< 2 Samuel 3 >

1 Ogun náà sì pẹ́ títí láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi: agbára Dafidi sì ń pọ̀ sí i, ṣùgbọ́n ìdílé Saulu ń rẹ̀yìn sí i.
Na rĩrĩ, mbaara gatagatĩ ka nyũmba ya Saũlũ na nyũmba ya Daudi nĩyatũũrire ihinda iraaya. Daudi agĩkĩrĩrĩria kũgĩa hinya; nayo nyũmba ya Saũlũ ĩgĩkĩrĩrĩria kwaga hinya.
2 Dafidi sì bí ọmọkùnrin ní Hebroni: Amnoni ni àkọ́bí rẹ̀ tí Ahinoamu ará Jesreeli bí fún un.
Nake Daudi nĩagĩire na ciana cia aanake arĩ kũu Hebironi: Mũriũ wake wa irigithathi eetagwo Amunoni ũrĩa waciarĩtwo nĩ Ahinoamu ũrĩa Mũjezireeli;
3 Èkejì rẹ̀ sì ni Kileabu, tí Abigaili aya Nabali ará Karmeli bí fún un; ẹ̀kẹta sì ni Absalomu ọmọ tí Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri bí fún un.
Mũriũ wa keerĩ eetagwo Kileabu ũrĩa waciarĩtwo nĩ Abigaili ũrĩa warĩ mũtumia wa ndigwa wa Nabali ũrĩa Mũkarimeli; na wa gatatũ aarĩ Abisalomu ũrĩa waciarĩtwo nĩ Maaka mwarĩ wa Talimai mũthamaki wa Geshuru;
4 Ẹ̀kẹrin sì ni Adonijah ọmọ Haggiti; àti ẹ̀karùnún ni Ṣefatia ọmọ Abitali;
wa kana aarĩ Adonija ũrĩa waciarĩtwo nĩ Hagithu; wa gatano aarĩ Shefatia ũrĩa waciarĩtwo nĩ Abitali;
5 Ẹ̀kẹfà sì ni Itreamu, tí Egla aya Dafidi bí fún un. Wọ̀nyí ni a bí fún Dafidi ni Hebroni.
na wa gatandatũ aarĩ Ithireamu mũrũ wa Egila mũtumia wa Daudi. Acio nĩo maaciarĩirwo Daudi kũu Hebironi.
6 Ó sì ṣe, nígbà tí ogun wà láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi, Abneri sì dì alágbára ní ìdílé Saulu.
Hĩndĩ ya mbaara ya nyũmba ya Saũlũ na nyũmba ya Daudi, Abineri no kũgĩa aagĩaga na hinya arĩ thĩinĩ wa nyũmba ya Saũlũ.
7 Saulu ti ní àlè kan, orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Rispa, ọmọbìnrin Aiah: Iṣboṣeti sì bi Abneri léèrè pé, “Èéṣe tí ìwọ fi wọlé tọ àlè baba mi lọ.”
Na rĩrĩ, Saũlũ nĩ arĩ na thuriya yetagwo Rizipa mwarĩ wa Aia. Nake Ishi-Boshethu akĩũria Abineri atĩrĩ, “Wakomire na thuriya ya baba nĩkĩ?”
8 Abneri sì bínú gidigidi nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ti Iṣboṣeti sọ fún un, ó sì wí pé, “Èmi jẹ́ bí orí ajá ti Juda bí? Di òní yìí ni mo ṣàánú fún ìdílé Saulu baba rẹ, àti fún àwọn arákùnrin rẹ̀, àti fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, tí èmi kò sì fi ọ́ lé Dafidi lọ́wọ́, ìwọ sì kà ẹ̀ṣẹ̀ sí mí lọ́rùn nítorí obìnrin yìí lónìí?
Abineri nĩarakarire mũno tondũ wa kwĩrwo ũguo nĩ Ishi-Boshethu, nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Kaĩ ndĩkĩrĩ mũtwe wa ngui mwena-inĩ wa Juda? Ũmũthĩ ũyũ niĩ ndĩ rũmwe na nyũmba ya thoguo Saũlũ na andũ a nyũmba yake na arata. Niĩ ndirĩ ndaamũneana kũrĩ Daudi. No rĩu ũranjĩĩra atĩ nĩhĩtĩtie ihĩtia ũhoro-inĩ ũkoniĩ mũndũ-wa-nja ũyũ!
9 Bẹ́ẹ̀ ni kí Ọlọ́run ó ṣe Abneri, àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú, bí Olúwa ti búra fún Dafidi, bí èmi kò ní ṣe bẹ́ẹ̀ fún un.
Ngai arothũũra, niĩ Abineri, na anjĩke ũũru makĩria, ingĩaga kũhingĩria Daudi ũrĩa Jehova aamwĩrĩire na mwĩhĩtwa,
10 Láti mú ìjọba náà kúrò ní ìdílé Saulu, àti láti gbé ìtẹ́ Dafidi kalẹ̀ lórí Israẹli, àti lórí Juda, láti Dani títí ó fi dé Beerṣeba.”
na ndute ũthamaki nyũmba-inĩ ya Saũlũ, na ndũgamie gĩtĩ kĩa Daudi kĩa ũnene igũrũ wa Isiraeli na Juda, kuuma Dani nginya Birishiba.”
11 Òun kò sì lè dá Abneri lóhùn kan nítorí tí ó bẹ̀rù rẹ̀.
Ishi-Boshethu ndaigana kwĩra Abineri ũndũ ũngĩ tondũ nĩamwĩtigĩrĩte.
12 Abneri sì rán àwọn oníṣẹ́ sí Dafidi nítorí rẹ̀ wí pé, “Ti ta ni ilẹ̀ náà ń ṣe? Bá mi ṣe àdéhùn, èmi yóò si kó gbogbo Israẹli tọ̀ ọ́ wá.”
Ningĩ Abineri agĩtũma andũ kũrĩ Daudi makamwĩre atĩrĩ, “Bũrũri ũyũ nĩ waũ? Nĩtũgĩe na kĩrĩkanĩro nawe, na nĩngũgũteithia ngũrehere andũ a Isiraeli othe mwena waku.”
13 Òun sì wí pé, “Ó dára, èmi ó bá ọ ṣe àdéhùn, ṣùgbọ́n ohun kan ni èmi ó béèrè lọ́wọ́ rẹ, èyí ni pé, ìwọ kì yóò rí ojú mi, àfi bí ìwọ bá kọ́ mú Mikali ọmọbìnrin Saulu wá, nígbà tí ìwọ bá wá, láti rí ojú mi.”
Nake Daudi akiuga atĩrĩ, “Ũguo nĩ wega. Nĩtũkũgĩa na kĩrĩkanĩro nawe. No nĩ harĩ ũndũ ũmwe ngwenda wĩke: ndũkanooke mbere yakwa angĩkorwo ndũkarehe Mikali mwarĩ wa Saũlũ hĩndĩ ĩrĩa ũgooka kũnyona.”
14 Dafidi sì rán àwọn ìránṣẹ́ sí Iṣboṣeti ọmọ Saulu pé, “Fi Mikali obìnrin mi lé mi lọ́wọ́, ẹni tí èmi ti fi ọgọ́rùn-ún awọ iwájú orí àwọn Filistini fẹ́.”
Ningĩ Daudi agĩtũma andũ kũrĩ Ishi-Boshethu mũrũ wa Saũlũ makamwĩre atĩrĩ, “Nengera mũtumia wakwa Mikali, ũrĩa ndagũrire na ikonde igana rĩmwe cia Afilisti.”
15 Iṣboṣeti sì ránṣẹ́, ó sì gbà á lọ́wọ́ ọkùnrin tí a ń pè ní Paltieli ọmọ Laiṣi.
Nĩ ũndũ ũcio Ishi-Boshethu agĩathana Mikali agĩĩrwo kuuma kũrĩ mũthuuriwe Palitieli mũrũ wa Laishi.
16 Ọkọ rẹ̀ sì ń bà a lọ, ó ń rìn, ó sì ń sọkún lẹ́yìn rẹ̀ títí ó fi dé Bahurimu Abneri sì wí fún un pé, “Padà sẹ́yìn!” Òun sì padà.
No rĩrĩ, mũthuuriwe, agĩtwarana nake, agĩthiĩ amũrũmĩrĩire akĩrĩraga nginya Bahurimu. Hĩndĩ ĩyo Abineri akĩmwĩra atĩrĩ, “Cooka mũciĩ!” Nĩ ũndũ ũcio agĩcooka mũciĩ.
17 Abneri sì bá àwọn àgbàgbà Israẹli sọ̀rọ̀ pé, “Ẹ̀yin ti ń ṣe àfẹ́rí Dafidi ní ìgbà àtijọ́, láti jẹ ọba lórí yín.
Nake Abineri akĩaranĩria na athuuri a Isiraeli akĩmeera atĩrĩ, “Kwa ihinda nĩmũkoretwo mwĩrirĩirie gũtua Daudi mũthamaki wanyu.
18 Ǹjẹ́ ẹ ṣe, nítorí tí Olúwa ti sọ fún Dafidi pé, ‘Láti ọwọ́ Dafidi ìránṣẹ́ mi lé mi ó gba Israẹli ènìyàn mi là kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini àti lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá a wọn.’”
Mũtigĩĩke ũguo rĩu! Nĩgũkorwo Jehova nĩerire Daudi atĩrĩ, ‘Na ũndũ wa ndungata yakwa Daudi nĩngahonokia andũ akwa a Isiraeli kuuma guoko-inĩ kwa Afilisti na kuuma guoko-inĩ gwa thũ ciao ciothe.’”
19 Abneri sì sọ̀rọ̀ létí Benjamini: Abneri sì lọ sọ létí Dafidi ní Hebroni, gbogbo èyí tí ó dára lójú Israẹli, àti lójú gbogbo ilé Benjamini.
Nake Abineri nĩacookire akĩaranĩria na andũ a Benjamini. Agĩcooka agĩthiĩ Hebironi akeere Daudi maũndũ mothe marĩa Isiraeli na nyũmba yothe ya Benjamini meendaga gwĩka.
20 Abneri sì tọ Dafidi wá ní Hebroni, ogún ọmọkùnrin sì lọ pẹ̀lú rẹ̀ Dafidi sì ṣe àsè fún Abneri àti fún àwọn ọmọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀.
Rĩrĩa Abineri, ũrĩa warĩ na andũ mĩrongo ĩĩrĩ ookire kũrĩ Daudi kũu Hebironi, Daudi akĩmũrugithĩria iruga hamwe na andũ ake.
21 Abneri sì wí fún Dafidi pé, “Èmi ó dìde, èmi ó sì lọ, èmi ó sì kó gbogbo Israẹli jọ sọ́dọ̀ ọba olúwa mi, wọn ó sì bá a ṣe àdéhùn, ìwọ ó sì jẹ ọba gbogbo wọn bí ọkàn rẹ ti ń fẹ́.” Dafidi sì rán Abneri lọ; òun sì lọ ní àlàáfíà.
Hĩndĩ ĩyo Abineri akĩĩra Daudi atĩrĩ, “Reke thiĩ o ro rĩu ngacookanĩrĩrie andũ a Isiraeli othe nĩ ũndũ wa mũthamaki mwathi wakwa, nĩgeetha marĩkanĩre nawe, na nĩguo ũthamakagĩre o kũrĩa guothe ngoro yaku ĩĩrirĩirie.” Nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩtũma Abineri athiĩ, nake agĩthiĩ na thayũ.
22 Sì wò ó, àwọn ìránṣẹ́ Dafidi àti Joabu sì ti ibi ìlépa ẹgbẹ́ ogun kan bọ̀, wọ́n sì mú ìkógun púpọ̀ bọ̀; ṣùgbọ́n Abneri kò sí lọ́dọ̀ Dafidi ní Hebroni; nítorí tí òun ti rán an lọ, òun sì ti lọ ní àlàáfíà.
Hĩndĩ o ĩyo andũ a Daudi, na Joabu magĩcooka kuuma mbaara-inĩ, na magĩũka na indo nyingĩ iria maatahĩte. No Abineri ndaarĩ hamwe na Daudi kũu Hebironi, tondũ Daudi nĩamwĩrĩte athiĩ, nake agĩthiĩ na thayũ.
23 Nígbà tí Joabu àti gbogbo ogun tí ó pẹ̀lú rẹ̀ sì dé, wọ́n sì sọ fún Joabu pé Abneri, ọmọ Neri ti tọ ọba wá, òun sì ti rán an lọ, ó sì ti lọ ní àlàáfíà.
Rĩrĩa Joabu na thigari ciothe iria ciarĩ hamwe nake maakinyire-rĩ, akĩĩrwo atĩ Abineri mũrũ wa Neri nĩokĩte kũrĩ mũthamaki, na atĩ mũthamaki nĩarekire athiĩ, nake agĩthiĩ na thayũ.
24 Joabu sì tọ ọba wá, ó sì sọ pé, “Kí ni ìwọ ṣe yìí? Wò ó, Abneri tọ̀ ọ́ wá; èéha ti ṣe tí ìwọ sì fi rán an lọ? Òun sì ti lọ.
Nĩ ũndũ ũcio Joabu agĩthiĩ kũrĩ mũthamaki akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa ũguo weka? Ta kĩone, Abineri nĩokire kũrĩ wee. Ũrekire athiĩ nĩkĩ? Rĩu nĩagĩthiire!
25 Ìwọ mọ Abneri ọmọ Neri, pé ó wá láti tàn ọ́ jẹ ni, àti láti mọ ìjáde lọ rẹ, àti wíwọlé rẹ́ àti láti mọ gbogbo èyí tí ìwọ ń ṣe.”
Wee nĩũũĩ atĩ Abineri mũrũ wa Neri egũũkĩte gũkũheenia na gũthigaana mĩthiĩre yaku, na amenye maũndũ marĩa mothe ũreka.”
26 Nígbà tí Joabu sì jáde kúrò lọ́dọ̀ Dafidi, ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ láti lépa Abneri, wọ́n sì pè é padà láti ibi kànga Sira, Dafidi kò sì mọ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa Joabu oimire harĩ Daudi, agĩtũma andũ makinyĩre Abineri, nao makĩmũcookia kuuma gĩthima-inĩ gĩa Sira. No Daudi ndaigana kũmenya ũhoro ũcio.
27 Abneri sì padà sí Hebroni, Joabu sì bá a tẹ̀ láàrín ojú ọ̀nà láti bá a sọ̀rọ̀ ní àlàáfíà, ó sì gún un níbẹ̀ lábẹ́ inú, ó sì kú, nítorí ẹ̀jẹ̀ Asaheli arákùnrin rẹ̀.
Na rĩrĩ, rĩrĩa Abineri aacookire Hebironi, Joabu akĩmũtwara keheri-inĩ kĩhingo-inĩ, ta ekwenda kwaria nake na hitho. Na marĩ hau, akĩmũtheeca nda agĩkua, nĩguo arĩhĩrie thakame ya mũrũ wa nyina Asaheli.
28 Lẹ́yìn ìgbà tí Dafidi sì gbọ́ ọ, ó sì wí pé, “Èmi àti ìjọba mi sì jẹ́ aláìlẹ́bi níwájú Olúwa títí láé, ní ti ẹ̀jẹ̀ Abneri ọmọ Neri,
Thuutha ũcio, rĩrĩa Daudi aiguire ũhoro ũcio, akiuga atĩrĩ, “Niĩ na ũthamaki wakwa tũtirĩ na ihĩtia nginya tene mbere ya Jehova ũhoro-inĩ wa thakame ya Abineri mũrũ wa Neri.
29 jẹ́ kí ó wà ní orí Joabu, àti ní orí gbogbo ìdílé baba rẹ̀; kí a má sì fẹ́ ẹni ó tí ní ààrùn ìsun, tàbí adẹ́tẹ̀, tàbí ẹni tí ń tẹ ọ̀pá, tàbí ẹni tí a ó fi idà pa, tàbí ẹni tí ó ṣe aláìní oúnjẹ kù ní ilé Joabu.”
Thakame yake ĩrocookerera Joabu na nyũmba ya ithe yothe! Nayo nyũmba ya Joabu ndĩkanaage mũndũ ũmwe ũrĩ na kĩronda gĩkuura thakame, kana mangũ, kana mũndũ ũrĩthiiaga na mĩtĩ, kana mũndũ ũũragĩtwo na rũhiũ rwa njora, kana mũndũ wagĩte irio.”
30 (Joabu àti Abiṣai arákùnrin rẹ̀ sì pa Abneri, nítorí pé òun ti pa Asaheli arákùnrin wọn ní Gibeoni ní ogun.)
(Joabu na Abishai mũrũ wa nyina mooragire Abineri tondũ nĩooragĩte Asaheli mũrũ wa nyina wao mbaara-inĩ kũu Gibeoni.)
31 Dafidi sì wí fún Joabu àti fún gbogbo ènìyàn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ fa aṣọ yín ya, kí ẹ̀yin sì mú aṣọ ọ̀fọ̀, kí ẹ̀yin sì sọkún níwájú Abneri.” Dafidi ọba tìkára rẹ̀ sì tẹ̀lé pósí rẹ̀.
Hĩndĩ ĩyo Daudi akĩĩra Joabu na andũ othe arĩa aarĩ nao atĩrĩ, “Tembũrangai nguo cianyu na mwĩhumbe makũnia, na mũthiĩ mũgĩcakayaga mbere ya Abineri.” Nake Daudi ũcio mũthamaki agĩthiĩ arũmĩrĩire ndayaya ĩrĩa yakuuĩte kĩimba.
32 Wọ́n sì sin Abneri ní Hebroni, ọba sì gbé ohùn rẹ̀ sókè, ó sì sọkún ní ibojì Abneri; gbogbo àwọn ènìyàn náà sì sọkún.
Nao magĩthika Abineri kũu Hebironi, nake mũthamaki akĩrĩra aanĩrĩire hau mbĩrĩra-inĩ ya Abineri. O nao andũ othe makĩrĩra.
33 Ọba sì sọkún lórí Abneri, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ Abneri ó yẹ kí ó kú bí aṣiwèrè?
Mũthamaki akĩina icakaya rĩĩrĩ nĩ ũndũ wa Abineri: “Abineri nĩaragĩrĩirwo nĩgũkua ta andũ arĩa moinaga watho?
34 A kò sá à dè ọ́ lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ni a kò kan ẹsẹ̀ rẹ ní àbà. Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ń ṣubú níwájú àwọn ìkà ènìyàn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ ṣubú.” Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì tún sọkún lórí rẹ̀.
Moko maku matiarĩ moohe, namo magũrũ maku matiarĩ moohe na nyororo. Wagũire o ta mũndũ ũrĩa ũgũũaga mbere ya andũ arĩa aaganu.” Nao andũ othe makĩrĩra rĩngĩ nĩ ũndũ wake.
35 Nígbà tí gbogbo ènìyàn sì wá láti gba Dafidi ní ìyànjú kí ó jẹun, nígbà tí ọjọ́ sì ń bẹ, Dafidi sì búra wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni kí Ọlọ́run ó ṣe sí mi àti jù bẹ́ẹ̀ lọ, bí èmi yóò bá tọ́ oúnjẹ wò, tàbí nǹkan mìíràn títí oòrùn yóò fi wọ̀!”
Ningĩ andũ othe magĩũka na makĩringĩrĩria Daudi arĩe irio gũtanatuka, no Daudi akĩĩhĩta na mwĩhĩtwa, akiuga atĩrĩ, “Ngai arothũũra, o na anjĩke ũũru makĩria, ingĩcama irio kana kĩndũ kĩngĩ riũa rĩtanathũa!”
36 Gbogbo àwọn ènìyàn sì kíyèsi i, ó sì dára lójú wọn, gbogbo èyí tí ọba ṣe sì dára lójú gbogbo àwọn ènìyàn náà.
Nao andũ acio othe maakĩona ũrĩa gwathiĩ magĩkena; ti-itherũ, maũndũ mothe marĩa mũthamaki eekire nĩmamakenirie.
37 Gbogbo àwọn ènìyàn náà àti gbogbo Israẹli sì mọ̀ lọ́jọ́ náà pé, kì í ṣe ìfẹ́ ọba láti pa Abneri ọmọ Neri.
Nĩ ũndũ ũcio andũ othe na Isiraeli guothe makĩmenya mũthenya ũcio atĩ mũthamaki ndaarĩ na itemi ũhoro-inĩ wa gĩkuũ kĩa Abineri mũrũ wa Neri.
38 Ọba sì wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ̀yin kò mọ̀ pé olórí àti ẹni ńlá kan ni ó ṣubú lónìí ní Israẹli.
Ningĩ mũthamaki akĩĩra andũ ake atĩrĩ, “Kaĩ mũtaramenya atĩ mũndũ mũnene na ũrĩ igweta mũno nĩarĩkĩtie gũkua ũmũthĩ thĩinĩ wa Isiraeli?
39 Èmi sì ṣe aláìlágbára lónìí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a fi èmi jẹ ọba; àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ọmọ Seruiah sì le jù mí lọ: Olúwa ni yóò san án fún ẹni tí ó ṣe ibi gẹ́gẹ́ bí ìwà búburú rẹ̀!”
Na rĩrĩ, ũmũthĩ, o na gũkorwo ndĩmũitĩrĩrie maguta nduĩke mũthamaki, ndirĩ na hinya, nao ariũ aya a Zeruia marĩ na hinya mũno kũngĩra. Jehova arorĩhia mwĩki ũũru kũringana na ciĩko ciake njũru!”

< 2 Samuel 3 >