana i te aroaro o Ihowa; a whakahawea ana ia ki a ia i roto i tona ngakau.
17 Wọ́n sì mú àpótí ẹ̀rí Olúwa náà wá, wọ́n sì gbé e kalẹ̀ sípò rẹ̀ láàrín àgọ́ náà tí Dafidi pa fún un. Dafidi sì rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ níwájú Olúwa.
Na ka kawea e ratou te aaka a Ihowa, a whakaturia ana ki tona wahi, ki waenganui o te tapenakara i whakaarahia e Rawiri mona: na ka tapaea e Rawiri etahi tahunga tinana ki te aroaro o Ihowa, me etahi whakahere mo te pai.
18 Dafidi sì parí ìṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ náà, ó sì súre fún àwọn ènìyàn náà ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
A, no ka mutu ta Rawiri tapae i nga tahunga tinana, i nga whakahere mo te pai, ka manaakitia e ia te iwi i runga i te ingoa o Ihowa o nga mano.
19 Ó sì pín fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, àní fún gbogbo ọ̀pọ̀ ènìyàn Israẹli, àti ọkùnrin àti obìnrin; fún olúkúlùkù ìṣù àkàrà kan àti ekìrí ẹran kan, àti àkàrà díndín kan. Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì túká lọ, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀.
I tuwhaina ano e ia ma te iwi katoa, ma te huihui katoa o Iharaira, ma te tane, ma te wahine, kotahi keke taro ma tenei, ma tenei, me tetahi wahi kikokiko, me tetahi keke karepe maroke. Na haere ana te iwi katoa ki tona whare, ki tona whare.
20 Dafidi sì yípadà láti súre fún àwọn ará ilé rẹ̀, Mikali ọmọbìnrin Saulu sì jáde láti wá pàdé Dafidi, ó sì wí pé, “Báwo ni ọba Israẹli ṣe ṣe ara rẹ̀ lógo bẹ́ẹ̀ lónìí, tí ó bọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ lónìí lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn lásán tí ń bọ́ra rẹ̀ sílẹ̀.”
Katahi a Rawiri ka hoki ki te manaaki i tona whare. A ka puta a Mikara, tamahine a Haora ki te whakatau i a Rawiri, a ka mea, Ano te kororia o te kingi o Iharaira inaianei, i whakakite kirikau nei i a ia inakuanei ki nga kanohi o nga pononga wah ine a ana tangata, pera i tetahi o te hunga wairangi e whakakite nui ana i a ia!
21 Dafidi sì wí fún Mikali pé, “Níwájú Olúwa ni, ẹni tí ó yàn mí fẹ́ ju baba rẹ lọ, àti ju gbogbo ìdílé rẹ lọ, láti fi èmi ṣe olórí àwọn ènìyàn Olúwa, àní lórí Israẹli, èmi ó sì súre níwájú Olúwa.
Na ka mea a Rawiri ki a Mikara, I te aroaro ra o Ihowa, i whiriwhiri nei i ahau, i kape nei i tou papa, me tona whare katoa, i whakarite hoki a ahau hei rangatira mo te iwi a Ihowa, mo Iharaira; koia ahau ka takaro ki te aroaro o Ihowa.
22 Èmi ó sì tún rẹ ara mi sílẹ̀ jú bẹ́ẹ̀ lọ, èmi ó sì ṣe aláìníyìn lójú ara mi, àti lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin náà ti ìwọ wí, lọ́dọ̀ wọn náà ni èmi ó sì ní ògo.”
Na ka nui atu ano i tenei toku wairangi, a ka iti iho ahau ki taku titiro; ko nga pononga wahine ia i kiia mai na e koe, ka whakahonoretia ahau e ratou.
23 Mikali ọmọbìnrin Saulu kò sì bí ọmọ, títí o fi di ọjọ́ ikú rẹ̀ nítorí tí ó sọ̀rọ̀-òdì yìí sí Dafidi.
Na kahore he tamariki a Mikara tamahine a Haora a taea noatia te ra i mate ai ia.

< 2 Samuel 6 >