< 2 Kings 8 >

1 Nísinsin yìí, Eliṣa wí fún obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin jí padà sáyé pé, “Jáde lọ pẹ̀lú ìdílé rẹ kí o sì lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ní ibikíbi tí o bá le dúró sí, nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ní ìlú tí yóò lò tó ọdún méje.”
UElisha wasekhuluma kowesifazana ondodana yakhe ayeyenze yaphila, esithi: Sukuma, uhambe wena lendlu yakho, uyehlala njengowezizwe lapho ongahlala khona njengowezizwe, ngoba iNkosi ibize indlala, ezafika njalo elizweni iminyaka eyisikhombisa.
2 Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ sí lọ, wọ́n sì ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.
Owesifazana wasukuma-ke, wenza njengokutsho komuntu kaNkulunkulu; wahamba yena lendlu yakhe, wahlala njengowezizwe elizweni lamaFilisti iminyaka eyisikhombisa.
3 Ní ẹ̀yìn ọdún méje ó sì padà wá láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ẹ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.
Kwasekusithi ekupheleni kweminyaka eyisikhombisa, owesifazana waphenduka evela elizweni lamaFilisti; waphuma ukuyakhala enkosini ngendlu yakhe langensimu yakhe.
4 Ọba sì ń sọ̀rọ̀ sí Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run pé, “Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá tí Eliṣa ti ṣe.”
Inkosi yayikhuluma-ke loGehazi inceku yomuntu kaNkulunkulu isithi: Akungilandisele izinto zonke ezinkulu uElisha asezenzile.
5 Bí Gehasi ti ń sọ bí tí Eliṣa ṣe jí òkú di alààyè, obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tí Eliṣa ti dá padà sí ayé wá láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. Gehasi sì wí pé, “Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí tí Eliṣa ti jí dìde sí ayé.”
Kwasekusithi esatshela inkosi ukuthi wavusa njani ofileyo, khangela-ke, owesifazana ondodana yakhe ayeyivuse ekufeni wakhala enkosini ngendlu yakhe langensimu yakhe. UGehazi wasesithi: Nkosi yami, nkosi, nguye lo owesifazana, njalo yiyo le indodana yakhe uElisha ayiphilisayo.
6 Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sì sọ fún un. Ó sì yan ìjòyè kan fún ún fún ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì wí fún un pé, “Ẹ fún un padà gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀lú gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ tí ó ti kúrò ní ìlú títí di àsìkò yìí.”
Lapho inkosi ibuza owesifazana, wayilandisela. Inkosi yasimmisela induna ethile, isithi: Buyisela konke okwakungokwakhe, laso sonke isivuno sensimu kusukela mhla esuka elizweni kuze kube lamuhla.
7 Eliṣa lọ sí Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé, “Ènìyàn Ọlọ́run ti wá láti gbogbo ọ̀nà òkè síbí,”
UElisha wasefika eDamaseko, njalo uBenihadadi inkosi yeSiriya wayegula. Wasetshelwa kwathiwa: Umuntu kaNkulunkulu ufikile lapha.
8 ọba sì wí fún Hasaeli pé, “Mú ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, sì lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. Kí o sì béèrè Olúwa láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?”
Inkosi yasisithi kuHazayeli: Thatha esandleni sakho isipho, uyehlangabeza umuntu kaNkulunkulu, ubusubuza eNkosini ngaye usithi: Ngizasila yini kulumkhuhlane?
9 Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó mú lọ pẹ̀lú rẹ̀ ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí ogójì ẹrù ìbákasẹ tí gbogbo ìní tí ó dára jù fún wíwò ti Damasku, ó sì wọlé lọ ó sì dúró níwájú rẹ̀, ó sì wí pé, “Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè pé, ‘Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’”
UHazayeli wasesiyamhlangabeza, wathatha isipho esandleni sakhe, ngitsho esakho konke okuhle kweDamaseko, imithwalo yamakamela engamatshumi amane, weza wema phambi kwakhe, wathi: Indodana yakho uBenihadadi inkosi yeSiriya ingithumile kuwe isithi: Ngizasila yini kulumkhuhlane?
10 Eliṣa da á lóhùn pé, “Lọ kí o lọ sọ fún un pé, ‘Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn mí pé nítòótọ́ òun yóò kùú.”
UElisha wasesithi kuye: Hamba uthi kuye: Ungasila lokusila, kodwa iNkosi ingibonisile ukuthi uzakufa lokufa.
11 Ó sì ranjú mọ́ ọn pẹ̀lú àtẹjúmọ́ gidigidi títí tí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
Wasemjolozela waze waba lenhloni. Umuntu kaNkulunkulu waselila.
12 “Kí ni ó dé tí olúwa mi fi ń sọkún?” Hasaeli béèrè. “Nítorí pé èmi mọ ibi tí ìwọ yóò ṣe sí Israẹli,” ó sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ọ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀lú idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó sì fọ́ wọn túútúú, ìwọ o sì la inú àwọn aboyún wọn.”
UHazayeli wasesithi: Inkosi yami ililelani? Wasesithi: Ngoba ngiyazi ububi ozabenza ebantwaneni bakoIsrayeli; uzathungela inqaba zabo ngomlilo, ubulale amajaha abo ngenkemba, uphahlaze abantwanyana babo, uqhaqhe abesifazana babo abakhulelweyo.
13 Hasaeli sì wí pé. “Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́ẹ̀?” “Olúwa ti fihàn mí pé ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria,” Eliṣa dá a lóhùn.
Kodwa uHazayeli wathi: Kodwa iyini inceku yakho eyinja nje, ukuthi yenze linto enkulu? UElisha wasesithi: INkosi ingibonisile ukuthi uzakuba yinkosi phezu kweSiriya.
14 Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí Beni-Hadadi béèrè, “Kí ni ohun tí Eliṣa sọ fún ọ?” Hasaeli dá a lóhùn, “Ó sọ fún mi wí pé ìwọ yóò sàn nítòótọ́.”
Wasesuka kuElisha weza enkosini yakhe eyathi kuye: UElisha utheni kuwe? Wasesithi: Ungitshele ukuthi uzasila lokusila.
15 Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kejì ó mú aṣọ tí ó nípọn, ó sì kì í bọ inú omi ó sì tẹ̀ ẹ́ sí ojú ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú. Nígbà náà Hasaeli sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Kwasekusithi kusisa wathatha ingubo, wayigxamuza emanzini, wayendlala phezu kobuso bakhe waze wafa. UHazayeli wasesiba yinkosi esikhundleni sakhe.
16 Ní ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà tí Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba Juda.
Njalo ngomnyaka wesihlanu kaJoramu indodana kaAhabi inkosi yakoIsrayeli, lapho uJehoshafathi eyinkosi yakoJuda, uJehoramu indodana kaJehoshafathi inkosi yakoJuda waba yinkosi.
17 Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ.
Wayeleminyaka engamatshumi amathathu lambili lapho esiba yinkosi, wabusa iminyaka eyisificaminwembili eJerusalema.
18 Ó sì rìn ní ọ̀nà ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó sì ṣe ohun búburú níwájú Olúwa.
Wasehamba ezindleleni zamakhosi akoIsrayeli njengokwenza kwendlu kaAhabi, ngoba indodakazi kaAhabi yayingumkakhe; wenza okubi emehlweni eNkosi.
19 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa kò fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́jú ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.
Kodwa iNkosi kayithandanga ukuchitha uJuda ngenxa kaDavida inceku yayo, njengokuthembisa kwayo kuye ukuthi izanika isibane kuye zonke izinsuku, lemadodaneni akhe.
20 Ní àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì gbé ọba tiwọn kalẹ̀.
Ensukwini zakhe iEdoma yahlamuka isuka phansi kwesandla sakoJuda, yabeka inkosi phezu kwayo.
21 Bẹ́ẹ̀ ni Jehoramu lọ sí Sairi pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu sì yí i ká àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró ní òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, sá padà lọ ilé.
UJoramu wasewelela eZayiri lazo zonke inqola zilaye; yena wavuka ebusuku watshaya amaEdoma ayemzingelezele, lenduna zezinqola; labantu babalekela emathenteni abo.
22 Títí ó fi di òní, Edomu wà nínú ọ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ ní àkókò kan náà.
Ngakho iEdoma yahlamuka isuka phansi kwesandla sakoJuda kuze kube lamuhla. Khona iLibhina yahlamuka ngalesosikhathi.
23 Gẹ́gẹ́ bí fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
Ezinye-ke zezindaba zikaJoramu, lakho konke akwenzayo, kakubhalwanga yini egwalweni lwemilando yamakhosi akoJuda?
24 Jehoramu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
UJoramu waselala laboyise, wangcwatshelwa kuboyise emzini kaDavida. UAhaziya indodana yakhe wasesiba yinkosi esikhundleni sakhe.
25 Ní ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.
Ngomnyaka wetshumi lambili kaJoramu indodana kaAhabi inkosi yakoIsrayeli uAhaziya indodana kaJehoramu, inkosi yakoJuda, waba yinkosi.
26 Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní ọdún kan ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli.
UAhaziya wayeleminyaka engamatshumi amabili lambili lapho esiba yinkosi, wabusa umnyaka owodwa eJerusalema. Lebizo likanina lalinguAthaliya, indodakazi kaOmri inkosi yakoIsrayeli.
27 Nígbà tí ó rin ọ̀nà ilé Ahabu ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó sí ìdílé Ahabu.
Wasehamba ngendlela yendlu kaAhabi, wenza okubi emehlweni eNkosi, njengendlu kaAhabi, ngoba wayengumkhwenyana wendlu kaAhabi.
28 Ahasiah sì lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu lọ sí ogun lórí Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀.
Wasehamba loJoramu indodana kaAhabi ukulwa loHazayeli inkosi yeSiriya eRamothi-Gileyadi; amaSiriya aselimaza uJoramu.
29 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Joramu padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí ará Siria ti jẹ ní yà lórí rẹ̀ ní Ramoti ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Aramu. Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí tí ó fi ara pa.
UJoramu inkosi wabuyela ukwelatshwa eJizereyeli amanxeba amaSiriya ayemtshaye wona eRama ekulweni kwakhe loHazayeli inkosi yeSiriya. UAhaziya indodana kaJehoramu inkosi yakoJuda wasesehla ukubona uJoramu indodana kaAhabi eJizereyeli, ngoba wayegula.

< 2 Kings 8 >