< 2 Samuel 11 >

1 Lẹ́yìn ìgbà tí ọdún yípo, ní àkókò ìgbà tí àwọn ọba máa ń jáde ogun, Dafidi sì rán Joabu, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, àti gbogbo Israẹli; wọ́n sì pa àwọn ọmọ Ammoni, wọ́n sì dó ti Rabba. Dafidi sì jókòó ní Jerusalẹmu.
Woufo misini, fa: no odemaha, amogalu hina bagade ilia da gegena ahoasu, Da: ibidi da Youa: be amola ea dadi gagui ouligisu dunu amola Isala: ili dadi gagui wa: i, amo gadili asunasi. Ilia da A: mone dunu hasali amola La: ba moilai bai bagadega doagala: lalu. Be Da: ibidi hi da Yelusaleme amoga ouesalu.
2 Ó sì ṣe, ní ìgbà àṣálẹ́ kan, Dafidi sì dìde ní ibùsùn rẹ̀, ó sì ń rìn lórí òrùlé ilé ọba, láti orí òrùlé náà ni ó sì rí obìnrin kan tí ó ń wẹ̀ ara rẹ̀; obìnrin náà sì ṣe arẹwà lójú láti wò.
Eso afaega, daeya agoane, Da: ibidi da golai dialu wa: legadole, hina bagade diasu gadodili fa: i da: iya heda: i. E da amo da: iya ahoanoba, e da uda amo hano ulalebe ba: i. Amo uda da isisima: goi ba: i.
3 Dafidi sì ránṣẹ́ ó sì béèrè obìnrin náà. Ẹnìkan sì wí pé, “Èyí ha kọ́ ni Batṣeba, ọmọbìnrin Eliamu, aya Uriah ará Hiti.”
Amaiba: le, e da amo uda da nowayale hogomusa: , adola ahoasu dunu asunasi. Amo ea hogole ba: loba, amo uda da Ba: desiba, amo Ilaia: me ea idiwi amola Hidaide dunu Iulaia ea idua, e da nabi.
4 Dafidi sì rán àwọn ìránṣẹ́, ó sì mú un; ó sì wọ inú ilé tọ̀ ọ́ lọ, ó sì bá a dàpọ̀, nígbà tí ó sì wẹ ara rẹ̀ mọ́ tán, ó sì padà lọ sí ilé rẹ̀.
Da: ibidi da adola ahoasu dunu ilima amo uda ema oule misa: ne asunasi. Ilia da ema oule misini, ela da gilisili golai. (Amo uda da oubiga wamo fisu dagoiba: le, e da sema dodofesu defele hamoi dagoi ba: i). Amalalu, amo uda da hi diasua buhagi.
5 Obìnrin náà sì lóyún, ó sì ránṣẹ́ ó sì sọ fún Dafidi, ó sì wí pé, “Èmi ti lóyún.”
Amogalu fa: no, Ba: desiba hi ba: loba, e da abula agui ba: i. E da Da: ibidima, e amane hamoi amo adola masa: ne sia: si.
6 Dafidi sì ránṣẹ́ sí Joabu, pé, “Rán Uriah ará Hiti sí mi.” Joabu sì rán Uriah sí Dafidi.
Amalalu, Da: ibidi da Youa: bema amane sia: sia: si, “Hidaide dunu Iulaia amo nama misa: ne asunasima!” Amaiba: le, Youa: be da Iulaia amo Da: ibidima masa: ne adola asi.
7 Nígbà tí Uriah sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, Dafidi sì bi í léèrè báwo ni Joabu ti ṣe àti àlàáfíà àwọn ènìyàn náà, àti bí ogun náà ti ń ṣe.
Iulaia da doaga: loba, Da: ibidi da ema Youa: be amola Isala: ili dadi gagui ilia da habodane esalabeyale, amola gegesu da habodane hamonanebeyale adole ba: i.
8 Dafidi sì wí fún Uriah pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ, kí o sì wẹ ẹsẹ̀ rẹ.” Uriah sì jáde kúrò ní ilé ọba, oúnjẹ láti ọ̀dọ̀ ọba wá sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
Amalalu, Da: ibidi da Iulaia ema amane sia: i, “Di diasua fonobahadi helefimusa: masa!” Iulaia da fisili asili, Da: ibidi da udigili iasu amo ea diasuga iasi.
9 Ṣùgbọ́n Uriah sun ní ẹnu-ọ̀nà ilé ọba lọ́dọ̀ gbogbo ìránṣẹ́ olúwa rẹ̀, kò sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ̀.
Be Iulaia da hi diasua hame asi. E da hina bagade diasu logo holeiga, hina bagade ea sosodo aligisu dunu ili gilisili golai.
10 Nígbà tí wọ́n sì sọ fún Dafidi pé, “Uriah kò sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ̀,” Dafidi sì wí fún Uriah pé, “Ṣe bí ọ̀nà àjò ni ìwọ ti wá? Èéha ti ṣe tí ìwọ kò fi sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ.”
Da: ibidi da Iulaia e hi diasu hame asi amo nababeba: le, e da ema amane adole ba: i, “Di da eso bagohame ga esalu buhagi. Abuliba: le di da di diasua hame asibala: ?”
11 Uriah sì wí fún Dafidi pé, “Àpótí ẹ̀rí, àti Israẹli, àti Juda jókòó nínú àgọ́; àti Joabu olúwa mi, àti àwọn ìránṣẹ́ olúwa mi wà ní ibùdó ní pápá, èmi ó ha lọ sí ilé mi, láti jẹ àti láti mu, àti láti bá obìnrin mi sùn? Bí ìwọ bá wà láààyè, àti bí ẹ̀mí rẹ́ si ti ń bẹ láààyè, èmi kì yóò ṣe nǹkan yìí.”
Iulaia da bu adole i, “Isala: ili dunu amola Yuda dunu da ga gegesa esala. Amola Gousa: su Sema Gagili da ili diala. Na ouligisudafa dunu Youa: be amola ea afoha ouligisu dunu ilia da udigili sogega golasa. Na da habodane na diasu ha: i amola hano naha amola na uda ani gilisili golama: ne masa: ne sia: ma: bela: ? Sema legei amo huluane amoga na da ilegesa! Na da agoaiwane hamomu hamedei ba: sa!”
12 Dafidi sì wí fún Uriah pé, “Sì dúró níhìn-ín lónìí, lọ́la èmi ó sì jẹ́ kí ìwọ ó lọ.” Uriah sì dúró ní Jerusalẹmu ní ọjọ́ náà, àti ọjọ́ kejì.
Amaiba: le, Da: ibidi da amane sia: i, “Amai galea, wali eso guiguda: ouesalu, amola na da aya di bu asunasimu.” Amaiba: le, Iulaia da amo esohaga amola aya esoha Yelusaleme moilai bai bagadega esalu.
13 Dafidi sì pè é, ó sì jẹ, ó sì mú nítorí rẹ̀; ó sì mu kí ọtí pa á; òun sì jáde ní alẹ́ lọ sí ibùsùn rẹ̀ lọ́dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ̀, kò sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ̀.
Da: ibidi da ela gilisili ha: i manusa: hiougi. E da ema adini bagade iabeba: le, Iulaia da feloai. Be amo gasia amola, Iulaia da hi diasua mae asili, hina bagade sosodo aligisu dunu ilia sesei amo ganodini hina: abula sosone diasu amo da: iya golai.
14 Ó sì ṣe ní òwúrọ̀, Dafidi sì kọ̀wé sí Joabu, ó fi rán Uriah.
Golale, hahabe, Da: ibidi da Youa: bema meloa dedei amo, Iulaia ema iasi.
15 Ó sì kọ sínú ìwé pé, “Fi Uriah síwájú ibi tí ogun gbé le, kí ẹ sì fàsẹ́yìn, kí wọn lè kọlù ú, kí ó sì kú.”
E amane dedene i, “Di Iulaia amo gegesu bisili dadaleia amogusu asunasima. Amasea, ha lai dunu ilia e fane legema: ne, adodigilisima.”
16 Ó sì ṣe nígbà tí Joabu ṣe àkíyèsí ìlú náà, ó sì yan Uriah sí ibi kàn ní ibi tí òun mọ̀ pé àwọn alágbára ọkùnrin ń bẹ níbẹ̀.
Amaiba: le, Youa: be da La: ba moilai bai bagadega doagala: lalu, e da Iulaia e sogebi amo ganodini ha lai dunu da gasa bagade gegebe hi dawa: amoga asunasi.
17 Àwọn ọkùnrin ìlú náà sì jáde wá, wọ́n sì bá Joabu jà, díẹ̀ sì ṣubú nínú àwọn ènìyàn náà nínú àwọn ìránṣẹ́ Dafidi, Uriah ará Hiti sì kú pẹ̀lú.
Ha lai dunu da moilaiga gadili asili, Youa: be ea dadi gagui wa: i doagala: i. Da: ibidi ea dadi gagui dunu ouligisu dunu mogili da fane legei dagoi ba: i. Amola Iulaia da fane legei dagoi ba: i.
18 Joabu sì ránṣẹ́ ó sì ro gbogbo nǹkan ogun náà fún Dafidi.
Amalalu, Youa: be da gegesu ea hou olelema: ne, Da: ibidima sia: sia: si.
19 Ó sì pàṣẹ fún ìránṣẹ́ náà pé, “Nígbà tí ìwọ bá sì parí àti máa ro gbogbo nǹkan ogun náà fún ọba.
E da sia: adola ahoasu dunuma amane sia: i, “Di da hina bagade ema gegesu ahoabe hou olelelalu,
20 Bí ó bá ṣe pé, ìbínú ọba bá ru, ti òun sì wí fún ọ pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin fi súnmọ́ ìlú náà láti bá wọn jà, ẹ̀yin kò mọ̀ pé wọn ó tafà láti orí odi wá.
amabela: , e da ougili dima amane adole ba: ma: bela: , `Dilia da abuliba: le moilai gadenene gegemusa: asi. Ilia da dilima dobea amodili gala: mu, amo dilia da hame dawa: bela: ?
21 Ta ni ó pa Abimeleki ọmọ Jerubu-Beṣeti? Kì í ṣe obìnrin ni ó yí òkúta-ọlọ lù ú láti orí odi wá, tí ó sì kú ní Tebesi? Èéha ti rí tí ẹ̀yin fi súnmọ́ odi náà? Ìwọ yóò sì wí fún un pé, Uriah ìránṣẹ́ rẹ ará Hiti kú pẹ̀lú.’”
Abimelege (Gidione egefe) amo ea fane legei hou bu dawa: ma! Dibese moilaiga uda afae dobea da: iya esalu da widi goudasu gele galaguduli e fane legei. Amaiba: le, dilia da abuliba: le dobea gadenene asibala: ?’ Hina bagade da dima agoane adole ba: sea, ema amane adoma, `Dia dadi gagui ouligisu dunu Iulaia, amola da fane legei dagoi ba: i.’”
22 Ìránṣẹ́ náà sì lọ, ó sì wá, ó sì jẹ́ gbogbo iṣẹ́ tí Joabu rán an fún Dafidi.
Amaiba: le, sia: adola ahoasu dunu da Da: ibidima asili, Youa: be ea sia: i defele ema olelei.
23 Ìránṣẹ́ náà sì wí fún Dafidi pé, “Nítòótọ́ àwọn ọkùnrin náà lágbára jù wá lọ, wọ́n sì jáde tọ̀ wá wá ní pápá, àwa sì tẹ̀lé wọn títí wọ́n fi dé ẹ̀yìn odi.
E amane sia: i, “Ha lai dunu ilia gasa da ninia gasa baligi. Ilia da moilai fisili, ninima gegemusa: misi. Be ninia da ili fula ilila: moilai logo holei gelaba gano sese sa: i.
24 Àwọn tafàtafà sì ta sí ìránṣẹ́ rẹ láti orí odi wá, díẹ̀ nínú àwọn ìránṣẹ́ ọba sì kú, ìránṣẹ́ rẹ̀ Uriah ará Hiti sì kú pẹ̀lú.”
Amalalu, ilia da moilai dobea amodili nini dadiga gagala: i. Amola, hina noga: i! Dia dadi gagui ouligisu mogili da fane legei ba: i. Amola dia ouligisu Iulaia amola da fane legei dagoi ba: i.”
25 Dafidi sì wí fún ìránṣẹ́ náà pé, “Báyìí ni ìwọ yóò wí fún Joabu pé, ‘Má ṣe jẹ́ kí nǹkan yìí burú ní ojú rẹ, nítorí pé idà a máa pa lọ́tùn ún lósì, mú ìjà rẹ le sí ìlú náà, kí o sì bì í ṣubú.’ Kí ìwọ sì mú un lọ́kàn le.”
Da: ibidi da sia: adola ahoasu dunuma amane sia: i, “Di Youa: be ea dogo denesima: ma. E mae da: i dioma: ne sia: ma. Bai nowa da gegesu ganodini fane legei dagoi ba: mu, amo ninia dawa: mu da hamedei. E da moilai amo bu gasa bagade doagala: le, hasalima: ne ema sia: ma.”
26 Nígbà tí aya Uriah sì gbọ́ pé Uriah ọkọ rẹ̀ kú, ó sì ṣọ̀fọ̀ nítorí ọkọ rẹ̀.
Bedesiba da egoa fane legei dagoi sia: amo nababeba: le, heawini disa esalu.
27 Nígbà tí ìṣọ̀fọ̀ náà sì kọjá tan, Dafidi sì ránṣẹ́, o sì mú un wá sí ilé rẹ̀, ó sì di aya rẹ̀, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún un, ṣùgbọ́n nǹkan náà tí Dafidi ṣe burú níwájú Olúwa.
Heawini dinana eso da dagoloba, Da: ibidi da Ba: desiba amo hina bagade diasuga misa: ne sia: si. E da Ba: desiba lai, amola ela dunu mano lalelegei. Be Hina Gode da Da: ibidi ea hamoi amo higale ba: i.

< 2 Samuel 11 >