< 2 Samuel 22 >

1 Dafidi sì kọ ọ̀rọ̀ orin yìí sí Olúwa ní ọjọ́ tí Olúwa gbà á kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀, àti kúrò lọ́wọ́ Saulu.
Și David a spus DOMNULUI cuvintele acestei cântări în ziua în care DOMNUL l-a eliberat din mâna tuturor dușmanilor săi și din mâna lui Saul;
2 Ó sì wí pé, “Olúwa ni àpáta mi, àti Olùgbàlà mi;
Și a spus: DOMNUL este stânca mea și fortăreața mea și eliberatorul meu;
3 Ọlọ́run mi, àpáta mi, nínú ẹni tí èmi ní ààbò, àti ìwo ìgbàlà mi, ibi ìsádi gíga mi. Àti ibi ìlùmọ̀ mi, Olùgbàlà mi; ìwọ ni ó ti gbà mí kúrò lọ́wọ́ ìwà ipá.
Dumnezeul stâncii mele; în el mă voi încrede; el este scutul meu și cornul salvării mele, turnul meu înalt și locul meu de scăpare, salvatorul meu; tu mă salvezi din violență.
4 “Èmi ké pe Olúwa, tí ó yẹ láti máa yìn, ó sì gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
Voi chema pe DOMNUL, care este demn de laudă; astfel voi fi salvat din mâna dușmanilor mei.
5 Nígbà tí ìbìlù ìrora ikú yí mi káàkiri; tí àwọn ìṣàn ènìyàn búburú dẹ́rùbà mí.
Când valurile morții m-au încercuit, potopurile oamenilor neevlavioși m-au înspăimântat;
6 Ọ̀já isà òkú yí mi káàkiri; ìkẹ́kùn ikú dojúkọ mí. (Sheol h7585)
Întristările iadului m-au încercuit; capcanele morții m-au întâmpinat. (Sheol h7585)
7 “Nínú ìpọ́njú mi, èmi ké pé Olúwa, èmi sì gbé ohùn mi sókè sí Ọlọ́run mi. Ó sí gbóhùn mi láti tẹmpili rẹ̀ igbe mí wọ etí rẹ̀.
În strâmtorarea mea l-am chemat pe DOMNUL și am strigat către Dumnezeul meu; și el mi-a auzit vocea din templul său și strigătul meu a ajuns în urechile lui.
8 Ilẹ̀ sì mì, ó sì wárìrì; ìpìlẹ̀ ọ̀run wárìrì, ó sì mì, nítorí tí ó bínú.
Atunci pământul s-a zguduit și s-a cutremurat; temeliile cerului s-au mișcat și au fost zguduite, pentru că s-a înfuriat.
9 Èéfín ti ihò imú rẹ̀ jáde wá, iná ajónirun ti ẹnu rẹ̀ jáde wá, ẹ̀yin iná bú jáde láti inú rẹ̀.
Un fum s-a înălțat din nările lui și foc mistuia din gura lui; cărbuni s-au aprins prin el.
10 Ó tẹ orí ọ̀run ba pẹ̀lú, ó sì sọ̀kalẹ̀; òkùnkùn biribiri sì ń bẹ ní àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀.
El de asemenea a aplecat cerurile și a coborât; și întuneric era sub picioarele lui.
11 Ó sì gun orí kérúbù, ó sì fò, a sì rí i lórí ìyẹ́ afẹ́fẹ́.
Și călărea pe un heruvim și zbura; și a fost văzut pe aripile vântului.
12 Ó sì fi òkùnkùn ṣe ibùjókòó yí ara rẹ̀, àti àgbájọ omi, àní ìṣúdudu ìkùùkuu àwọ̀ sánmọ̀.
Și a făcut întunericul să fie corturi de jur împrejurul lui, ape întunecoase și nori groși ai cerurilor.
13 Nípasẹ̀ ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ̀ ẹ̀yín iná ràn.
Prin strălucirea de dinaintea sa au fost aprinși cărbuni de foc.
14 Olúwa sán àrá láti ọ̀run wá, Ọ̀gá-ògo jùlọ sì fọhùn rẹ̀.
DOMNUL a tunat din cer și cel Preaînalt și-a înălțat vocea.
15 Ó sì ta ọfà, ó sì tú wọn ká; ó kọ mànàmànà, ó sì ṣẹ́ wọn.
Și a trimis săgeți și i-a împrăștiat; fulgerul și i-a învins.
16 Ìṣàn ibú òkun sì fi ara hàn, ìpìlẹ̀ ayé fi ara hàn, nípa ìbáwí Olúwa, nípa fífún èémí ihò imú rẹ̀.
Și albiile apelor au apărut, temeliile lumii s-au dezgolit, la mustrarea DOMNULUI, la pufnirea suflării nărilor sale.
17 “Ó ránṣẹ́ láti òkè wá, ó mú mi; ó fà mí jáde láti inú omi ńlá wá.
El a trimis din înalt, m-a luat, m-a scos din multe ape.
18 Ó gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá mi alágbára, lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra mi, nítorí pé wọ́n lágbára jù mí lọ.
M-a eliberat de dușmanul meu puternic și de cei ce m-au urât; fiindcă erau prea puternici pentru mine.
19 Wọ́n wá láti borí mi lọ́jọ́ ìpọ́njú mi, ṣùgbọ́n Olúwa ni aláfẹ̀yìntì mi.
M-au întâmpinat în ziua nenorocirii mele, dar DOMNUL a fost sprijinul meu.
20 Ó sì mú mi wá sí ààyè ńlá, ó gbà mi, nítorí tí inú rẹ̀ dún sí mi.
M-a dus de asemenea într-un loc larg; m-a eliberat, pentru că a găsit plăcere în mine.
21 “Olúwa sán án fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi; ó sì san án fún mi gẹ́gẹ́ bí mímọ́ ọwọ́ mi.
DOMNUL m-a răsplătit conform dreptății mele; mi-a întors conform curăției mâinilor mele.
22 Nítorí pé èmi pa ọ̀nà Olúwa mọ́, èmi kò sì fi ìwà búburú yapa kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run mi.
Pentru că am ținut căile DOMNULUI și nu m-am abătut cu stricăciune de la Dumnezeul meu.
23 Nítorí pé gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ ni ó wà níwájú mi; àti ní ti òfin rẹ̀, èmi kò sì yapa kúrò nínú wọn.
Pentru că toate judecățile lui au fost înaintea mea; și cât despre statutele lui, nu m-am depărtat de ele.
24 Èmi sì wà nínú ìwà títọ́ sí í, èmi sì pa ara mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi.
Am fost de asemenea integru înaintea lui și m-am păzit de nelegiuirea mea.
25 Olúwa sì san fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi, gẹ́gẹ́ bí ìwà mímọ́ mi níwájú rẹ̀.
De aceea DOMNUL mi-a întors conform dreptății mele, conform curăției mâinilor mele înaintea ochilor săi.
26 “Fún aláàánú ni ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn ni aláàánú, àti fún ẹni ìdúró ṣinṣin ní òdodo ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn ní ìdúró ṣinṣin ní òdodo.
Cu cel milos te vei arăta milos; și cu omul integru te vei arăta integru.
27 Fún onínú funfun ni ìwọ fi ara rẹ hàn ní funfun; àti fún ẹni wíwọ́ ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn ní wíwọ́.
Cu cel pur te vei arăta pur; și cu cel pervers te vei arăta fără gust.
28 Àwọn ènìyàn tí ó wà nínú ìyà ni ìwọ ó sì gbàlà; ṣùgbọ́n ojú rẹ wà lára àwọn agbéraga, láti rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.
Și pe poporul chinuit îl vei salva; dar ochii tăi sunt asupra celor trufași, ca să îi înjosești.
29 Nítorí ìwọ ni ìmọ́lẹ̀ mi, Olúwa; Olúwa yóò sì sọ òkùnkùn mi di ìmọ́lẹ̀.
Fiindcă tu ești candela mea DOAMNE și DOMNUL îmi va lumina întunericul.
30 Bẹ́ẹ̀ ni nítorí nípa rẹ̀ ni èmi ti la àárín ogun kọjá; nípa Ọlọ́run mi èmi ti fo odi kan.
Căci cu tine am alergat asupra unei cete; și cu Dumnezeul meu am sărit peste zid.
31 “Ọlọ́run yìí, pípé ni ọ̀nà rẹ̀; ọ̀rọ̀ Olúwa ni a ti dánwò. Òun sì ni asà fún gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e.
Cât despre Dumnezeu, calea lui este desăvârșită, cuvântul DOMNULUI este încercat; el este o pavăză pentru toți cei ce se încred în el.
32 Nítorí ta ni Ọlọ́run, bí kò ṣe Olúwa? Ta ni àpáta, bí kò ṣe Ọlọ́run wa.
Căci cine este Dumnezeu în afară de DOMNUL? Și cine este o stâncă în afară de Dumnezeul nostru?
33 Ọlọ́run alágbára ni ó fún mi ní agbára, ó sì sọ ọ̀nà mi di títọ́.
Dumnezeu este tăria și puterea mea; și îmi face calea desăvârșită.
34 Ó ṣe ẹsẹ̀ mi bí ẹsẹ̀ abo àgbọ̀nrín; ó sì mú mi dúró ní ibi gíga mi.
El îmi face picioarele ca ale căprioarei și mă așază pe locurile mele înalte.
35 Ó kọ́ ọwọ́ mi ní ogun jíjà; tó bẹ́ẹ̀ tí apá mi fa ọrun idẹ.
Îmi deprinde mâinile la război, ca brațele mele să frângă un arc de oțel.
36 Ìwọ sì ti fún mi ní asà ìgbàlà rẹ̀; ìrẹ̀lẹ̀ rẹ̀ sì ti sọ mí di ńlá.
Tu de asemenea mi-ai dat scutul salvării tale; și bunătatea ta m-a făcut mare.
37 Ìwọ sì sọ ìtẹ̀lẹ̀ di ńlá ní abẹ́ mi; tó bẹ́ẹ̀ tí ẹsẹ̀ mi kò fi yọ̀.
Mi-ai lărgit pașii sub mine, încât picioarele mele nu au alunecat.
38 “Èmi ti lépa àwọn ọ̀tá mi, èmi sì ti run wọ́n, èmi kò pẹ̀yìndà títí èmi fi run wọ́n.
Am urmărit pe dușmanii mei și i-am nimicit și nu m-am întors înapoi până nu i-am mistuit.
39 Èmi ti pa wọ́n run, èmi sì ti fọ́ wọn, wọn kò sì le dìde mọ́, wọ́n ṣubú lábẹ́ mi.
Și i-am mistuit și i-am rănit, încât nu erau în stare să se ridice; da, sunt căzuți sub picioarele mele.
40 Ìwọ sì ti fi agbára dì mí ní àmùrè fún ìjà; àwọn tí ó ti dìde sí mi ni ìwọ sì ti tẹ̀ lórí ba fún mi.
Fiindcă m-ai încins cu tărie pentru bătălie, ai supus sub mine pe cei ce s-au ridicat împotriva mea.
41 Ìwọ sì mú àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà fún mi, èmi ó sì pa àwọn tí ó kórìíra mi run.
Mi-ai dat de asemenea gâturile dușmanilor mei, ca să îi nimicesc pe cei ce mă urăsc.
42 Wọ́n wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan láti gbà wọ́n; wọ́n wo Olúwa, ṣùgbọ́n kò dá àwọn lóhùn.
Au privit, dar nu era nimeni să îi salveze; strigau chiar către DOMNUL, dar nu le-a răspuns.
43 Nígbà náà ni èmi sì gún wọn wẹ́wẹ́ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, èmi sì tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ bí ẹrẹ̀ ìta, èmi sì tẹ́ wọn gbọrọ.
Atunci i-am pisat mărunt ca țărâna pământului, i-am călcat ca pe noroiul străzii și i-am împrăștiat.
44 “Ìwọ sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ ìjà àwọn ènìyàn mi, ìwọ pa mi mọ́ ki èmi lè ṣe olórí àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè. Àwọn ènìyàn tí èmi kò tí mọ̀ yóò máa sìn mí.
M-ai scăpat de asemenea de luptele poporului meu, m-ai ținut să fiu capul păgânilor, un popor pe care nu l-am cunoscut, mă va servi.
45 Àwọn àjèjì wá láti tẹríba fún mi; bí wọ́n bá ti gbúròó mi, wọ́n á sì gbọ́ tèmi.
Străinii mi se vor supune; imediat ce aud, vor asculta de mine.
46 Àyà yóò pá àwọn àlejò, wọ́n ó sì fi ìbẹ̀rù sá kúrò níbi kọ́lọ́fín wọn.
Străinii se vor ofili și de teamă vor ieși din locurile lor închise.
47 “Olúwa ń bẹ́; olùbùkún sì ni àpáta mi! Gbígbéga sì ni Ọlọ́run àpáta ìgbàlà mi.
DOMNUL trăiește; și binecuvântată fie stânca mea; și să fie înălțat Dumnezeul stâncii salvării mele.
48 Ọlọ́run ni ẹni tí ń gbẹ̀san mi, àti ẹni tí ń rẹ àwọn ènìyàn sílẹ̀ lábẹ́ mi.
Dumnezeu este cel ce îmi face dreptate și care doboară popoarele sub mine,
49 Àti ẹni tí ó gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi. Ìwọ sì gbé mi sókè ju àwọn tí ó kórìíra mi lọ; ìwọ sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọkùnrin oníwà ipá.
Și care mă scoate din mâna dușmanilor mei; tu de asemenea m-ai înălțat deasupra celor ce s-au ridicat împotriva mea; m-ai eliberat de omul violent.
50 Nítorí náà èmi ó fi ọpẹ́ fún ọ, Olúwa, láàrín àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè, èmi ó sì kọrin sí orúkọ rẹ.
De aceea îți voi aduce mulțumiri, DOAMNE, printre păgâni și voi cânta laude numelui tău.
51 “Òun ni ilé ìṣọ́ ìgbàlà fún ọba rẹ̀; ó sì fi àánú hàn fún ẹni àmì òróró rẹ̀, fún Dafidi, àti fún irú-ọmọ rẹ̀ títí láéláé.”
El este turnul salvării pentru împăratul său; și arată milă unsului său, lui David și seminței lui pentru totdeauna.

< 2 Samuel 22 >