< 2 Samuel 6 >

1 Dafidi sì tún kó gbogbo àwọn akọni ọkùnrin ní Israẹli jọ, wọ́n sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Da: ibidi da bu Isala: ili dadi gagui dunu noga: i amo gilisimusa: bu wele sia: i. Ilia idi da dunu 30,000 agoane.
2 Dafidi sì dìde, ó sì lọ àti gbogbo àwọn ènìyàn tí ń bẹ́ lọ́dọ̀ rẹ́, láti Baalahi ní Juda wá, láti mú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run tí ibẹ̀ wá, èyí tí a ń pe orúkọ rẹ̀ ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí ó jókòó láàrín àwọn kérúbù.
E da ili bisili, Ba: ila agolo, Yuda soge ganodini, amoga oule asi. Ilia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili (amoga da Hina Gode Bagadedafa Ea Dio gala. Ea Fisu da `selabimi’ amoga gadodili ba: sa, ) amo bu gaguli misa: ne asi.
3 Wọ́n sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run náà gun kẹ̀kẹ́ tuntun kan, wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu wá, èyí tí ó wà ní Gibeah: Ussa àti Ahio, àwọn ọmọ Abinadabu sì ń dá kẹ̀kẹ́ tuntun náà.
Ilia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo Abinada: be ea diasu agolo da: iya galu amoga lale, gaguli fula ahoasu gaheabolo bulamagauga hiougima: ne, amo da: iya ligisi. Asa amola Ahaiou (Abinada: be egefela) da amo gaguli fula ahoasu ea ahoabe amo adonana ahoanu.
4 Wọ́n sì mú un láti ilé Abinadabu jáde wá, tí ó wà ní Gibeah, pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, Ahio sì ń rìn níwájú àpótí ẹ̀rí náà.
Ahaiou da bisili ahoanu.
5 Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì ṣiré níwájú Olúwa lára gbogbo onírúurú ohun èlò orin tí a fi igi arère ṣe àti lára ìlù haapu, ní ara tambori, sisitirumu àti lára kimbali.
Da: ibidi amola Isala: ili dunu huluane da Hina Gode Ea nodoma: ne, gogosa: amola gesami hea: sa ahoanebe ba: i. Ilia da sani baidama, ilibu, gesolo dabi, amola gisanidulu amo dudududaha ahoasu.
6 Nígbà tí wọ́n dé sí ilẹ̀ ìpakà Nakoni, Ussa sì na ọwọ́ rẹ̀ sí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, ó sì dìímú, nítorí tí màlúù kọsẹ̀.
Ilia da Na: igone widi dadabisu sogebi doaga: loba, bulamagau da didigaboi. Asa da ea lobo ligiagale, Gousa: su Sema Gagili mae sa: ima: ne banene gagui.
7 Ìbínú Olúwa sì ru sí Ussa; Ọlọ́run sì pa á níbẹ̀ nítorí ìṣísẹ̀ rẹ̀; níbẹ̀ ni ó sì kù ní ẹ̀bá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.
Amogaluwane hedolo, Hina Gode da Asama ougi. E da Asa fane legei. Bai e da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amoma nodoiba: le, e da hame beda: i. Asa da amogawi Gousa: su Sema Gagili dafulili bogoi dagoi.
8 Inú Dafidi sì bàjẹ́ nítorí tí Olúwa gé Ussa kúrò, ó sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Peresi-Usa títí ó fi di òní yìí.
Amaiba: le, amogainini amo sogebi ea dio da `Bilese Asa’ dialu. (Amo ea dawa: loma: ne da “Asa ea se Iasu”). Hina Gode da ougili Asa medole legeiba: le, Da: ibidi amola da ougi bagade ba: i.
9 Dafidi sì bẹ̀rù Olúwa ní ọjọ́ náà, ó sì wí pé, “Àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò ti ṣe tọ̀ mí wá?”
Amalalu, Da: ibidi da Hina Godeba: le beda: i galu. E da amane sia: i, “Na da habodane Gousa: su Sema Gagili amo bu gaguli masa: bela: ?”
10 Dafidi kò sì fẹ́ mú àpótí ẹ̀rí Olúwa sọ́dọ̀ rẹ̀ sí ìlú Dafidi; ṣùgbọ́n Dafidi sì mú un yà sí ilé Obedi-Edomu ará Gitti.
Amaiba: le, e da amo Yelusaleme moilai bai bagadega hame gaguli masunu dawa: i. E da logo yolesili, dunu ea dio amo Oubede Idome (Ga: de moilai bai bagade dunu) amo ea diasuga Gousa: su Sema Gagili gaguli asi.
11 Àpótí ẹ̀rí Olúwa sì gbé ní ilé Obedi-Edomu ará Gitti ní oṣù mẹ́ta; Olúwa sì bùkún fún Obedi-Edomu, àti gbogbo ilé rẹ̀.
Gousa: su Sema Gagili amo da amogawi oubi udiana dialu. Amola Hina Gode da Oubede Idome amola ea sosogo fi ilima hahawane dogolegele hamoi.
12 A sì rò fún Dafidi ọba pé, “Olúwa ti bùkún fún ilé Obedi-Edomu, àti gbogbo èyí tí í ṣe tirẹ̀, nítorí àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run.” Dafidi sì lọ, ó sì mú àpótí ẹ̀rí náà gòkè láti ilé Obedi-Edomu wá sí ìlú Dafidi pẹ̀lú ayọ̀.
Hina Da: ibidi da Oubede Idome amola ea sosogo fi da Gousa: su Sema Gagili ouligibiba: le, Hina Gode Ea ilima amola ilia gagui amoma hahawane dogolegele hamosu, amo nabi. Amaiba: le, e da gilisisu bagade hamone, Gousa: su Sema Gagili amo Oubede Idome ea diasuga lale, bu Yelusaleme moilai bai bagadega gaguli asi.
13 Ó sì ṣe nígbà tí àwọn ènìyàn tí ó ru àpótí ẹ̀rí Olúwa bá sì ṣí ẹsẹ̀ mẹ́fà, òun a sì fi màlúù àti ẹran àbọ́pa rú ẹbọ.
Da: ibidi da dunu amo da Gousa: su Sema Gagili gaguli ahoasu, ilia da emo gafeyale osa: le gale aligima: ne sia: i. Amalalu, e da bulamagau gawali amola sefena bulamagau mano Godema gobele sali.
14 Dafidi sì fi gbogbo agbára rẹ̀ jó níwájú Olúwa; Dafidi sì wọ efodu ọ̀gbọ̀.
Da: ibidi da ahea: iai abula buluale gale banene idiniginisi. E da Hina Godema nodone, ea gasa defele bagadewane giginisa lai.
15 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti gbogbo ilé Israẹli sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa gòkè wá, pẹ̀lú ìhó ayọ̀, àti pẹ̀lú ìró ìpè.
Amola e amola Isala: ili dunu huluane ilia da nodone wele sisa: ne amola `dalabede’ fulabolalu, ilia da Gousa: su Sema Gagili Yelusaleme moilai bai bagadega gaguli asi.
16 Bí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wọ ìlú Dafidi wá; Mikali ọmọbìnrin Saulu sì wo láti ojú fèrèsé, ó sì rí Dafidi ọba ń fò sókè ó sì ń jó níwájú Olúwa; òun sì kẹ́gàn rẹ̀ ní ọkàn rẹ̀.
Ilia da Gousa: su Sema Gagili amo Yelusaleme ganodini gaguli ahoanoba, Solo idiwi Maiga: le da fo misa: ne agenesi amoga gadili ba: lu, hina bagade Da: ibidi giginisa lalebe amola soagala: ga gadolalebe ba: beba: le, e higale ba: i.
17 Wọ́n sì mú àpótí ẹ̀rí Olúwa náà wá, wọ́n sì gbé e kalẹ̀ sípò rẹ̀ láàrín àgọ́ náà tí Dafidi pa fún un. Dafidi sì rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ níwájú Olúwa.
Ilia da Gousa: su Sema Gagili amo gaguli misini, abula diasu amo Da: ibidi ea hamoi, amo ganodini ligisi. Amalalu, Da: ibidi da Hina Godema gobele salasu amola Hahawane Gilisili olofole Iasu amo hamoi.
18 Dafidi sì parí ìṣe ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ náà, ó sì súre fún àwọn ènìyàn náà ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
E da gobele salasu hamoi dagoloba, e da Hina Gode Bagadedafa Ea Dioba: le, ea fi dunuma hahawane dogolegele sia: i.
19 Ó sì pín fún gbogbo àwọn ènìyàn náà, àní fún gbogbo ọ̀pọ̀ ènìyàn Israẹli, àti ọkùnrin àti obìnrin; fún olúkúlùkù ìṣù àkàrà kan àti ekìrí ẹran kan, àti àkàrà díndín kan. Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì túká lọ, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀.
Amola e da ili huluane ilima ha: i manu sagoi. E da Isala: ili dunu amola uda huluane afae afae ilima agi ga: gi afae amola hu damui gobele gala: i afae amola fofogai waini fage mogili ilima sagoi. Amalalu, dunu huluane da ilia diasuga buhagi.
20 Dafidi sì yípadà láti súre fún àwọn ará ilé rẹ̀, Mikali ọmọbìnrin Saulu sì jáde láti wá pàdé Dafidi, ó sì wí pé, “Báwo ni ọba Israẹli ṣe ṣe ara rẹ̀ lógo bẹ́ẹ̀ lónìí, tí ó bọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ lónìí lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn lásán tí ń bọ́ra rẹ̀ sílẹ̀.”
Amogalu fa: no, Da: ibidi da hi diasu ea sosogo fi gousa: musa: ahoanoba, Maiga: le da gadili e ba: la misi. E amane sia: i, “Isala: ili hina bagade da wali eso ea dio gaguia gadoma: ne hidale bagade hamoi! E da gagaoui dunu agoane, ea ouligisu dunu ilia hawa: hamosu a: fini ba: ma: ne, ea abula gisa: le fasi!”
21 Dafidi sì wí fún Mikali pé, “Níwájú Olúwa ni, ẹni tí ó yàn mí fẹ́ ju baba rẹ lọ, àti ju gbogbo ìdílé rẹ lọ, láti fi èmi ṣe olórí àwọn ènìyàn Olúwa, àní lórí Israẹli, èmi ó sì súre níwájú Olúwa.
Da: ibidi da bu adole i, “Na da Hina Godema nodone gigini. Bai E da dia ada, ea sosogo amo fisili, na Ea fi Isala: ili ouligima: ne ilegei dagoi. Amola na da mae yolesili, Hina Godema nodoma: ne bu gigininimu.
22 Èmi ó sì tún rẹ ara mi sílẹ̀ jú bẹ́ẹ̀ lọ, èmi ó sì ṣe aláìníyìn lójú ara mi, àti lójú àwọn ìránṣẹ́bìnrin náà ti ìwọ wí, lọ́dọ̀ wọn náà ni èmi ó sì ní ògo.”
Amola bu gogosiasu ba: mu. Di da na da hamedei dunu dawa: mu. Be amo ouligisu dunu ilia hawa: hamosu a: fini da na nodone ba: mu.”
23 Mikali ọmọbìnrin Saulu kò sì bí ọmọ, títí o fi di ọjọ́ ikú rẹ̀ nítorí tí ó sọ̀rọ̀-òdì yìí sí Dafidi.
Solo idiwi Maiga: le da gebewane aligime esalu.

< 2 Samuel 6 >