< 2 Samuel 16 >
1 Nígbà tí Dafidi sì fi díẹ̀ kọjá orí òkè náà, sì wò ó, Ṣiba ìránṣẹ́ Mefiboṣeti sì ń bọ̀ wá pàdé rẹ̀, òun àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì tí a ti dì ní gàárì, àti igba ìṣù àkàrà lórí wọn, àti ọgọ́rùn-ún síírí àjàrà gbígbẹ, àti ọgọ́rùn-ún èso ẹ̀rún, àti ìgò ọtí wáìnì kan.
Hagi Deviti'a ananteti onasi'a vugamanu ategeno, Mefiboseti eri'za ne' Siba'a Devitina tutagiha hunte'naku eme avega antenegeno ome ke'ne. Hagi agra tare donkifi 200'a breti konagi, fiki raga 100'a konagi, ante hagage hu'nea waini raga'a 100'a konagi huno erineno meme afumofo akru'are tro hu'naza tintafempi waini tina erino emani'ne.
2 Ọba sì wí fún Ṣiba pé, “Kí ni wọ̀nyí?” Ṣiba sì wí pé, “Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ̀nyí ni fún àwọn ará ilé ọba láti máa gùn àti àkàrà yìí, àti èso ẹ̀rún yìí ni fún àwọn ọ̀dọ́mọdékùnrin láti jẹ; àti ọtí wáìnì yìí ni fún àwọn aláàárẹ̀ ní ijù láti mu.”
Hagi kini ne Deviti'a Sibana antahigeno, amazana na'a hu'zane? Higeno Siba'a kenona huno, ama donki afutrena naga kamo'za zanagumpi mani'za vugahaze. Hagi bretine zafa raganena venenemo'za negahaze. Hagi ama waini tina hagage kopima nevanageno tamavresrama hanigeta negahaze.
3 Ọba sì wí pé, “Ọmọ olúwa rẹ dà?” Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Wò ó, ó jókòó ní Jerusalẹmu; nítorí tí ó wí pé, ‘Lónìí ni ìdílé Israẹli yóò mú ìjọba baba mi padà wá fún mi.’”
Hagi kini ne'mo ete antahigeno, inantega kva vahekamofo negeho Mefiboseti'a mani'ne? Higeno Siba'a huno, Agra agesama antahiana menina negeho kini trara namigahaze huno Jerusalemi mani'ne.
4 Ọba sì wí fún Ṣiba pé, “Wò ó, gbogbo nǹkan tí í ṣe ti Mefiboṣeti jẹ́ tìrẹ.” Ṣiba sì wí pé, “Mo túúbá, jẹ́ kí n rí oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ, olúwa mi ọba.”
Hagi kini ne'mo'a Sibana asamino, E'i menina maka Mefiboseti zantamina ete'na kagri kamue. Higeno Siba'a kenona huno, kini ne' ranimoka kagri'ma kavesisia zana amne hugahue.
5 Dafidi ọba sì dé Bahurimu, sì wò ó, ọkùnrin kan ti ibẹ̀ jáde wá, láti ìdílé Saulu wá, orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Ṣimei, ọmọ Gera, ó sì ń bú èébú bí o tí ń bọ̀.
Hagi anama hute'za kini ne'mo'a Bahurimi kumate'ma vigeno, mago ne'mo tutagiha hunte'ne. Ana nera Soli nagapinti ne' Gera nemofo Simeikino ne-eno Devitina kesuno e'ne.
6 Ó sì sọ òkúta sí Dafidi, àti sí gbogbo ìránṣẹ́ Dafidi ọba, àti sí gbogbo ènìyàn, gbogbo àwọn alágbára ọkùnrin sì wà lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀ àti lọ́wọ́ òsì rẹ̀.
Hagi Simei'a have knonu matevuno Devitina neheno, mika Deviti'enema vu'naza vahera nezamaheno, Devitima kegavama hunte'za kanti kamama vu'naza avate hanave sondia vahe'enena zamahe'ne.
7 Báyìí ni Ṣimei sì wí nígbà tí ó ń yọ èébú, “Jáde, ìwọ ọkùnrin ẹ̀jẹ̀, ìwọ ọkùnrin Beliali.
Hagi Simei'a Devitima kema nesuno'a amanage hu'ne, Kagra vahe ahe fri vava hunka vahe kora eri taginka haviza hu'nana vahe mani'nananki, amafintira maniganenka vuo.
8 Olúwa mú gbogbo ẹ̀jẹ̀ ìdílé Saulu padà wá sí orí rẹ, ní ipò ẹni tí ìwọ jẹ ọba; Olúwa ti fi ìjọba náà lé Absalomu ọmọ rẹ lọ́wọ́: sì wò ó, ìwà búburú rẹ ni ó mú èyí wá bá ọ, nítorí pé ọkùnrin ẹ̀jẹ̀ ni ìwọ.”
Hagi kagra Soli naga'ma zamahe frinka, Soli kini trama eri'nana zante menina Ra Anumzamo'a kagrira nona hunegante. Hagi menina negamofo Absalomu kini eri'zana hanare amigenka, frenka ne'ane. Na'ankure kagra vahe zamahe frinka vahe kora eritagi ne' mani'nanku, e'inahu hazenkea eri'ne.
9 Abiṣai ọmọ Seruiah sì wí fún ọba pé, “Èéṣe tí òkú ajá yìí fi ń bú olúwa mi ọba? Jẹ́ kí èmi kọjá, èmi bẹ̀ ọ́, kí èmi sì bẹ́ ẹ́ lórí.”
Anante Zeruia nemofo Abisai'a kini ne' asamino, nahigeno ami fri'nea kramo'a kini ne'moka e'inahu kea kasuno ne-e! Natrege'na ome ahena agenopa akafri'neno.
10 Ọba sì wí pé, “Kín ni èmi ní ṣe pẹ̀lú yín, ẹ̀yin ọmọ Seruiah? Bí ó bá ń bú èébú, nítorí tí Olúwa ti wí fún un pé, ‘Bú Dafidi!’ Ta ni yóò sì wí pé, ‘Kín ni ìdí tí o fi ṣe bẹ́ẹ̀.’”
Hianagi kini ne'mo huno, Ra Anumzamo'ma huntenigeno huhavizama hunenante'na Zeruia nemofoga antahio, tagra magozana hugara osu'none.
11 Dafidi sì wí fún Abiṣai, àti fún gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Wò ó, ọmọ mi tí ó ti inú mi wá, ń wá mi kiri, ǹjẹ́ mélòó mélòó ni ará Benjamini yìí yóò sì ṣe? Fi í sílẹ̀, sì jẹ́ kí o máa yan èébú; nítorí pé Olúwa ni ó sọ fún un.
Anante Deviti'a Abisaine mika eri'za vahe'anena zamasamino, Nagra'ama kasente'noa mofavremo Absalomu'ma nahe'za nehanigeno'a, Benzameni naga'mo'za amane nahegahaze. Hagi Ra Anumzamo asamigeno nehianki, mago'zana osu atrenkeno huhavizana hunanteno.
12 Bóyá Ọlọ́run yóò wo ìpọ́njú mi, Olúwa yóò sì fi ìre san án fún mi ní ipò èébú rẹ̀ lónìí.”
Hagi nagriku'ma haviza hunane huno'ma huhavizama hunanterera, Ra Anumzamo'a nenageno, Agra'a nona huno asomura hunante'nie.
13 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì ń lọ ní ọ̀nà, Ṣimei sì ń rìn òdìkejì òkè tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, ó sì ń yan èébú bí ó ti ń lọ, ó sì ń sọ ọ́ lókùúta, ó sì ń fọ́n erùpẹ̀.
Hagi Deviti'ene naga'amo'za nevazageno Simei'a anagami kaziga nevuno, Devitina kea nesuno kugusopa kateno avufina netreno have kanona atreno aheno vu'ne.
14 Ọba, àti gbogbo àwọn ènìyàn tí ó ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ sì dé Jordani, ó sì rẹ̀ wọ́n, wọ́n sì sinmi níbẹ̀.
Hagi kini ne'ene agranema vu'naza vahe'mo'za zamavaresra hige'za Jodani tinte unehanati'za anante umanigasa hu'naze.
15 Absalomu àti gbogbo àwọn ènìyàn, àwọn ọkùnrin Israẹli sì wá sí Jerusalẹmu, Ahitofeli sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
Hagi ana'ma nehazageno'a, Absalomu'ene maka eri'za vahe'anema Jerusalema ehanati'zageno'a Ahitofeli'a agrane e'ne.
16 Ó sì ṣe, nígbà tí Huṣai ará Arki, ọ̀rẹ́ Dafidi tọ Absalomu wá, Huṣai sì wí fún Absalomu pé, “Kí ọba ó pẹ́! Kí ọba ó pẹ́.”
Hagi Deviti rone'a Akati kumateti ne' Husai'a Absalomuna eme tutagiha hunteno anage hu'ne, Kini nera kagra zazate kinia manigahane!
17 Absalomu sì wí fún Huṣai pé, “Oore rẹ sí ọ̀rẹ́ rẹ ni èyí? Èéṣe tí ìwọ kò bá ọ̀rẹ́ rẹ lọ?”
Hianagi Absalomu'a Husaina antahigeno, Deviti nefuga mani'nananki, kagra nahigenka agranena ovu mani'nane? E'i knare kavukvara negafuna huontane.
18 Huṣai sì wí fún Absalomu pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ nítorí ẹni tí Olúwa, àti gbogbo àwọn ènìyàn yìí, àti gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli bá yàn, tirẹ̀ lèmi ó jẹ́, òun lèmi ó sì bá jókòó.
Higeno Husai'a kenona huno, Ra Anumzamo'ene maka Israeli vahe'mo'za huhamprintesaza kini nemofo agoraga nagra manigahue.
19 Àti pé, ta ni èmi ó sì sìn? Kò ha yẹ kí èmi ó máa sìn níwájú ọmọ rẹ̀? Gẹ́gẹ́ bí èmi ti ń sìn rí níwájú baba rẹ, bẹ́ẹ̀ ni èmi ó sìn níwájú rẹ.”
Hagi nagra negafa antahintahima ami eri'za vahe mani'noankna hu'na kagri eri'za vahe manigahue.
20 Absalomu sì wí fún Ahitofeli pé, “Ẹ bá ará yín gbìmọ̀ ohun tí àwa ó ṣe.”
Hagi Absalomu'a Ahitofelina asamino, Na'a hugahumpi antahi'zana namio.
21 Ahitofeli sì wí fún Absalomu pé, “Wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ lọ, tí ó fi sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé, gbogbo Israẹli yóò sì gbọ́ pé, ìwọ di ẹni ìríra sí baba rẹ, ọwọ́ gbogbo àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ yóò sì le.”
Higeno Ahitofeli'a Absalomuna hunteno, negafana henka a'nezaga'ane umaso. Na'ankure agra nonku'ma kegava hanazegu zamatreno vu'ne. E'inama hananke'za Israeli vahe'mo'za antahisu'za, tamage hunka negafana ha'renentane nehu'za, kagranema mani'naza vahe'mo'za hanaveti'za kagritega antegahaze.
22 Wọ́n sì tẹ́ àgọ́ kan fún Absalomu ní òrùlé; Absalomu sì wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ̀ lójú gbogbo Israẹli.
Higeno nomofo agofetu seli no Absalomuna kintageno, nefama zamatreno vu'nea a'nenea mika Israeli vahe zamavuga zamanteno mase'ne. (2 Samuel 12:11-12.)
23 Ìmọ̀ Ahitofeli tí ó máa ń gbà ni ìgbà náà, ó dàbí ẹni pé ènìyàn béèrè nǹkan lọ́wọ́ Ọlọ́run, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ìmọ̀ Ahitofeli fún Dafidi àti fún Absalomu sì rí.
Hagi ana knafina Ahitofeli'a Ra Anumzamofontegati'ma antahintahima erinoma hiankna ke nehigeno Absalomu'a kote'ma Deviti'ma hu'neankna huno amagera ante'ne.