< 2 Samuel 4 >

1 Nígbà tí ọmọ Saulu sì gbọ́ pé, Abneri kú ní Hebroni, ọwọ́ rẹ̀ sì rọ, gbogbo Israẹli sì rẹ̀wẹ̀sì.
Na rĩrĩ, hĩndĩ ĩrĩa Ishi-Boshethu mũrũ wa Saũlũ aaiguire atĩ Abineri nĩakuĩrĩire kũu Hebironi-rĩ, akĩũrwo nĩ hinya, nao andũ othe a Isiraeli makĩmaka.
2 Ọmọ Saulu sì ní ọkùnrin méjì tí í ṣe olórí ẹgbẹ́ ogun: a ń pe orúkọ ọ̀kan ní Baanah, àti orúkọ èkejì ní Rekabu, àwọn ọmọ Rimoni ará Beeroti ti àwọn ọmọ Benjamini (nítorí pé a sì ka Beeroti pẹ̀lú Benjamini).
Nake mũrũ wa Saũlũ aarĩ na andũ eerĩ arĩa maarĩ atongoria a ikundi cia gũtharĩkanĩra. Ũmwe eetagwo Baana na ũcio ũngĩ Rekabu; maarĩ ariũ a Rimoni ũrĩa Mũbeerothi wa mũhĩrĩga wa Benjamini; Beerothu gũtaragwo ta gĩcunjĩ kĩa Benjamini,
3 Àwọn ará Beeroti sì ti sálọ sí Gittaimu, wọ́n sì ṣe àtìpó níbẹ̀ títí ó fi di ọjọ́ òní yìí.
tondũ andũ a Beerothu nĩmoorĩire Gitaimu na matũũrĩte kuo ta andũ a kũngĩ nginyagia ũmũthĩ.
4 (Jonatani ọmọ Saulu sì ti bí ọmọkùnrin kan tí ẹsẹ̀ rẹ̀ rọ, òun sì jẹ́ ọdún márùn-ún, nígbà tí ìròyìn dé ní ti Saulu àti Jonatani láti Jesreeli wá, olùtọ́ rẹ̀ sì gbé e, o sì sálọ, ó sì ṣe, bí ó sì ti ń yára láti sálọ, òun sì ṣubú, ó sì ya arọ. Orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Mefiboṣeti.)
(Jonathani mũrũ wa Saũlũ aarĩ na mũriũ wonjete magũrũ meerĩ. Aarĩ na ũkũrũ wa mĩaka ĩtano rĩrĩa ũhoro wa Saũlũ na Jonathani wamakinyĩire kuuma Jezireeli. Nake mũreri wake akĩmũkuua, akĩũra; no rĩrĩa aahiũhĩte akĩũra-rĩ, mwana ũcio akĩgũa agĩtuĩka kĩonje. Rĩĩtwa rĩake rĩarĩ Mefiboshethu.)
5 Àwọn ọmọ Rimoni, ará Beeroti, Rekabu àti Baanah sì lọ wọ́n sì wá síh ilé Iṣboṣeti ní ọ̀sán gangan, òun sì sinmi lórí ibùsùn kan ní ọjọ́-kanrí.
Nake Rekabu na Baana, ariũ a Rimoni ũrĩa Mũbeerothi, magĩthiĩ marorete nyũmba-inĩ ya Ishi-Boshethu, na magĩkinya kuo rĩrĩa gũkoragwo kũrĩ ũrugarĩ mũthenya, rĩrĩa aahurũkĩte mĩaraho.
6 Sì wò ó, bí olùṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé náà ti ń gbọn àwọn pàǹtí, ó tòògbé ó sì sùn lọ, wọ́n sì wá sí àárín ilé náà, wọ́n sì ṣe bí ẹni pé wọ́n ń fẹ́ mú alikama; wọ́n sì gún un lábẹ́ inú. Rekabu àti Baanah arákùnrin rẹ̀ sì sálọ.
Nao makĩingĩra nyũmba ya thĩinĩ metuĩte ta meendaga gũkuua ngano, makĩmũtheeca nda. Nake Rekabu na mũrũ wa nyina Baana makĩũra.
7 Nígbà tí wọ́n wọ ilé náà lọ, òun sì dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀ nínú iyàrá rẹ̀, wọ́n sì pa á, wọ́n sì bẹ́ ẹ lórí, wọ́n gbé orí sálọ, wọ́n sì fi gbogbo òru rìn ni pẹ̀tẹ́lẹ̀ náà.
Maingĩrire nyũmba hĩndĩ ĩrĩa aakomete gĩtanda-inĩ nyũmba yake ya toro. Maarĩkia kũmũtheeca na kũmũũraga, magĩtinia mũtwe wake. Makĩũkuua, magĩthiĩ ũtukũ wothe magerete njĩra ya Araba.
8 Wọ́n sì gbé orí Iṣboṣeti tọ Dafidi wá ní Hebroni, wọ́n sì wí fún ọba pé, “Wò ó, orí Iṣboṣeti ọmọ Saulu ọ̀tá rẹ, tí ó ti ń wá ẹ̀mí rẹ kiri, Olúwa ti gbẹ̀san fún ọba olúwa mi lónìí lára Saulu àti lára irú-ọmọ rẹ̀.”
Magĩtwarĩra Daudi mũtwe wa Ishi-Boshethu kũu Hebironi, makĩĩra mũthamaki atĩrĩ, “Ĩ ũyũ mũtwe wa Ishi-Boshethu mũrũ wa Saũlũ, thũ yaku, ũrĩa wageragia gũkũũraga. Ũmũthĩ nĩguo Jehova arĩhĩria mwathi wakwa mũthamaki gwĩ Saũlũ na rũciaro rwake.”
9 Dafidi sì dá Rekabu àti Baanah arákùnrin rẹ̀, àwọn ọmọ Rimoni ará Beeroti lóhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Bí Olúwa ti ń bẹ, ẹni tí ó gba ẹ̀mí mi lọ́wọ́ gbogbo ìpọ́njú.
Nake Daudi agĩcookeria Rekabu na Baana, mũrũ wa nyina, ariũ a Rimoni ũrĩa Mũbeerothi atĩrĩ, “Ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo, ũrĩa ũhonoketie kuuma mathĩĩna-inĩ mothe,
10 Nígbà tí ẹnìkan rò fún mi pé, ‘Wò ó, Saulu ti kú,’ lójú ara rẹ̀ òun sì jásí ẹni tí ó mú ìyìnrere wá, èmi sì mú un, mo sì pa á ní Siklagi, ẹni tí ó ṣe bí òun ó rí nǹkan gbà nítorí ìròyìn rere rẹ̀.
rĩrĩa mũndũ aanjĩĩrire atĩrĩ, ‘Saũlũ nĩakuĩte’, agĩĩciiria atĩ nĩ ũhoro mwega andehera, ndamũnyiitire ngĩmũũragĩra kũu Zikilagi. Kĩu nĩkĩo kĩheo kĩrĩa ndamũheire nĩ ũndũ wa ndũmĩrĩri ĩyo yake!
11 Mélòó mélòó ni, nígbà tí àwọn ìkà ènìyàn pa olódodo ènìyàn kan ni ilé rẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀—ǹjẹ́ èmi ha sì lè ṣe aláìbéèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ yín bí? Kí èmi sì mú yín kúrò láààyè.”
Akĩrĩ makĩria atĩa, hĩndĩ ĩrĩa andũ aaganu moragĩte mũndũ ũtarĩ na ihĩtia thĩinĩ wa nyũmba yake akomete ũrĩrĩ-inĩ wake, githĩ ndiagĩrĩirwo nĩ gwĩtia thakame yake kuuma moko-inĩ manyu na ndĩmweherie muume thĩ!”
12 Dafidi sì fi àṣẹ fún àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ̀, wọ́n sì pa wọ́n, wọ́n sì gé ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn, a sì fi wọ́n há lórí igi ní Hebroni. Ṣùgbọ́n wọ́n mú orí Iṣboṣeti, wọ́n sì sin ín ní ibojì Abneri ní Hebroni.
Nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩatha andũ ake, nao makĩmooraga. Makĩmatinia moko na magũrũ, na magĩcuuria mĩĩrĩ yao hau karia-inĩ kũu Hebironi. No rĩrĩ, makĩoya mũtwe wa Ishi-Boshethu na makĩũthika mbĩrĩra-inĩ ya Abineri kũu Hebironi.

< 2 Samuel 4 >