< 2 Kings 9 >

1 Wòlíì Eliṣa fi àṣẹ pe ọkùnrin kan láti ẹgbẹ́ àwọn wòlíì, ó sì wí fún un pé, “Ki agbádá rẹ sínú ọ̀já àmùrè rẹ, gba ṣágo kékeré òróró yìí pẹ̀lú rẹ, kí o sì lọ sí Ramoti Gileadi.
Profet Elisha ni Profet capa thung dawk e buet touh hah a kaw teh, ahni koe, coungkacoe awm la a, hete satuium heh sin nateh Ramothgilead vah cet loe.
2 Nígbà tí o bá dé bẹ̀, wá Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi kiri. Lọ sí ọ̀dọ̀ ọ rẹ̀, mú un kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀, kí o sì mú un wọ inú yàrá lọ́hùn ún lọ.
Na pha toteh, Nimshi ca Jehoshaphat capa, Jehu hah tawng loe, kâen sin nateh a hmaunawnghanaw koehoi tâcawt nateh imrakhan buet touh dawk kâenkhai.
3 Nígbà náà, mú ṣágo kékeré yìí, kí o sì da òróró náà lé e lórí, kí o sì wí pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.”’ Nígbà náà, ṣí ìlẹ̀kùn, kí o sì sáré, má ṣe jáfara!”
Hahoi satuium hah lat nateh, a lû dawk awi pouh. BAWIPA ni hettelah a dei. Isarelnaw koe siangpahrang lah o hanelah nang teh satui na awi. Telah na ti pouh han. Hahoi tho paawng nateh pou yawng takhai, kânawngkâai hanh atipouh.
4 Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀dọ́mọkùnrin náà, wòlíì náà lọ sí Ramoti Gileadi.
Hot patetlah, Profet e san thoundoun teh Ramothgilead vah a cei.
5 Nígbà tí ó dé, ó rí àwọn olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun tí wọ́n jókòó papọ̀. “Èmi ní iṣẹ́ fún ọ, olórí,” Ó wí. “Sí ta ni nínú wa?” Jehu béèrè. Òun sì wí pé, “Sí ọ, balógun,” Ó dáhùn.
A pha toteh, khenhaw! ransabawi hah a tahung, ahni ni yah ransabawi, nang koevah lawk dei han ka tawn atipouh. Jehu ni api koe vaimoe atipouh. Ahni ni ransabawi nang nama koe doeh atipouh.
6 Jehu dìde sókè, ó sì wọ inú ilé lọ. Nígbà náà, wòlíì náà da òróró náà sórí Jehu; ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí àwọn ènìyàn Olúwa Israẹli.
A thaw teh imthungkhu vah a kâenkhai teh, a lû dawk satui hah a awi pouh teh Isarel siangpahrang BAWIPA Cathut ni hettelah a dei, BAWIPA e tamihu Isarel lathueng vah, siangpahrang hanelah satui na awi.
7 Kí ìwọ kí ó pa ilé Ahabu ọ̀gá à rẹ̀ run, Èmi yóò sì gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì àti gbogbo ẹ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ Olúwa tí a ta sílẹ̀ látọwọ́ ọ Jesebeli.
Ka san profetnaw e thi phu hoi BAWIPA e a sannaw e thi phu Jezebel koehoi ka pathung thai nahan lah.
8 Gbogbo ilé Ahabu yóò ṣègbé. Èmi yóò gé e kúrò láti orí Ahabu gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó gbẹ̀yìn ni Israẹli, ẹrú tàbí òmìnira.
Bangtelane tetpawiteh, Ahab imthungkhunaw teh be kahmakata awh vaiteh, Ahab koehoi kamtawng teh a ca tongpa pueng teh, Isarel ram thung hoi kahlout e thoseh, kahlout hoeh e thoseh, be ka pahma han.
9 Èmi yóò ṣe ilé Ahabu gẹ́gẹ́ bí ilé Jeroboamu ọmọ Nebati àti ilé Baaṣa ọmọ Ahijah.
Ahab imthungkhu teh, Nebat capa Jeroboam imthungkhu hoi Ahijah capa Baasha imthungkhu patetlah ka tho sak han.
10 Fún Jesebeli, ajá ni yóò jẹ ẹ́ ní oko Jesreeli, kò sì sí ẹni tí yóò sin òkú rẹ̀.’” Nígbà náà ó ṣí ìlẹ̀kùn, ó sì sálọ.
Uinaw ni Jezebel teh, Jezreel kho kalupnae rapan kung koe a ai vaiteh, kapakawpkung awm mahoeh ati telah atipouh. Hahoi tho a paawng teh a yawng.
11 Nígbà tí Jehu jáde lọ bá àwọn ọgbà ìjòyè e rẹ̀, ọ̀kan nínú wọn sì bi í pé, “Ṣé gbogbo nǹkan dára?” Kí ni ó dé tí aṣiwèrè fi tọ̀ ọ́ wá, “Ìwọ mọ ọkùnrin náà àti irú nǹkan tí ó ń sọ,” Jehu fèsì.
Hot patetlah Jehu teh BAWIPA e a sannaw koe a cei teh tami buet touh ni ahni koe koung ahawi maw, hote tami ka pathu hah, bangkongmaw nang koe a cei atipouh. Ahnimouh ni ama ni a phuenang e teh be na thai awh toung tayaw atipouh.
12 “Ìyẹn kì í ṣe òótọ́!” Wọ́n wí. “Sọ fún wa.” Jehu wí, “Èyí ni ohun tí ó sọ fún mi: ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.”’”
Ahnimouh ni ka thai awh hoeh bo, na dei pouh haw khe, atipouh awh. Hettelah nahoehmaw ka ti pouh awh. BAWIPA ni hettelah a dei Isarelnaw han siangpahrang lah na o nahanelah, satui na awi toe telah a dei e hah patuen dei pouh telah a ti.
13 Wọ́n ṣe gírí, wọ́n sì mú agbádá a wọn, wọ́n sì tàn wọ́n sí abẹ́ rẹ̀ ní orí àtẹ̀gùn. Nígbà náà, wọ́n fọn ìpè, wọ́n sì kígbe, “Jehu jẹ ọba!”
Hahoi tami pueng ni, a hni hah lengkaleng a la awh teh khalai dawk a phai awh. Mongka a ueng awh teh, Jehu teh siangpahrang doeh telah a pathang awh.
14 Bẹ́ẹ̀ ni Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi, dìtẹ̀ sí Joramu. (Nísinsin yìí Joramu àti gbogbo Israẹli ti ń dáàbò bo Ramoti Gileadi nítorí Hasaeli ọba Aramu.
Hahoi Nimshi capa Jehoshaphat capa Jehu ni Joram teh a youk. Siria siangpahrang ni Hazael a taran dawkvah Joram hoi Isarelnaw pueng ni, Ramothgilead kho hah a ring awh.
15 ṣùgbọ́n ọba Joramu ti padà sí Jesreeli láti lọ sàn nínú ọgbẹ́ tí àwọn ará Aramu ti dá sí i lára nínú ogun pẹ̀lú ọba Hasaeli ti Aramu.) Jehu wí pé, “Tí èyí bá jẹ́ ọ̀nà tí ò ń rò, má ṣe jẹ́ kí ẹnìkankan kí ó yọ jáde nínú ìlú ńlá láti lọ sọ ìròyìn náà ní Jesreeli.”
Siangpahrang Joram teh, Siria siangpahrang Hezael hoi a kâtuknae dawk Sirianaw ni hmâ a ca sak awh e naw hah, ahawi nahanlah Jezreel kho vah a ban awh toe. Jehu ni kai koe lah na kampang e lah na awm pawiteh, apihai yah Jezreel kho vah hete lawk dei hanlah kho thung hoi tâcawt awh hanh loe atipouh.
16 Nígbà náà Jehu wọ inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ó sì gùn ún lọ sí Jesreeli, nítorí Joramu ń sinmi níbẹ̀ àti Ahasiah ọba Juda sì sọ̀kalẹ̀ láti wá wò Joramu.
Hahoi Jehu teh, rangleng dawk a kâcui teh, Jezreel kho vah a cei. Bangkongtetpawiteh, Joram teh haw vah a yan. Hahoi Judah siangpahrang Ahaziah hai Joram khet hanlah a cei.
17 Nígbà tí olùṣọ́ kan tí ó dúró ní ilé ìṣọ́ ní Jesreeli, rí ọ̀wọ́ ogun Jehu tí wọ́n ń súnmọ́ tòsí, ó pè jáde, “Mo rí àwọn ọ̀wọ́ ogun tí ó ń bọ̀.” “Mú ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kan,” Joramu pa á láṣẹ. “Rán an lọ sí ọ̀dọ̀ wọn kí o sì béèrè pé, ‘Ṣé ẹ̀yin wá pẹ̀lú àlàáfíà?’”
Jezreel e imrasang van ramveng ni a kangdue teh, ahni ni Jehu hoi a taminaw a tho e hah a hmu. Tami moikapap ka hmu atipouh. Joram ni marang dawk kâcuinaw dawn hanelah patoun haw, roumnae koe la vaimoe, tet pouh haw seh telah atipouh.
18 Ọkùnrin ẹlẹ́ṣin náà, lọ láti lọ bá Jehu ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba wí: ‘Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà?’” “Kí ni ìwọ ní ṣe pẹ̀lú àlàáfíà?” Jehu sì dáhùn. “Bọ́ sí ẹ̀yìn mi.” Olùṣọ́ náà sì wí fún un pé, “Ìránṣẹ́ náà ti dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n kò tún padà wá mọ́.”
Hahoi tami buet touh marang kâcui e ni dawn hanlah a cei. Siangpahrang ni, hettelah a dei, roumnae koe lah vaimoe telah ati. Jehu ni, roumnae lawk hah nang ni na thai hanelah bangmaw kaawm ka hnuklah cet loe atipouh. Hahoi ramveng ni, patoune nang koe a tho vaiyaw, hatei bout ban hoeh toe atipouh.
19 Bẹ́ẹ̀ ni, ọba rán ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kejì. Nígbà náà ó wá sí ọ̀dọ̀ wọn, ó wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba sọ: “Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà?” Jehu dáhùn, “Dúró sí ẹ̀yìn mi.”
Hahoi tami buet touh marang kâcui e bout a patoun. Hot haiyah ahnimouh koe a pha teh, siangpahrang ni telah a dei pouh. Roumnae koelae vaimoe, ati telah ati. Jehu ni, roumnae koe lah teh nang ni na thai han bangmaw kaawm. Ka hnuklah cet ngoun atipouh.
20 Olùṣọ́ náà sì fi sùn. “Ó ti dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n kò tún padà wá mọ́ pẹ̀lú. Wíwá rẹ̀ sì dàbí ti Jehu ọmọ Nimṣi, ó ń wa kẹ̀kẹ́ bí ti aṣiwèrè.”
Ramveng ni, ahni haiyah ama koe ka phat ei nan ma, bout ban hoeh toe. Hahoi a yawng sak e hai, Nimshi capa Jehu ni a yawng sak e patet doeh. Bangkongtetpawiteh, kahlî patetlah doeh thouk a kamleng telah atipouh.
21 “Fi ìwọ̀ kọ́ kẹ̀kẹ́ ogun mi.” Joramu pa á láṣẹ. Àti nígbà tí a fi kọ́, Joramu ọba Israẹli àti Ahasiah ọba Juda, gun kẹ̀kẹ́ lọ, olúkúlùkù nínú kẹ̀kẹ́ ogun tirẹ̀, láti lọ bá Jehu. Wọ́n bá a pàdé ní ibi oko tí ó ti jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli.
Joram ni, coungkacoe lah awm awh telah ati. Leng hah sut a rakueng pouh awh teh, Isarel siangpahrang Joram hoi Judah siangpahrang Ahaziah teh amamouh roi e rangleng reira hoi a tâco roi teh Jehu dawn hanlah a cei roi. Jezreel tami Naboth e takha dawk a kâhro awh.
22 Nígbà tí Joramu rí Jehu, ó béèrè pé, “Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà, Jehu?” “Báwo ni àlàáfíà yóò ṣe wà,” Jehu dáhùn, “Ní ìwọ̀n ìgbà tí gbogbo ìbọ̀rìṣà àti iṣẹ́ àjẹ́ ti màmá rẹ Jesebeli di púpọ̀?”
Hahoi Joram ni, Jehu a kâhmo toteh hettelah doeh, roumnae koelae vaimoe. Jehu atipouh. Ahni ni na manu Jezebel ni hettelah kapap lah a tak a kâyo teh taân a sin e hah maw, bangtelah hoi maw roumnae lah ao thai han vaw atipouh.
23 Joramu yí ọwọ́ rẹ̀ padà, ó sì sálọ, ó sì ń pe Ahasiah, “Ọ̀tẹ̀ dé, Ahasiah!”
Joram teh a kamlang hoi a yawng. Ahaziah koevah na dum awh e doeh Ahaziah atipouh.
24 Nígbà náà, Jehu fa ọrun rẹ̀, ó sì yin Joramu láàrín èjìká méjèèjì. Ọfà náà sì wọ inú ọkàn rẹ̀, ó sì ṣubú lulẹ̀ láti orí kẹ̀kẹ́ rẹ̀.
Jehu ni licung hah a thaothue hoi a sawn teh, Joram teh aloung hoi aloung rahak vah roum a ka pouh teh, pala ni hai a lung pawk a kâ pouh teh, a leng van a kamlei teh a due.
25 Jehu sọ fún Bidikari, balógun kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ pé, “Gbé e sókè kí ó sì jù ú sí orí oko tí ó jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli. Rántí bí èmi àti ìwọ ti ń gun kẹ̀kẹ́ papọ̀ lẹ́yìn Ahabu baba à rẹ nígbà tí Olúwa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀,
Jehu ni, a ransabawi Bidkar koevah dawk tawm nateh Jezreel tami Naboth takha thung tâkhawng. Bangkongtetpawiteh, Ayan vah nang nama hoi na pa Ahab hnuk vah marang kâcui hoi pâlei navah, BAWIPA ni hete hmuenri heh na tak dawk a patue e pahnim hanh.
26 ‘Ní àná, mo rí ẹ̀jẹ̀ Naboti pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ni Olúwa wí.’ Ǹjẹ́ nítorí náà, ẹ gbé e sókè, kí o sì jù ú sí orí ilẹ̀ oko náà ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa.”
BAWIPA ni paduem vah Naboth thi hoi a canaw e thi hah ka hmu toe telah a dei. BAWIPA ni hete hmuen koe roeroe vah lû ka la han telah bout ati. Hot patetlah BAWIPA ni a dei e patetlah hete ro hah tawm nateh hete hmuen koe roeroe tâkhawng telah atipouh.
27 Nígbà tí Ahasiah ọba, Juda rí ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀, ó sálọ sójú ọ̀nà sí Beti-Haggani. Jehu sì lépa rẹ̀, ó ń kígbe, “Pa á pẹ̀lú!” Wọ́n ṣá a ní ọgbẹ́ nínú kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ ní ọ̀nà lọ sí Guri lẹ́bàá a Ibleamu, ṣùgbọ́n ó sálọ sí Megido, ó sì kú síbẹ̀.
Hatei, Judah siangpahrang Ahaziah ni hote hmu toteh, Bethhaggan lah a yawng. Jehu ni a pâlei teh ama haiyah a leng dawk ka ngala awh atipouh. Hahoi Ibleam teng Gur lah takhangnae koe, amae rangleng van vah a ka awh. Megiddo lah a yawng teh haw vah a due.
28 Ìránṣẹ́ rẹ̀ sì gbé e pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ lọ sí Jerusalẹmu, ó sì sin ín pẹ̀lú, baba a rẹ̀ nínú ibojì rẹ̀ ní ìlú ńlá ti Dafidi.
A taminaw ni leng hai Jerusalem lah a ceikhai awh teh a na minnaw koe, Devit khopui vah a pakawp awh.
29 (Ní ọdún kọkànlá ti Joramu ọmọ Ahabu, Ahasiah ti di ọba Juda.)
Ahab capa Joram kum hlaibun touh a bawinae kum vah, Ahaziah teh Judahnaw e siangpahrang lah ao.
30 Nígbà náà Jehu lọ sí Jesreeli. Nígbà tí Jesebeli gbọ́ nípa rẹ̀, ó kun ojú u rẹ̀, ó to irun rẹ̀, ó sì wò jáde láti ojú fèrèsé.
Jehu teh Jezreel kho a kâen navah, Jezebel ni a thai, hahoi teh a mit hah pathoup teh a sam hai a pathoup teh, hlalangaw dawk hoi a radoung.
31 Bí Jehu ti wọ ẹnu ìlẹ̀kùn, ó béèrè, “Ṣé ìwọ wá ní àlàáfíà, Simri, ìwọ olùpa ọ̀gá à rẹ?”
Kalupnae longkha koe Jehu a kâen navah roumnae koe lah vaimoe na bawipa na ka thet e Zimri telah atipouh.
32 Ó gbójú sókè láti wo fèrèsé, ó sì pè jáde, “Ta ni ó wà ní ẹ̀gbẹ́ mi? Ta ni?” Ìwẹ̀fà méjì tàbí mẹ́ta bojú wò ó nílẹ̀.
Ahni ni hlalangaw lah khet hoi kalvan lah radoung hoi, apimaw kai koe lah kambawng telah ati. Tuenla e tami kahni kathum touh ni ahni koe lah a khet awh.
33 Jehu sọ wí pé, “Gbé e jù sílẹ̀!” Wọ́n sì jù ú sílẹ̀. Díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì fọ́n sí ara ògiri àti àwọn ẹṣin bí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ wọn.
Jehu ni napui hah tâkhawng awh telah ati. Hahoi a tâkhawng awh teh siangpahrang im tapang dawk thoseh, marang van hai thoseh a thi naw koung a tâcawn sin, Jehu ni a khok hoi a coungroe.
34 Jehu wọ inú ilé lọ, ó jẹ, ó sì mu. “Tọ́jú obìnrin yẹn tí a fi bú,” Ó wí, “Kí o sì sin ín, nítorí ọmọbìnrin ọba ni ó jẹ́.”
A kâen teh a canei thoebonae kahmawt e napui ka hawi lah kuemyawt awh teh pakawp awh. Bangdawk ahni teh siangpahrang canu doeh a ti.
35 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n jáde lọ láti lọ sin ín, wọn kò rí nǹkan kan àyàfi agbárí i rẹ̀, ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì àti ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì.
Pakawp hanlah a cei navah, lû hru hoi a khokcareinaw hoi a kutcareinaw laipalah teh pâphawng hoeh toe.
36 Wọ́n padà lọ sọ fún Jehu, ẹni tí ó wí pé, “Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah ará Tiṣibi wí pé, ‘Ní orí oko Jesreeli ni àwọn ajá yóò ti jẹ ẹran-ara Jesebeli.
A tho teh a dei pouh awh ahni ni het heh BAWIPA ni a san Tishbit tami Elijah hno lahai Jezreel kalupnae kung koe uinaw ni Jezebel teh a ai han.
37 Òkú Jesebeli yóò dàbí ohun ẹ̀gbin ní orí oko Jesreeli, dé bi pé, ẹnikẹ́ni kì yóò lè sọ pé, “Jesebeli ni èyí.”’”
Jezebel ro teh Jezreel longkha kung koe eitaboung patetlah kaawm han, hethateh Jezebel nan ma aw, ati awh hoeh nahanelah telah dei e lawk doeh telah ati awh.

< 2 Kings 9 >