< 2 Samuel 6 >

1 Dafidi sì tún kó gbogbo àwọn akọni ọkùnrin ní Israẹli jọ, wọ́n sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
O rĩngĩ, Daudi agĩcookanĩrĩria andũ arĩa maarĩ njamba a Isiraeli othe, nao maarĩ ngiri mĩrongo ĩtatũ.
2 Dafidi sì dìde, ó sì lọ àti gbogbo àwọn ènìyàn tí ń bẹ́ lọ́dọ̀ rẹ́, láti Baalahi ní Juda wá, láti mú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run tí ibẹ̀ wá, èyí tí a ń pe orúkọ rẹ̀ ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí ó jókòó láàrín àwọn kérúbù.
Daudi arĩ hamwe na andũ acio ake othe magĩthiĩ moimĩte Baala kũu Juda makambatie ithandũkũ rĩa Ngai marĩrute kuo, ithandũkũ rĩrĩa rĩĩtanĩtio na Rĩĩtwa Rĩake, naguo ũguo nĩ ta kuuga Rĩĩtwa rĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe, ũrĩa ũikaraga gatagatĩ ka makerubi marĩa marĩ igũrũ rĩa ithandũkũ rĩu.
3 Wọ́n sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run náà gun kẹ̀kẹ́ tuntun kan, wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu wá, èyí tí ó wà ní Gibeah: Ussa àti Ahio, àwọn ọmọ Abinadabu sì ń dá kẹ̀kẹ́ tuntun náà.
Nao makĩigĩrĩra ithandũkũ rĩa Ngai ngaari-inĩ njerũ ya ngʼombe, makĩrĩruta nyũmba ya Abinadabu, ĩrĩa yarĩ kĩrĩma-inĩ. Nao Uza na Ahio, ariũ a Abinadabu, nĩo maatongoretie ngaari ĩyo njerũ
4 Wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu jáde wá, tí ó wà ní Gibeah, pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, Ahio sì ń rìn níwájú àpótí ẹ̀rí náà.
ĩrĩ na ithandũkũ rĩu rĩa Ngai igũrũ rĩayo, nake Ahio nĩwe warĩtongoretie.
5 Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì ṣiré níwájú Olúwa lára gbogbo onírúurú ohun èlò orin tí a fi igi arère ṣe àti lára ìlù haapu, ní ara tambori, sisitirumu àti lára kimbali.
Nake Daudi na nyũmba yothe ya Isiraeli maarũũhagia na hinya wao wothe marĩ mbere ya Jehova, makaina nyĩmbo na inanda cia kĩnũbi, na inanda cia mũgeeto, na tũhembe, na njingiri na thaani iria ihũũrithanagio ikagamba.
6 Nígbà tí wọ́n dé sí ilẹ̀ ìpakà Nakoni, Ussa sì na ọwọ́ rẹ̀ sí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, ó sì dìímú, nítorí tí màlúù kọsẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa maakinyire kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kĩa Nakoni, ndegwa ikĩhĩngwo, Uza agĩtambũrũkia guoko akanyiitĩrĩra ithandũkũ rĩa Ngai tondũ ndegwa nĩ ciahĩngĩtwo.
7 Ìbínú Olúwa sì ru sí Ussa; Ọlọ́run sì pa á níbẹ̀ nítorí ìṣísẹ̀ rẹ̀; níbẹ̀ ni ó sì kù ní ẹ̀bá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.
Namo marakara ma Jehova magĩakanĩra Uza tondũ wa gĩĩko kĩu gĩa kwaga gĩtĩĩo; Nĩ ũndũ ũcio Ngai akĩmũgũtha akĩgũa, agĩkuĩra hakuhĩ na ithandũkũ rĩa Ngai.
8 Inú Dafidi sì bàjẹ́ nítorí tí Olúwa gé Ussa kúrò, ó sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Peresi-Usa títí ó fi di òní yìí.
Nake Daudi akĩrakara tondũ mangʼũrĩ ma Jehova nĩmookĩrĩire Uza, na nginya ũmũthĩ handũ hau hetagwo Perezu-Uza.
9 Dafidi sì bẹ̀rù Olúwa ní ọjọ́ náà, ó sì wí pé, “Àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò ti ṣe tọ̀ mí wá?”
Nake Daudi agĩĩtigĩra Jehova mũthenya ũcio, akĩũria atĩrĩ, “Ngaahota atĩa kũinũkia ithandũkũ rĩĩrĩ rĩa Jehova?”
10 Dafidi kò sì fẹ́ mú àpótí ẹ̀rí Olúwa sọ́dọ̀ rẹ̀ sí ìlú Dafidi; ṣùgbọ́n Dafidi sì mú un yà sí ilé Obedi-Edomu ará Gitti.
Nake ndetĩkĩrire gũtwara ithandũkũ rĩu rĩa Jehova kũu aatũire, itũũra-inĩ inene rĩa Daudi. Handũ ha ũguo, aarĩtwarire kwa Obedi-Edomu ũrĩa Mũgiiti.
11 Àpótí ẹ̀rí Olúwa sì gbé ní ilé Obedi-Edomu ará Gitti ní oṣù mẹ́ta; Olúwa sì bùkún fún Obedi-Edomu, àti gbogbo ilé rẹ̀.
Ithandũkũ rĩu rĩa Jehova rĩgĩikara nyũmba-inĩ ya Obedi-Edomu ũrĩa Mũgiiti mĩeri ĩtatũ, nake Jehova akĩmũrathima hamwe na nyũmba yake yothe.
12 A sì rò fún Dafidi ọba pé, “Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí tí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.” Dafidi sì lọ, ó sì mú àpótí ẹ̀rí náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu wá sí ìlú Dafidi pẹ̀lú ayọ̀.
Na rĩrĩ, Mũthamaki Daudi akĩĩrwo atĩrĩ, “Jehova nĩarathimĩte nyũmba ya Obedi-Edomu na kĩrĩa gĩothe arĩ nakĩo, tondũ wa ithandũkũ rĩa Ngai.” Nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩikũrũka akĩruta ithandũkũ rĩa Ngai kuuma nyũmba ya Obedi-Edomu akĩrĩtwara itũũra inene rĩa Daudi akenete.
13 Ó sì ṣe nígbà tí àwọn ènìyàn tí ó ru àpótí ẹ̀rí Olúwa bá sì ṣí ẹsẹ̀ mẹ́fà, òun a sì fi màlúù àti ẹran àbọ́pa rú ẹbọ.
Na rĩrĩ, andũ acio maakuuĩte ithandũkũ rĩa Jehova maakinya makinya matandatũ-rĩ, Daudi akĩruta igongona rĩa ndegwa na gacaũ kanoru.
14 Dafidi sì fi gbogbo agbára rẹ̀ jó níwájú Olúwa; Dafidi sì wọ efodu ọ̀gbọ̀.
Daudi akĩina arĩ mbere ya Jehova na hinya wake wothe, ehumbĩte ebodi ya gatani;
15 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa gòkè wá, pẹ̀lú ìhó ayọ̀, àti pẹ̀lú ìró ìpè.
nĩ ũndũ ũcio Daudi na nyũmba yothe ya Isiraeli makĩambatia ithandũkũ rĩa Jehova makĩanagĩrĩra na makĩhuhaga tũrumbeta.
16 Bí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wọ ìlú Dafidi wá; Mikali ọmọbìnrin Saulu sì wo láti ojú fèrèsé, ó sì rí Dafidi ọba ń fò sókè ó sì ń jó níwájú Olúwa; òun sì kẹ́gàn rẹ̀ ní ọkàn rẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa ithandũkũ rĩa kĩrĩkanĩro kĩa Jehova rĩatoonyaga itũũra inene rĩa Daudi-rĩ, Mikali mwarĩ wa Saũlũ agĩcũthĩrĩria arĩ ndirica-inĩ. Na rĩrĩa onire Mũthamaki Daudi akĩrũga-rũga akĩinaga mbere ya Jehova, akĩmũnyarara ngoro-inĩ yake.
17 Wọ́n sì mú àpótí ẹ̀rí Olúwa náà wá, wọ́n sì gbé e kalẹ̀ sípò rẹ̀ láàrín àgọ́ náà tí Dafidi pa fún un. Dafidi sì rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ níwájú Olúwa.
Nao makĩrehe ithandũkũ rĩa Jehova na makĩrĩiga handũ harĩo thĩinĩ wa hema ĩrĩa Daudi aambĩte nĩ ũndũ warĩo, nake Daudi akĩruta maruta ma njino na ma ũiguano mbere ya Jehova.
18 Dafidi sì parí ìṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ náà, ó sì súre fún àwọn ènìyàn náà ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Aarĩkia kũruta magongona ma njino, na maruta ma ũiguano-rĩ, akĩrathima andũ thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe.
19 Ó sì pín fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, àní fún gbogbo ọ̀pọ̀ ènìyàn Israẹli, àti ọkùnrin àti obìnrin; fún olúkúlùkù ìṣù àkàrà kan àti ekìrí ẹran kan, àti àkàrà díndín kan. Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì túká lọ, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀.
Ningĩ akĩheana mũgate, na gĩkũmba gĩa thabibũ, na gĩcunjĩ kĩa nyama kũrĩ mũndũ o wothe warĩ gĩkundi-inĩ kĩu gĩa Isiraeli, arũme na andũ-a-nja o ũndũ ũmwe. Nao andũ othe makĩinũka mĩciĩ kwao.
20 Dafidi sì yípadà láti súre fún àwọn ará ilé rẹ̀, Mikali ọmọbìnrin Saulu sì jáde láti wá pàdé Dafidi, ó sì wí pé, “Báwo ni ọba Israẹli ṣe ṣe ara rẹ̀ lógo bẹ́ẹ̀ lónìí, tí ó bọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ lónìí lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn lásán tí ń bọ́ra rẹ̀ sílẹ̀.”
Hĩndĩ ĩrĩa Daudi aacookire mũciĩ akarathime andũ a nyũmba yake-rĩ, Mikali mwarĩ wa Saũlũ agĩũka kũmũtũnga, akiuga atĩrĩ, “Kaĩ mũthamaki wa Isiraeli nĩakĩĩonanĩtie ũmũthĩ-ĩ, agakĩruta nguo mbere ya ngombo cia airĩtu cia ndungata ciake, o ta ũrĩa mũndũ ũtarĩ thoni angĩĩka!”
21 Dafidi sì wí fún Mikali pé, “Níwájú Olúwa ni, ẹni tí ó yàn mí fẹ́ ju baba rẹ lọ, àti ju gbogbo ìdílé rẹ lọ, láti fi èmi ṣe olórí àwọn ènìyàn Olúwa, àní lórí Israẹli, èmi ó sì súre níwájú Olúwa.
Daudi akĩĩra Mikali atĩrĩ, “Nyuma mbere ya Jehova ũrĩa wathuurire niĩ handũ ha thoguo kana mũndũ o na ũmwe wa nyũmba yake, hĩndĩ ĩrĩa aathuurire nduĩke mũthamaki wa gũthamakĩra andũ a Jehova, nĩo andũ a Isiraeli, na nĩ ũndũ ũcio no nginya nyine ndĩ mbere ya Jehova.
22 Èmi ó sì tún rẹ ara mi sílẹ̀ jú bẹ́ẹ̀ lọ, èmi ó sì ṣe aláìníyìn lójú ara mi, àti lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin náà ti ìwọ wí, lọ́dọ̀ wọn náà ni èmi ó sì ní ògo.”
O na nĩ ngũkĩrĩrĩria kwĩyagithia gĩtĩĩo gũkĩra ũũ, na nĩngwĩnyiihia maitho-inĩ makwa. No rĩrĩ, ndungata icio cia airĩtu wagweta-rĩ, niĩ nĩgũtĩĩo ngũtĩĩo nĩcio.”
23 Mikali ọmọbìnrin Saulu kò sì bí ọmọ, títí o fi di ọjọ́ ikú rẹ̀ nítorí tí ó sọ̀rọ̀-òdì yìí sí Dafidi.
Nake Mikali mwarĩ wa Saũlũ ndaagĩire ciana nginya mũthenya ũrĩa aakuire.

< 2 Samuel 6 >