< 2 Samuel 23 >

1 Wọ̀nyí sì ni ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi. “Dafidi ọmọ Jese, àní ọkùnrin tí a ti gbéga, ẹni àmì òróró Ọlọ́run Jakọbu, àti olórin dídùn Israẹli wí pé,
EIA na olelo hope a Davida. I aku la o Davida ke keiki a Iese, ke kanaka i hookiekieia'e iluna, ka mea poni a ke Akua o Iakoba, a me ka mea haku mele maikai no ka Iseraela,
2 “Ẹ̀mí Olúwa sọ ọ̀rọ̀ nípa mi, ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì ń bẹ ní ahọ́n mi.
Ua olelo aku ka Uhane o Iehova ma o'u nei, a ma ko'u alelo kana olelo.
3 Ọlọ́run Israẹli ni, àpáta Israẹli sọ fún mi pé, ‘Ẹnìkan ti ń ṣe alákòóso ènìyàn lódodo, tí ń ṣàkóso ní ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
I mai la ke Akua no ka Iseraela, olelo mai la ka Pohaku no ka Iseraela ia'u, O ka mea e alii ana maluna o kanaka, e hoopono oia, e alii ana me ka makau i ke Akua.
4 Yóò sì dàbí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ nígbà tí oòrùn bá là, òwúrọ̀ tí kò ní ìkùùkuu, nígbà tí koríko tútù bá hù wá láti ilẹ̀ lẹ́yìn òjò.’
A e like ia me ka malamalama o ke kakahiaka i ka puka ana o ka la, me ke kakahiaka i uhi ole ia e ke ao; a e like hoi me ka mauu opiopio mailoko mai o ka honua, e kupu ana ma ka malamalama aiai mahope iho o ka ua.
5 “Lóòtítọ́ ilé mi kò rí bẹ́ẹ̀ níwájú Ọlọ́run, ṣùgbọ́n ó ti bá mi dá májẹ̀mú àìnípẹ̀kun, tí a túnṣe nínú ohun gbogbo, tí a sì pamọ́; nítorí pé gbogbo èyí ni ìgbàlà, àti gbogbo ìfẹ́ mi, ilé mi kò lè ṣe kí ó má dàgbà.
Ina aole pela ka'u ohana imua o ke Akua; ua hookau mai hoi oia i berita mau loa me au, i hoonohonoho pono ia ma na mea a pau, a i malamaia: no ka mea, oia kuu mea e ola'i a pau, a me kuu makemake a pau, ke ole paha ia e hooulu ae ia.
6 Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọ Beliali yóò dàbí ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n tí a ṣá tì, nítorí pé a kò lè fi ọwọ́ kó wọn.
Aka, e pau no ka poe Beliala i ke kiolaia'ku e like me ka nahele ooi; no ka mea, aole e hiki ke hoopaia'ku e na lima.
7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí yóò tọ́ wọn yóò fi irin àti ọ̀pá ọ̀kọ̀ ṣagbára yí ara rẹ̀ ká; wọ́n ó jóná lúúlúú níbìkan náà.”
A o ke kanaka nana lakou e hoopa aku, e pono ia ia ke uhiia i na mea hao, a me ke au o ka ihe, a e pau lakou i ka puhiia maloko o ke ahi ma ia wahi no.
8 Wọ̀nyí sì ni orúkọ àwọn akọni ọkùnrin tí Dafidi ní: Joṣebu-Basṣebeti ará Takemoniti ni olórí àwọn balógun, òun sì ni akọni rẹ̀ tí ó pa ẹgbẹ̀rin ènìyàn lẹ́ẹ̀kan náà.
Eia na inoa o na kanaka ikaika no Davida; o ko Takemoni ka i noho ma ka noho, ka luna o na mea akolu, oia ka mea i hoaka i ka ihe i ku e i na haneri kanaka ewalu, a pepehi aku la i ka manawa hookahi.
9 Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni Eleasari ọmọ Dodo ará Ahohi, ọ̀kan nínú àwọn alágbára ọkùnrin mẹ́ta ti ó wà pẹ̀lú Dafidi, nígbà tí wọ́n pe àwọn Filistini ní ìjà, àwọn ọkùnrin Israẹli sì ti lọ kúrò.
Mahope iho ona o Eleazara ke keiki a Dodo ke keiki a Ahohi, kekahi o na kanaka ikaika ekolu me Davida, ia lakou i ku e i ka poe Pilisetia i kahi i hoakoakoaia'e lakou e kaua, a na naholo aku na kanaka o ka Iseraela.
10 Òun sì dìde, ó sì kọlu àwọn Filistini títí ọwọ́ fi kún un, ọwọ́ rẹ̀ sì lẹ̀ mọ́ idà; Olúwa sì ṣiṣẹ́ ìgbàlà ńlá lọ́jọ́ náà, àwọn ènìyàn sì padà bọ̀ lẹ́yìn rẹ̀ láti kó ìkógun.
Ku ae la ia, a pepehi aku la i ko Pilisetia, a luhi iho la kona lima, a pipili iho la kona lima i ka pahikaua: na Iehova i haawi mai i ka lanakila nui ia la, a hoi hou mai la na kanaka mahope ona a lawe waiwai pio wale no.
11 Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni Ṣamma ọmọ Agee ará Harari, àwọn Filistini sì kó ara wọn jọ láti piyẹ́, oko kan sì wà níbẹ̀ tí ó kún fun lẹntili, àwọn ọmọ-ogun Israẹli sì sá kúrò níwájú àwọn Filistini.
Mahope iho ona o Sama ke keiki a Agee no ka aina mauna. Ua akoakoa ae ko Pilisetia i poe kaua hookahi ma kahi e paapu ana na papapa: a naholo aku la na kanaka mai ko Pilisetia aku.
12 Ṣamma sì dúró láàrín méjì ilẹ̀ náà, ó sì gbà á sílẹ̀, ó sì pa àwọn Filistini Olúwa sì ṣe ìgbàlà ńlá.
Aka, ku ae la oia mawaena konu o ia wahi, a malama aku ia, a pepehi iho la i ko Pilisetia: a haawi mai la o Iehova i ka lanakila nui.
13 Mẹ́ta nínú àwọn ọgbọ̀n ìjòyè sọ̀kalẹ̀, wọ́n sì tọ Dafidi wá ní àkókò ìkórè nínú ihò Adullamu, ọ̀wọ́ àwọn Filistini sì dó sí àfonífojì Refaimu.
Iho aku la na mea ekolu o ka poe luna he kanakolu, a hiki aku la io Davida la i ke ana o Adulama i ka wa e ohi ai i ka ai, a hoomoana iho la ko Pilisetia ma ke awawa i Repaima.
14 Dafidi sì wà nínú odi, ibùdó àwọn Filistini sì wà ní Bẹtilẹhẹmu nígbà náà.
Ilaila o Davida iloko o ka wahi paa, a ma Betelehema ka pakaua o ke Pilisetia ia manawa.
15 Dafidi sì ń pòǹgbẹ, ó wí báyìí pé, “Ta ni yóò fún mi mu nínú omí kànga tí ń bẹ ní Bẹtilẹhẹmu, èyí tí ó wà ní ìhà ẹnu-bodè.”
A makewai iho la o Davida, i iho la, Nani ino kuu makemake e haawi mai kekahi i wai e inu no ka luawai ma Betelehema ma ka ipuka!
16 Àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta sì la ogún àwọn Filistini lọ, wọ́n sì fa omi láti inú kànga Bẹtilẹhẹmu wá, èyí tí ó wà ní ìhà ẹnu-bodè, wọ́n sì mú tọ Dafidi wá, òun kò sì fẹ́ mu nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n ó tú u sílẹ̀ fún Olúwa.
Wahi ae la ua mau kanaka ikaika la ekolu i ke Pilisetia, a huki ae la i ka wai mai loko ae o ka lua ma Betelehema ma ka ipuka, lalau iho la a lawe ae la ia io Davida la: aka, aole ia i manao e inu, a ninini aku no ia mea no Iehova.
17 Òun sì wí pé, “Kí a má rí, Olúwa, tí èmi ó fi ṣe èyí; ṣé èyí ni ẹ̀jẹ̀ àwọn ọkùnrin tí ó lọ tí àwọn tí ẹ̀mí wọn lọ́wọ́?” Nítorí náà òun kò sì fẹ́ mú un. Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí ṣe.
I aku la ia, E Iehova, aole loa au e hana ia mea; aole anei keia ke koko o na kanaka, o ka poe i hele a kokoke i ka make? Nolaila aole ia i make inu ia. Pela i hana'i ia mau kanaka ikaika ekolu.
18 Abiṣai, arákùnrin Joabu, ọmọ Seruiah, òun náà ni pàtàkì nínú àwọn mẹ́ta. Òun ni ó sì gbé ọ̀kọ̀ rẹ̀ sókè sí ọ̀ọ́dúnrún ènìyàn, ó sì pa wọ́n, ó sì ní orúkọ nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta.
A o Abisai ke kaikaina o Ioaba, ke keiki a Zeruia, oia ka luna o kekahi poe ekolu. Hoaka ae la ia i kana ihe e ku e i na kanaka ekolu haneri, a pepehi iho la ia lakou: a loaa ia ia ka inoa iwaena o ua mau kanaka ikaika la ekolu.
19 Ọlọ́lá jùlọ ni òun jẹ́ nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta, ó sì jẹ́ olórí fún wọn, ṣùgbọ́n òun kò tó àwọn mẹ́ta ìṣáájú.
Aole anei oia ka mea koikoi loa o ka poe ekolu? nolaila oia ko lakou luna: aole hoi i hiki aku kona e like me ko ka poe mua ekolu.
20 Benaiah, ọmọ Jehoiada, ọmọ akọni ọkùnrin kan tí Kabṣeeli, ẹni tí ó pọ̀ ní iṣẹ́ agbára, òun pa àwọn ọmọ Arieli méjì ti Moabu; ó sọ̀kalẹ̀ pẹ̀lú ó sì pa kìnnìún kan nínú ihò lákoko òjò-dídì.
O Benaia hoi ke keiki a Iehoiada, ke keiki a kekahi kanaka ikaika, no Kabezeela, he nui kana hana kupanaha: pepehi iho la ia i na kanaka liona elua o ka Moaba: iho iho la hoi ia iloko o ka lua, a pepehi iho la i ka liona i ka manawa hau.
21 Ó sì pa ará Ejibiti kan, ọkùnrin tí ó dára láti wò, ará Ejibiti náà sì ní ọ̀kọ̀ kan ní ọwọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n Benaiah sì sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ, pẹ̀lú ọ̀pá ní ọwọ́, ó sì gba ọ̀kọ̀ náà lọ́wọ́ ará Ejibiti náà, ó sì fi ọ̀kọ̀ rẹ̀ pa á.
Pepehi iho la hoi oia i kekahi kanaka no Aigupita, he mea helehelena maikai: he ihe no ma ka lima o ke kanaka no Aigupita, a hele aku la kela io na la me ke kookoo, a kaili ae la i ka ihe mai loko ae o ka lima o ke kanaka Aigupita, a pepehi iho la ia ia me kana ihe.
22 Nǹkan wọ̀nyí ní Benaiah ọmọ Jehoiada ṣe, ó sì ní orúkọ nínú àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta náà.
O na mea keia a Benaia a ke keiki a Iehoiada i hana'i, a loaa ia ia ka inoa iwaena o ka poe kanaka ikaika ekolu.
23 Nínú àwọn ọgbọ̀n náà, òun ní ọlá jùlọ, ṣùgbọ́n òun kò tó àwọn mẹ́ta ti ìṣáájú. Dafidi sì fi í ṣe ìgbìmọ̀ rẹ̀.
Ua oi aku kona koikoi i ko ka poe kanakolu, aole hoi i hiki aku kona i ko ka poe mua ekolu. A hoonoho aku la o Davida ia ia i kuhina nona.
24 Ọ̀kan nínú àwọn ọgbọ̀n náà: Asaheli arákùnrin Joabu sì Jásí Elhanani ọmọ Dodo ti Bẹtilẹhẹmu;
O Asahela ke kaikaina o Ioaba kekahi o ka poe kanakolu; a o Elehanana ke keiki a Dodo no Betelehema,
25 Ṣamma ará Haroditi, Elika ará Harodi.
O Sama no Haroda, a o Elika no Haroda,
26 Helesi ará Palti, Ira ọmọ Ikẹsi ará Tekoa;
O Heleza no Paleti, o Ira ke keiki a Ikesa no Tekoa,
27 Abieseri ará Anatoti, Sibekai ará Huṣati;
O Abiezera no Anetota, o Mebunai no Husata,
28 Salmoni ará Ahohi, Maharai ará Netofa;
O Zalemona no Ahota, o Maharai no Netopati,
29 Heledi ọmọ Baanah, ará Netofa, Ittai ọmọ Ribai to Gibeah ti àwọn ọmọ Benjamini;
O Heleba ke keiki a Baana no Netopati, o Itai ke keiki a Ribai no Gibea, no na mamo a Beniamina,
30 Benaiah ará Piratoni, Hiddai ti àfonífojì Gaaṣi,
O Benaia no Piratona, o Hidai no na awawa o Gaasa,
31 Abi-Alboni ará Arbati, Asmafeti Barhumiti;
O Abialebona no Areba, o Azemaveta no Barehuma,
32 Eliaba ará Ṣaalboni, àwọn ọmọ Jaṣeni, Jonatani;
O Eliaba no Saalebo, o Ionatana no na keikikane a Iasehena,
33 ọmọ Ṣamma ará Harari, Ahiamu ọmọ Ṣarari ará Harari;
O Sama no Harara, Ahiama ke keiki a Sarara no Harara,
34 Elifeleti ọmọ Ahasbai, ọmọ ará Maakati, Eliamu ọmọ Ahitofeli ará Giloni;
O Elipaleta ke keiki a Ahasabai, ke keiki a ka Maaka, o Eliama ke keiki a Ahitopela no Gilo,
35 Hesro ará Karmeli, Paarai ará Arba;
O Hezerai no Karemela, o Paarai no Areba,
36 Igali ọmọ Natani ti Soba, Bani ará Gadi;
O Igala ke keiki a Natana no Zoba, o Bani no Gada,
37 Seleki ará Ammoni, Naharai ará Beeroti, ẹni tí ń ru ìhámọ́ra Joabu ọmọ Seruiah;
O Zeleka no ka Amona, o Nahari no Beerota, nana i halihali i na mea kaua no Ioaba ke keiki a Zeruia.
38 Ira ará Itri, Garebu ará Itri.
O Ira no Itera, o Gareba no Itera,
39 Uriah ará Hiti. Gbogbo wọn jẹ́ mẹ́tàdínlógójì.
O Uria ka Heta, he kanakolu kumamahiku lakou a pau.

< 2 Samuel 23 >