< 2 Samuel 15 >

1 Lẹ́yìn èyí náà, Absalomu sì pèsè kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin fún ara rẹ̀, àti àádọ́ta ọmọkùnrin tí yóò máa sáré níwájú rẹ̀.
Te phoeiah tah Absalom loh amah ham leng neh marhang neh a hmaiah aka yong la hlang sawmnga te a hmoel.
2 Absalomu sì dìde ní kùtùkùtù, ó sì dúró ní apá kan ọ̀nà ẹnu ibodè. Bí ẹnìkan bá ní ẹjọ́ tí ó ń fẹ́ mú tọ ọba wá fún ìdájọ́, a sì pè é sọ́dọ̀ rẹ̀, a sì bi í pé, “Ará ìlú wo ni ìwọ?” Òun a sì dáhùn pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ti inú ọ̀kan nínú ẹ̀yà Israẹli wá.”
Te phoeiah Absalom te hlah uh tih vongka kah longpuei kaep ah pai. Te vaengah tuituknah a khueh tih manghai mikhmuh kah laitloeknah paan ham aka om hlang carhui te Absalom loh a khue. Te phoeiah, “Nang me kho lamkah lae?” a ti nah hatah, “Na sal he Israel koca pakhat ni,” a ti nah.
3 Absalomu yóò sì wí fún un pé, “Wò ó, ọ̀ràn rẹ ṣá dára, ó sì tọ́, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan tí ọba fi àṣẹ fún láti gbọ́ ọ̀ràn rẹ.”
Te vaengah anih te Absalom loh, “So lah, na ol tah then tih langya dae nang ol te manghai loh a hnatun moenih,” a ti nah.
4 Absalomu a sì wí pé, “À bá jẹ́ fi mi ṣe onídàájọ́ ní ilẹ̀ yìí! Kí olúkúlùkù ẹni tí ó ní ẹjọ́ tàbí ọ̀ràn kan bá à lè máa tọ̀ mí wá, èmi ìbá sì ṣe ìdájọ́ òtítọ́ fún un.”
Te phoeiah khaw Absalom loh, “Khohmuen ah lai aka tloek la kamah he dawk ng'khueh koinih tuituknah aka khueh hlang boeih loh kai taengla ha pawk vetih laitloeknah dongah anih te ka tang sak suidae,” a ti nah.
5 Bẹ́ẹ̀ ni bí ẹnìkan bá sì súnmọ́ láti tẹríba fún un, òun a sì nawọ́ rẹ̀, a sì dìímú, a sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
Te dongah a om nah kung ah anih bawk hamla aka mop hlang boeih te a kut a doe tih a kop phoeiah a mok.
6 Irú ìwà báyìí ni Absalomu a máa hù sí gbogbo Israẹli tí ó tọ́ ọba wá nítorí ìdájọ́, Absalomu sì fi fa ọkàn àwọn ènìyàn Israẹli sọ́dọ̀ rẹ̀.
Hekah olka bangla Absalom loh manghai kah laitloeknah aka paan Israel rhoek boeih taengah a saii. Te dongah Absalom loh Israel hlang rhoek kah lungbuei te a huen pah.
7 Ó sì ṣe lẹ́yìn ogójì ọdún, Absalomu sì wí fún ọba pé, “Èmi bẹ́ ọ́, jẹ́ kí èmi ó lọ, kí èmi sì san ìlérí mi tí èmi ti ṣe fún Olúwa, ní Hebroni.
Kum sawmli a poeng nen tah Absalom loh manghai taengah, “Ka cet mai saeh lamtah Hebron ah BOEIPA taengah ka saii ka olcaeng te ka thuung mai pawn eh.
8 Nítorí tí ìránṣẹ́ rẹ ti jẹ́ ẹ̀jẹ́ kan nígbà tí èmi ń bẹ ní Geṣuri ní Siria pé, ‘Bí Olúwa bá mú mi padà wá sí Jerusalẹmu, nítòótọ́, èmi ó sì sin Olúwa.’”
Aram Geshuri kah kho ka sak vaengah ni na sal loh olcaeng he a caeng coeng. Te vaengah, ‘BOEIPA loh kai he Jerusalem ah m'bal la m'bal puei atah BOEIPA taengah tho ka thueng eh,’ ka ti ta,” a ti nah.
9 Ọba sì wí fún un pé, “Máa lọ ní àlàáfíà.” Ó sì dìde, ó sì lọ sí Hebroni.
Te daengah anih te manghai loh, “Sading la cet ne,” a ti nah. Te dongah thoo tih Hebron la cet.
10 Ṣùgbọ́n Absalomu rán àmì sáàrín gbogbo ẹ̀yà Israẹli pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá gbọ́ ìró ìpè, kí ẹ̀yin sì wí pé, ‘Absalomu jẹ ọba ní Hebroni.’”
Tedae Absalom loh Israel koca boeih taengah longyam a tueih tih, “Tuki ol na yaak uh vaengah, ‘Absalom tah Hebron ah manghai la om coeng,’ ti uh ne,” a ti nah.
11 Igba ọkùnrin sì bá Absalomu ti Jerusalẹmu jáde, nínú àwọn tí a ti pè; wọ́n sì lọ nínú àìmọ̀kan wọn, wọn kò sì mọ nǹkan kan.
Te vaengah Jerusalem lamkah a khue hlang yahnih loh Absalom te a caeh puei. Amih te ngaimong ngaitoe la cet uh dae olka pakhat khaw a ming uh moenih.
12 Absalomu sì ránṣẹ́ pe Ahitofeli ará Giloni, ìgbìmọ̀ Dafidi, láti ìlú rẹ̀ wá, àní láti Giloni, nígbà tí ó ń rú ẹbọ. Ìdìmọ̀lù náà sì le; àwọn ènìyàn sì ń pọ̀ sọ́dọ̀ Absalomu.
David kah olrhoep Giloh Ahithophel te hmueih a nawn na kungah amah kho Giloh lamkah te Absalom loh a tah. Anih neh lairhui te om rhapsat dae pilnam khaw Absalom taengla muep cet.
13 Ẹnìkan sì wá rò fún Dafidi pé, “Ọkàn àwọn ọkùnrin Israẹli ṣí sí Absalomu.”
Te vaengah David taengla aka puen te ha pawk tih, “Israel hlang kah a lungbuei tah Absalom taengla om coeng,” a ti nah.
14 Dafidi sì wí fún gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí ó wá lọ́dọ̀ rẹ̀ ni Jerusalẹmu pé, “Ẹ dìde! Ẹ jẹ́ kí a sálọ, nítorí pé kò sí ẹni tí yóò gbà wá lọ́wọ́ Absalomu; ẹ yára, kí a lọ kúrò, kí òun má bá à yára lé wa bá, kí ó má sì mú ibi bá wa, kí ó má sì fi ojú idà pa ìlú run.”
Te dongah David loh Jerusalem kah amah taengah aka om a sal rhoek boeih te, “Thoo uh lamtah, yong uh pawn sih, Absalom mikhmuh lamloh mamih ham loeihnah om mahpawh, pahoi caeh ham om. Mamih he buengrhuet ng'kae vetih mamih soah yoethae hang heh phoeiah tah khopuei te cunghang ha neh ngawn ve,” a ti nah.
15 Àwọn ìránṣẹ́ ọba sì wí fún ọba pé, “Gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí olúwa wa ọba ń fẹ́, wò ó, àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ ti murá.”
Manghai kah sal rhoek loh manghai te, “Ka boei manghai kah a coelh bangla na sal rhoek boeih ka om uh he,” a ti uh.
16 Ọba sì jáde, gbogbo ilé rẹ̀ sì tẹ̀lé e. Ọba sì fì mẹ́wàá nínú àwọn obìnrin rẹ̀ sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé.
Te phoeiah tah manghai neh a kho kung kah a imkhui pum tah pahoi hlah uh. Tedae a yula huta parha te tah im tawt la manghai loh a caehtak.
17 Ọba sì jáde, gbogbo ènìyàn sì tẹ̀lé e, wọ́n sì dúró ní ibìkan tí ó jìnnà.
Manghai neh a kho kungkah pilnam boeih te hlah uh tih khohla bangsang kah im la pai uh.
18 Gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì kọjá sí iwájú rẹ̀, àti gbogbo àwọn Kereti, àti gbogbo àwọn Peleti, àti gbogbo àwọn ará Gitti, ẹgbẹ̀ta ọmọkùnrin tí ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn láti Gati wá, sì kọjá níwájú ọba.
Te vaengah a kut hmuiah aka pongpa a sal boeih neh Kerethi boeih, Phelethi boeih neh Gath lamloh anih kho kungah aka pongpa Ghitti boeih tah hlang ya rhuk la manghai mikhmuh ah cet uh.
19 Ọba sì wí fún Ittai ará Gitti pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń bá wa lọ pẹ̀lú, padà, kí o sì ba ọba jókòó; nítorí pé àlejò ni ìwọ, ìwọ sì ti fi ìlú rẹ sílẹ̀.
Tedae manghai loh Ghitti Ittai te, “Balae tih, kaimih taengah nang na pongpa he? Mael lamtah manghai taengah ana om ngawn. Nang tah kholong neh na hmuen lamloh m'poelyoe uh nang khaw.
20 Lánàá yìí ni ìwọ dé, èmi ó ha sì mú kí ìwọ máa bá wá lọ káàkiri lónìí bí? Èmi ń lọ sí ibikíbi tí mo bá rí: padà, kí o sì mú àwọn arákùnrin rẹ padà, kí àánú àti òtítọ́ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ.”
Hlaem ah na pawk tih tihnin ah nang he kam poeng khaw kam poeng puei mai aya? Kaimih neh n'caeh vaengah me la ka pawk a khaw ka cet to coeng. Sitlohnah neh oltak la mael lamtah na taengkah na manuca rhoek mael puei laeh,” a ti nah.
21 Ittai sì dá ọba lóhùn, ó sì wí pé, “Bí Olúwa tí ń bẹ láààyè, àti bí olúwa mi ọba ti ń bẹ láààyè, nítòótọ́ níbikíbi tí olúwa mi ọba bá gbé wà, ìbá à ṣe nínú ikú, tàbí nínú ìyè, níbẹ̀ pẹ̀lú ni ìránṣẹ́ rẹ yóò gbé wà.”
Tedae Ittai loh manghai te a doo tih, “BOEIPA kah hingnah neh ka boeipa manghai kah hingnah dongah, ka boeipa manghai te mekah hmuen ah om mai tih, dueknah neh hingnah dongah khaw na sal he ha om bitni,” a ti nah.
22 Dafidi sì wí fún Ittai pé, “Lọ kí o sì rékọjá!” Ittai ará Gitti náà sì rékọjá, àti gbogbo àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn ọmọ kéékèèké tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Tedae David loh Ittai te, “Cet lamtah kat laeh,” a ti nah. Te dongah Ghitti Ittai neh a hlang rhoek boeih, a taengkah camoe boeih te a kat puei.
23 Gbogbo ìlú náà sì fi ohùn rara sọkún, gbogbo ènìyàn sì rékọjá; ọba sì rékọjá àfonífojì Kidironi, gbogbo àwọn ènìyàn náà sì rékọjá, sí ìhà ọ̀nà ijù.
Pilnam te boeih a khum vaengah kho tomah a ol neh bungbung rhap uh. Manghai loh Kidron soklong te a poeng daengah pilnam boeih loh khosoek longpuei kah rhaldan la thoeih uh pueng.
24 Sì wò ó, Sadoku pẹ̀lú àti gbogbo àwọn ọmọ Lefi tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sí ń ru àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wọ́n sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run náà sọ̀kalẹ̀; Abiatari sí gòkè, títí gbogbo àwọn ènìyàn sì fi dẹ́kun àti máa kọjá láti ìlú wá.
Te vaengah Pathen kah paipi thingkawng aka kawt Zadok neh a taengkah Levi boeih long khaw Pathen kah thingkawng te dalh a hal uh. Te dongah khopuei lamkah aka nong ham pilnam te boeih a cing duela Abiathar loh a dom pah.
25 Ọba sì wí fún Sadoku pé, “Sì tún gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run náà padà sí ìlú, bí èmi bá rí ojúrere gbà lọ́dọ̀ Olúwa, yóò sì tún mú mi padà wá, yóò sì fi àpótí ẹ̀rí náà hàn mí àti ibùgbé rẹ̀.
Te vaengah manghai loh Zadok te, “Pathen kah thingkawng he khopuei la mael puei laeh, BOEIPA kah mikhmuh ah mikdaithen ka dang tih kai m'mael puei atah amah neh a tolkhoeng te kai n'tueng bitni.
26 Ṣùgbọ́n bí òun bá sì wí pé, ‘Èmi kò ní inú dídùn sí ọ,’ wò ó, èmi nìyìí, jẹ́ kí òun ó ṣe sí mi gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ ní ojú rẹ̀.”
Tedae, ‘Nang te kang ngaih moenih,’ a ti oeh atah a mikhmuh ah a then a ti bangla kai taengah han saii nawn saeh,” a ti nah.
27 Ọba sì wí fún Sadoku àlùfáà pé, “Aríran ha kọ́ ni ọ́? Padà sí ìlú ní àlàáfíà, àti àwọn ọmọ rẹ méjèèjì pẹ̀lú rẹ, Ahimasi ọmọ rẹ, àti Jonatani ọmọ Abiatari.
Te phoeiah manghai loh khosoih Zadok te, “Na taengkah na ca rhoi, na capa Ahimaaz neh Abiathar capa Jonathan khaw khopuei ah sading la mael puei ham na hmuh a?” a ti nah.
28 Wò ó, èmi ó dúró ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ ijù náà, títí ọ̀rọ̀ ó fi ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá láti sọ fún mi.”
“Ka hmuh, nangmih taeng lamkah ol aka thoeng te kai taengla ha puen hil khosoek kah vahcaeh, kolken ah kan rhing ni,” a ti nah.
29 Sadoku àti Abiatari sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run padà sí Jerusalẹmu, wọ́n sì gbé ibẹ̀.
Te dongah Zadok neh Abiathar loh Pathen kah thingkawng te Jerusalem la a mael puei rhoi tih pahoi om rhoi.
30 Dafidi sì ń gòkè lọ ní òkè igi olifi, o sì ń sọkún bí ó ti ń gòkè lọ, ó sì bo orí rẹ̀, ó ń lọ láìní bàtà ní ẹsẹ̀, gbogbo ènìyàn tí o wà lọ́dọ̀ rẹ̀, olúkúlùkù ọkùnrin sì bo orí rẹ̀, wọ́n sì ń gòkè lọ, wọ́n ń sọkún bí wọ́n ti ń gòkè lọ.
David te olive kham ah a luei. A luei vaengah rhap tih a lu khoep a yil tih khotling la cet. A taengkah pilnam boeih long khaw a lu rhip a yil uh tih a caeh, caeh doela rhap uh.
31 Ẹnìkan sì sọ fún Dafidi pé, “Ahitofeli wà nínú àwọn aṣọ̀tẹ̀ pẹ̀lú Absalomu.” Dafidi sì wí pé, “Olúwa, èmi bẹ̀ ọ́, sọ ìmọ̀ Ahitofeli di asán.”
Te vaengah David taengla a puen pa tih, “Absalom neh aka ven uh rhoek khuiah Ahithophel khaw om,” a ti nah. Te dongah David loh, “BOEIPA aw, Ahithophel kah cilsuep te pavai sak laeh,” a ti.
32 Ó sì ṣe, Dafidi dé orí òkè, níbi tí ó gbé wólẹ̀ sin Ọlọ́run, sì wò ó, Huṣai ará Arki sì wá láti pàdé rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ rẹ̀ yíya, àti erùpẹ̀, lórí rẹ̀.
Som la a pawk vaengah David loh Pathen te a bawk. Te vaengah Arkii Hushai loh a angkidung pawnsoem neh a lu dongah laipi hoeng la David tarha a doe.
33 Dafidi sì wí fún un pé, “Bí ìwọ bá bá mi kọjá, ìwọ ó sì jẹ́ ìdíwọ́ fún mi.
Te dongah anih te David loh, “Kai taengah na pongpa koinih kai ham hnorhih la na om ni.
34 Bí ìwọ bá sì padà sí ìlú, tí o sì wí fún Absalomu pé, ‘Èmi ó ṣe ìránṣẹ́ rẹ ọba, gẹ́gẹ́ bí èmi ti ṣe ìránṣẹ́ baba rẹ nígbà àtijọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi ó sì jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nísinsin yìí,’ kí ìwọ sì bá ìmọ̀ Ahitofeli jẹ́.
Tedae khopuei la na bal tih Absalom taengah, ‘Kai tah manghai nang kah sal la ka om eh, na pa kah sal lam khaw hlamat ah ka om coeng dae nang kah sal la ka om mai pawn eh,’ na ti koinih Ahithophel kah cilsuep te kai ham na phae suidae.
35 Ṣé Sadoku àti Abiatari àwọn àlùfáà wà níbẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀? Yóò sì ṣe, ohunkóhun tí ìwọ bá gbọ́ láti ilé ọba wá, ìwọ ó sì sọ fún Sadoku àti Abiatari àwọn àlùfáà.
Na taengah khosoih Zadok neh Abiathar te a om moenih a? Te daengah man manghai im kah olka na yaak boeih te khosoih Zadok neh Abiathar taengah na thui ve.
36 Wò ó, àwọn ọmọ wọn méjèèjì sì wà níbẹ̀ pẹ̀lú wọn, Ahimasi ọmọ Sadoku, àti Jonatani ọmọ Abiatari; láti ọwọ́ wọn ni ẹ̀yin ó sì rán ohunkóhun tí ẹ̀yin bá gbọ́ sí mi.”
A ca rhoi, Zadok capa Ahimaaz neh Abiathar capa Jonathan khaw amih taengah pahoi om ta ke. Olka na yaak boeih te amih kut lamkah loh kai taengla nam pat mako,” a ti nah.
37 Huṣai ọ̀rẹ́ Dafidi sì wá sí ìlú, Absalomu sì wá sí Jerusalẹmu.
Te dongah David kah olrhoep Hushai loh khopuei te a paan tih Jerusalem kah Absalom taengla kun.

< 2 Samuel 15 >