< 2 Samuel 4 >
1 Nígbà tí ọmọ Saulu sì gbọ́ pé, Abneri kú ní Hebroni, ọwọ́ rẹ̀ sì rọ, gbogbo Israẹli sì rẹ̀wẹ̀sì.
Saulning oƣli Abnǝrning Ⱨebronda ɵlginini angliƣanda ⱪoli boxixip kǝtti, barliⱪ Israil dǝkkǝ-dükkigǝ qüxti.
2 Ọmọ Saulu sì ní ọkùnrin méjì tí í ṣe olórí ẹgbẹ́ ogun: a ń pe orúkọ ọ̀kan ní Baanah, àti orúkọ èkejì ní Rekabu, àwọn ọmọ Rimoni ará Beeroti ti àwọn ọmọ Benjamini (nítorí pé a sì ka Beeroti pẹ̀lú Benjamini).
Saulning oƣlining ⱪoxunining aldin yürǝr ⱪismida ikki sǝrdari bolup, birining ismi Baanaⱨ, yǝnǝ birining ismi Rǝkab idi. Ular Binyamin ⱪǝbilisidin bolƣan Bǝǝrotluⱪ Rimmonning oƣulliri idi (qünki Bǝǝrot Binyamin ⱪǝbilisigǝ tǝwǝ ⱨesablinatti;
3 Àwọn ará Beeroti sì ti sálọ sí Gittaimu, wọ́n sì ṣe àtìpó níbẹ̀ títí ó fi di ọjọ́ òní yìí.
lekin Bǝǝrotluⱪlar Gittaimƣa ⱪeqip berip u yǝrdǝ bu küngiqǝ musapirdǝk yaxawatidu).
4 (Jonatani ọmọ Saulu sì ti bí ọmọkùnrin kan tí ẹsẹ̀ rẹ̀ rọ, òun sì jẹ́ ọdún márùn-ún, nígbà tí ìròyìn dé ní ti Saulu àti Jonatani láti Jesreeli wá, olùtọ́ rẹ̀ sì gbé e, o sì sálọ, ó sì ṣe, bí ó sì ti ń yára láti sálọ, òun sì ṣubú, ó sì ya arọ. Orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Mefiboṣeti.)
Saulning oƣli Yonatanning bir oƣli bolup, puti aⱪsaⱪ idi. Saul bilǝn Yonatanning ɵlgǝnliki toƣruluⱪ hǝwǝr Yizrǝǝlgǝ yǝtkǝndǝ, u bǝx yaxⱪa kirgǝn idi. Inik anisi uni elip ⱪaqti; lekin xundaⱪ boldiki, u aldirap yügürgǝqkǝ, bala qüxup ketip, aⱪsaⱪ bolup ⱪalƣanidi. Uning ismi Mǝfiboxǝt idi.
5 Àwọn ọmọ Rimoni, ará Beeroti, Rekabu àti Baanah sì lọ wọ́n sì wá síh ilé Iṣboṣeti ní ọ̀sán gangan, òun sì sinmi lórí ibùsùn kan ní ọjọ́-kanrí.
Əmdi bir küni Bǝǝrotloⱪ Rimmonning oƣulliri Rǝkab bilǝn Baanaⱨ qingⱪi qüx waⱪtida Ixboxǝtning ɵyigǝ bardi. Ixboxǝt qüxlük uyⱪuda uhlawatⱪanidi.
6 Sì wò ó, bí olùṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé náà ti ń gbọn àwọn pàǹtí, ó tòògbé ó sì sùn lọ, wọ́n sì wá sí àárín ilé náà, wọ́n sì ṣe bí ẹni pé wọ́n ń fẹ́ mú alikama; wọ́n sì gún un lábẹ́ inú. Rekabu àti Baanah arákùnrin rẹ̀ sì sálọ.
Ular buƣday alimiz degǝnni baⱨanǝ ⱪilip, ɵyining iqkirigǝ kirip, Ixboxǝtning ⱪorsiⱪiƣa [piqaⱪ] sanjidi. Andin Rǝkab wǝ Baanaⱨ ⱪeqip kǝtti
7 Nígbà tí wọ́n wọ ilé náà lọ, òun sì dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀ nínú iyàrá rẹ̀, wọ́n sì pa á, wọ́n sì bẹ́ ẹ lórí, wọ́n gbé orí sálọ, wọ́n sì fi gbogbo òru rìn ni pẹ̀tẹ́lẹ̀ náà.
(ular Ixboxǝt ⱨujrisida kariwatta yatⱪinida, ɵygǝ kirip, uni ɵltürgǝnidi). Ular uning kallisini kesip, andin kallisini elip keqiqǝ Arabaⱨ tüzlǝnglikidin mengip ɵtti.
8 Wọ́n sì gbé orí Iṣboṣeti tọ Dafidi wá ní Hebroni, wọ́n sì wí fún ọba pé, “Wò ó, orí Iṣboṣeti ọmọ Saulu ọ̀tá rẹ, tí ó ti ń wá ẹ̀mí rẹ kiri, Olúwa ti gbẹ̀san fún ọba olúwa mi lónìí lára Saulu àti lára irú-ọmọ rẹ̀.”
Ular Ixboxǝtning kallisini Ⱨebronƣa, Dawutning ⱪexiƣa elip berip, padixaⱨⱪa: Mana, bu janablirining jenini izdigǝn düxmǝnliri Saulning oƣli Ixboxǝtning kallisi! Bügün Pǝrwǝrdigar ƣojam padixaⱨni Saul bilǝn nǝslidin intiⱪam elixⱪa muyǝssǝr ⱪildi — dedi.
9 Dafidi sì dá Rekabu àti Baanah arákùnrin rẹ̀, àwọn ọmọ Rimoni ará Beeroti lóhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Bí Olúwa ti ń bẹ, ẹni tí ó gba ẹ̀mí mi lọ́wọ́ gbogbo ìpọ́njú.
Dawut Bǝǝrotluⱪ Rimmonning oƣulliri Rǝkab bilǝn inisi Baanaⱨƣa: Meni barliⱪ ⱪiyinqiliⱪlardin ⱪutⱪuzƣan Pǝrwǝrdigarning ⱨayati bilǝn ⱪǝsǝm ⱪilimǝnki,
10 Nígbà tí ẹnìkan rò fún mi pé, ‘Wò ó, Saulu ti kú,’ lójú ara rẹ̀ òun sì jásí ẹni tí ó mú ìyìnrere wá, èmi sì mú un, mo sì pa á ní Siklagi, ẹni tí ó ṣe bí òun ó rí nǹkan gbà nítorí ìròyìn rere rẹ̀.
burun birsi Dawutⱪa hux hǝwǝr elip kǝldim, dǝp oylap, manga: — Mana, Saul ɵldi, dǝp kǝlgǝndǝ, mǝn uni elip Ziklagta ɵltürüwǝttim. Bǝrⱨǝⱪ, mana bu uning yǝtküzgǝn hǝwirining mukapati bolƣanidi!
11 Mélòó mélòó ni, nígbà tí àwọn ìkà ènìyàn pa olódodo ènìyàn kan ni ilé rẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀—ǹjẹ́ èmi ha sì lè ṣe aláìbéèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ yín bí? Kí èmi sì mú yín kúrò láààyè.”
Əmdi mǝn xundaⱪ ⱪilƣan yǝrdǝ, rǝzil adǝmlǝr ɵz ɵyidǝ orunda yatⱪan bir ⱨǝⱪⱪaniy kixini ɵltürgǝn bolsa, mǝn nemǝ ⱪilay?! Uning aⱪⱪan ⱪan ⱪǝrzini silǝrning ⱪolunglardin elip, silǝrni yǝr yüzidin yoⱪatmamdim? — dedi.
12 Dafidi sì fi àṣẹ fún àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ̀, wọ́n sì pa wọ́n, wọ́n sì gé ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn, a sì fi wọ́n há lórí igi ní Hebroni. Ṣùgbọ́n wọ́n mú orí Iṣboṣeti, wọ́n sì sin ín ní ibojì Abneri ní Hebroni.
Dawut ƣulamliriƣa buyruⱪ ⱪiliwidi, ular bularni ⱪǝtl ⱪildi. Ularning ⱪol-putlirini kesip, ularni Ⱨebrondiki kɵlning yenida esip ⱪoydi; lekin ular Ixboxǝtning bexini elip Ⱨebronda Abnǝrning ⱪǝbrisidǝ dǝpnǝ ⱪildi.