< 2 Kings 8 >
1 Nísinsin yìí, Eliṣa wí fún obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin jí padà sáyé pé, “Jáde lọ pẹ̀lú ìdílé rẹ kí o sì lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ní ibikíbi tí o bá le dúró sí, nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ní ìlú tí yóò lò tó ọdún méje.”
Elisha’n achapa thisa ahindohsa peh numeinu kom’ah chun hitin anaseijin ahi, “Na insungmite kipuijin lang munchom dang khatna chetan ajeh chu Pakaiyin Israel chunga kum sagi kel alhah sahding ahi,” ati.
2 Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ sí lọ, wọ́n sì ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.
Hijeh chun Pathen mipan aseibang bangin numeinu chun aboltan ahi. Amanun ainsung mite apuidohin Philistine gam’ah kum sagi aga cheng tan ahi.
3 Ní ẹ̀yìn ọdún méje ó sì padà wá láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ẹ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.
Kellhah akichai jouvin Philistine gam’ah konin ainlam ah ahung kile kit tan ahi. Ain leh agam nungmu kitna dingin lengpa kom’ah achen ahi.
4 Ọba sì ń sọ̀rọ̀ sí Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run pé, “Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá tí Eliṣa ti ṣe.”
Hitia chu amanu lengpa kom’a agalut chun, lengpa chu Pathen mipa sohpa Gehazi chutoh ana kihoulim pet ahin, lengpa chun Gehazi kom’ah chun, “Elisha thilbol kidangho phabep neiseipeh in,” anatin ahi.
5 Bí Gehasi ti ń sọ bí tí Eliṣa ṣe jí òkú di alààyè, obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tí Eliṣa ti dá padà sí ayé wá láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. Gehasi sì wí pé, “Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí tí Eliṣa ti jí dìde sí ayé.”
Chule Gehazi chun, Elisha in chapang thisa khat ahindoh sah kit thu chu ana seipeh in ahi. Hichepet tah chun hiche chapangpa nuchu lengpa kom’ah tao dingin ahunglut in ahi.
6 Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sì sọ fún un. Ó sì yan ìjòyè kan fún ún fún ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì wí fún un pé, “Ẹ fún un padà gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀lú gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ tí ó ti kúrò ní ìlú títí di àsìkò yìí.”
Lengpan numeinu chu adongin, “Hichu dih hinam?” ati. Hichun amanun athusim chu aseipeh tai. Chuin lengpa anoija natong pipui ho khat chu akouvin numeinu thil le lo hochu ale chan kitna dinga agontoh peh dingin anganse tan ahi.
7 Eliṣa lọ sí Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé, “Ènìyàn Ọlọ́run ti wá láti gbogbo ọ̀nà òkè síbí,”
Elisha chu Ben-hadad damlouva alupna Syria khopi Damascus a chun achen ahi. Mikhat in lengpa kom’ah chun Pathen mipa ahunge tia aseipeh phat chun,
8 ọba sì wí fún Hasaeli pé, “Mú ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, sì lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. Kí o sì béèrè Olúwa láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?”
Lengpan Hazael kom’ah chun, “Kipa thilpeh khat chu choijinlang Pathen mipa chu gapenlang, chule hiche kanat na akona hi kadamdoh ding hinam? Pakai chu eidoh pehtan,” tin asollin ahi.
9 Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó mú lọ pẹ̀lú rẹ̀ ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí ogójì ẹrù ìbákasẹ tí gbogbo ìní tí ó dára jù fún wíwò ti Damasku, ó sì wọlé lọ ó sì dúró níwájú rẹ̀, ó sì wí pé, “Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè pé, ‘Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’”
Hiti chun Hazael chun sangonsang somli chu Damascus a thilsoh phapen ho chutoh, Elisha kom’a achen, hitin aseitan ahi, “Nasohpa Benhadad Syria lengpan nangkom’a eihinsol ahi chule hiche kanat na akona hi kadamdoh ding hi nam? tin eiga dohpeh in atia eihinsol ahi,” atin ahileh,
10 Eliṣa da á lóhùn pé, “Lọ kí o lọ sọ fún un pé, ‘Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn mí pé nítòótọ́ òun yóò kùú.”
Elishan adonbut in, “Chenlang hiti hin gasei peh tan, nangma nadamdoh teiding ahi, tihi Pakaiyin atahbeh in eimusah in ahi, ahinla amavang thitei ding ahi!” ati.
11 Ó sì ranjú mọ́ ọn pẹ̀lú àtẹjúmọ́ gidigidi títí tí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
Hichun Elisha’n Hazael chun nommo asah tokah sen mitlha louhellin avechang mellin, chujouvin Pathen mipa chu ahung kaplha jengtan ahi.
12 “Kí ni ó dé tí olúwa mi fi ń sọkún?” Hasaeli béèrè. “Nítorí pé èmi mọ ibi tí ìwọ yóò ṣe sí Israẹli,” ó sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ọ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀lú idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó sì fọ́ wọn túútúú, ìwọ o sì la inú àwọn aboyún wọn.”
“Ipithu hitam kapu!” tin, Hazael’in adongin ahile, Elisha in adonbut in, “Nangman Israelte chunga thil tijat um tahtah hohi nahin tohding kahen ahi. Nangin kul kiget khum akhopi hou nahin hal lhahding, agollhanghou chemjamma nahin ban satlih gamding, achapang teu toltoh nahin chotnat ding, anumei hou agailai nahin khojalding hi kahe in ahi,” ati.
13 Hasaeli sì wí pé. “Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́ẹ̀?” “Olúwa ti fihàn mí pé ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria,” Eliṣa dá a lóhùn.
Hazael lin adonbut in, “Keitobang imacha hilou khat mai maijin chutobang thil nasa chu katoh thei ding ham?” ati. Ahin Elisha’n adonbut in, “Nangma Syria leng nahung hiding ahite Pakaiyin eimusah in ahi,” ati.
14 Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí Beni-Hadadi béèrè, “Kí ni ohun tí Eliṣa sọ fún ọ?” Hasaeli dá a lóhùn, “Ó sọ fún mi wí pé ìwọ yóò sàn nítòótọ́.”
Hazael in Elisha adalhan lengpa kom ah akile kittan ahi, hicun lengpa jong ama kom ah chun, “Elisha ipi nahin seipeh em?” tin anadongin ahi. Hazael in adonbut in, “Nangma hi nadamdoh tei ding ahi tin aman eiseipeh e.” ati.
15 Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kejì ó mú aṣọ tí ó nípọn, ó sì kì í bọ inú omi ó sì tẹ̀ ẹ́ sí ojú ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú. Nígbà náà Hasaeli sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Ahinlah ajing nikhon Hazael in ponlum twiya asu-kotin amai akhun athi tokah in amai ah akhuden pehtan ahi. Hijouchun Hazael chun Syria te leng achangin Benhadad akheltan ahi.
16 Ní ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà tí Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba Juda.
Israel lengpa Ahab chapa Joram vaihom kum nga channa in Judah te leng Jehoshaphat chapa Jehoram min Judahte chunga vai ana homin ahi.
17 Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ.
Jehoram hi leng ahung hichun ama kum somthum le ni ana lhingtan amahin Jerusalem mah kum get lengvai anapon ahi.
18 Ó sì rìn ní ọ̀nà ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó sì ṣe ohun búburú níwájú Olúwa.
Jehoram hin Israel lengte chonchan ajuijin Ahab lengpa phatmo tobang'in aphamon ahi. Ajeh chu aman Ahab chanu ho lah’a khat ana kichenpin ahi. Hiti chun Jehoram hin Pakai mitmu’n thilsejing ana bollin ahi.
19 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa kò fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́jú ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.
Ahinlah Pakaiyin Judah mite ana sumang nompon ahi, ajeh chu aman David toh kitepna ana neijin achilhah ten vai ahopjom ding chule aitih a thaomei banga vahjing dinga anatep peh ahi.
20 Ní àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì gbé ọba tiwọn kalẹ̀.
Jehoram vaihom sungin, Edomten Judah dounan gal ahin bollun, leng atum’in ahin kitundoh tauvin ahi.
21 Bẹ́ẹ̀ ni Jehoramu lọ sí Sairi pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu sì yí i ká àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró ní òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, sá padà lọ ilé.
Hichun Jehoram in asakol kangtalai chengse chutoh akon un Zair khopi aga nokhum tauvin ahi. Ahin Edom miten asakol kangtalai chule gal lamkaiho chu ahin umkhum tauvin ahileh ama jong jan noiya chun apotdohin amaho chu jan muthim noija chun adelkhum min ahi. Ahinlah Jehoram chu asepaiten ajam sannun ainlam uvah ana jam san tauvin ahi.
22 Títí ó fi di òní, Edomu wà nínú ọ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ ní àkókò kan náà.
Hitihin Edom miten tuni changeiyin Judah a konin chamlhatna ana mutauvin ahi. Libnah khopi injong hichephat sunga chun kiphinna ahin neijun ahi.
23 Gẹ́gẹ́ bí fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
Jehoram vaihom sunga thilsoh holeh natoh dohho jouse Judah lengte thusim bua akijihlut soh keijin ahi.
24 Jehoramu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Jehoram athi phat chun, David khopia apu apate toh akivui khom’in ahi.
25 Ní ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.
Ahab chapa Joram lengvai poh kum somle ni channa a hin, Jehoram chapa Ahaziah hin Judah chungah lengvai ana po in ahi.
26 Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní ọdún kan ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli.
Ahaziah hi leng ahung chan chun ama kum somni le ni alhingin chuleh amahin, Jerusalem ah kum khat vai ana hom’in ahi. Anuchu Israel leng Omri tunu Athaliah ahi.
27 Nígbà tí ó rin ọ̀nà ilé Ahabu ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó sí ìdílé Ahabu.
Ahaziah chun Ahab lengpa insung mite chondan dihlou chu ana juiyin ahi. Aman Pakai mitmu’n thiphalou ngen ana bollin ahi. Ajeh chu aman Ahab insung ana kichenpi in ahi.
28 Ahasiah sì lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu lọ sí ogun lórí Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀.
Ahaziah hin Israel lengpa Ahab chapa Joram chu Ramoth-gilead munnah Syria lengpa Hazael te kisat dingin ana pan khompi in ahi. Syriaten Joram lengpa chu gal kisatna munnah ana kisuhkhah jeh chun,
29 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Joramu padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí ará Siria ti jẹ ní yà lórí rẹ̀ ní Ramoti ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Aramu. Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí tí ó fi ara pa.
Jezreel langah akisuh khahna a adamna dingin ana kinunglen, Ramoth kho ah ana lamto un ahi. Hitia chu Joram ana kisuhkhah jeh'in, Judah lengpa Ahaziah chu ama veding in Jezreel langa anachen ahi.