< 2 Kings 6 >

1 Àwọn ọmọ wòlíì sọ fún Eliṣa pé, “Wò ó, ní ibi tí a ti pàdé pẹ̀lú rẹ, ó kéré fún wa.
Na ka mea nga tama a nga poropiti ki a Eriha, Nana, ko te wahi e noho nei matou i tou aroaro he kuiti rawa mo tatou.
2 Jẹ́ kí àwa kí ó lọ sí Jordani, ní ibi tí ẹnìkọ̀ọ̀kan ti le rí ọ̀pá kan, jẹ́ kí àwa kí ó kọ́lé síbẹ̀ fún wa láti gbé.” Ó sì wí pé, “Lọ.”
Tena, tukua matou kia haere ki Horano, ki te tango kurupae mai i reira, tenei, tenei o matou, ka hanga ai i tetahi wahi i reira hei nohoanga mo tatou. A ka whakahokia e ia, Haere koutou.
3 Nígbà náà ni ọ̀kan lára wọn wí pé, “Kí ó wù ọ́, èmí bẹ̀ ọ́, láti bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ lọ?” Eliṣa dá a lóhùn pé, “Èmi yóò lọ,”
Na ka mea tetahi, Tena, whakaae mai kia haere koe i au pononga. Ano ra ko ia, Ka haere ano ahau.
4 Ó sì lọ pẹ̀lú wọn. Wọ́n sì lọ sí Jordani wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní gé igi.
Heoi haere ana ia i a ratou. I to ratou taenga ki Horano, kei te topetope rakau.
5 Bí ọ̀kan ṣe gé igi náà, àáké irin náà bọ́ sínú omi, ó kígbe sókè pé, “O! Olúwa mi, mo yá a ni!”
Otiia i tetahi e tua ana i te rakau, ka marere te pane o te toki ki te wai: na ka karanga ia, ka mea, Aue, e toku ariki! he toki na te tangata.
6 Ènìyàn Ọlọ́run sì béèrè pé, “Níbo ni ó bọ́ sí?” Nígbà tí ó fi ibẹ̀ hàn án, Eliṣa gé igi kan ó sì jù ú síbẹ̀, ó sì mú irin náà fò lójú omi.
Na ka mea te tangata a te Atua, Tena koa te wahi i marere ai? A ka whakaaturia e ia ki a ia te wahi. Na tapahia ana e ia tetahi rakau, a maka ana ki reira, na kua manu taua rino.
7 Ó wí pé, “Gbé e jáde.” Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà na ọwọ́ rẹ̀ jáde ó sì mú un.
Na ka mea ia, Tangohia ki a koe. Na ka totoro tona ringa, a tangohia ana e ia.
8 Nísinsin yìí ọba Aramu wà ní ogun pẹ̀lú Israẹli ó sì bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ gbèrò, ó wí pé, “Èmi yóò ṣe ibùdó mi sí ibí yìí nínú èyí náà àti bí ibí yìí.”
Na ka whawhai te kingi o Hiria ki a Iharaira; a ka whakatakoto whakaaro ia ki ana tangata, ka mea, Ko te wahi hei puni moku, kei mea.
9 Ènìyàn Ọlọ́run rán iṣẹ́ sí ọba Israẹli pé, “Kíyèsi ara láti kọjá ní ibẹ̀ yẹn, nítorí pé ará Aramu wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ síbẹ̀.”
Na ka tono tangata te tangata a te Atua ki te kingi o Iharaira ki te ki atu, Kia tupato kei tika koe na taua wahi: kei te haere hoki nga Hirianai ki raro, ki reira.
10 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli wo ibi tí ènìyàn Ọlọ́run náà fihàn, ní ẹ̀ẹ̀kan sí i Eliṣa kìlọ̀ fún ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó wà lórí sísọ ní ibẹ̀.
Na ka unga tangata te kingi o Iharaira ki te wahi i kiia ra e te tangata a te Atua ki a ia, i whakatupato ai ia i a ia; a ka honea ia i reira, ehara ano i te tuatahi, i te tuarua ranei.
11 Èyí mú ọba Aramu bínú. Ó pe àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ṣé ìwọ kò ní sọ fún mi èwo nínú wa ni ó wà ní ẹ̀gbẹ́ ọba Israẹli?”
Na pohewa noa iho te ngakau o te kingi o Hiria i tenei mea; a ka karangatia e ia ana tangata, ka mea ki a ratou, E kore ianei koutou e whakaatu ki ahau, ko wai o tatou kei te kingi o Iharaira?
12 Ọ̀kan lára ìránṣẹ́ rẹ̀ sì wí pé, “Kò sí ọ̀kan nínú wa, olúwa ọba mi, ṣùgbọ́n Eliṣa, wòlíì tí ó wà ní Israẹli, sọ fún ọba Israẹli ọ̀rọ̀ gangan tí ó sọ nínú yàrá rẹ̀.”
Ka mea tetahi o ana tangata, Kahore, e toku ariki, e te kingi; engari ko Eriha, ko te poropiti kei roto i a Iharaira, kei te whakaatu ki te kingi o Iharaira i nga kupu e korero ai koe i tou whare moenga.
13 Ọba pa á láṣẹ, “Lọ, kí ẹ lọ wo ibi tí ó wà, kí èmi kí ó lè rán ènìyàn láti lọ mú un wá.” Ìròyìn padà wá wí pé, “Ó wà ní Dotani.”
Na ka mea ia, Tikina, tirohia, kei hea ia, kia unga ai e ahau he tangata ki te tiki i a ia. A ka korerotia ki a ia, Nana, kei Rotana.
14 Nígbà náà ni ó rán àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ àti ogun ńlá tí ó le síbẹ̀. Wọ́n sì lọ ní alẹ́ wọ́n sì yí ìlú náà ká.
Na tonoa ana e ia ki reira he hoiho, he hariata, me tetahi ope nui: a haere po ana ratou, karapotia ana te pa.
15 Nígbà tí ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run dìde ó sì jáde lọ ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, ogun pẹ̀lú ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ wọn ti yí ìlú náà ká. “Yé è, olúwa mi! Kí ni kí àwa kí ó ṣe?” ìránṣẹ́ náà béèrè.
Na, i te marangatanga o te kaimahi a te tangata a te Atua i te ata tu, i te putanga ki waho, na, he taua e karapoti ana i te pa, me nga hoiho, me nga hariata. Na ka mea tana tangata ki a ia, Aue, e toku ariki, me aha tatou?
16 “Má ṣe bẹ̀rù,” wòlíì náà dáhùn, “Àwọn tí ó wà pẹ̀lú wa, wọ́n pọ̀ ju àwọn tí ó wà pẹ̀lú wọn lọ.”
Ano ra ko ia, Kaua e wehi; hira ake hoki o tatou hoa i o ratou hoa.
17 Eliṣa sì gbàdúrà, “Olúwa, la ojú rẹ̀ kí ó ba à lè ríran.” Nígbà náà Olúwa la ojú ìránṣẹ́ náà, ó sì wò, ó sì rí òkè ńlá tí ó kún fún ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ iná gbogbo yí Eliṣa ká.
Na ka inoi a Eriha, a ka mea, E Ihowa, kia titiro ona kanohi, kia kite ai ia. Na whakatirohia ana nga kanohi o taua taitamariki; a ka kite ia; na, kapi tonu te maunga i te hoiho, i te hariata ahi i nga taha katoa o Eriha.
18 Bí àwọn ọ̀tá ṣe ń sọ̀kalẹ̀ wá níwájú rẹ, Eliṣa gbàdúrà sí Olúwa pé. “Bu ìfọ́jú lu àwọn ènìyàn wọ̀nyí,” Olúwa sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Eliṣa ti béèrè.
Na, i to ratou haerenga ki raro ki a ia, ka inoi a Eriha ki a Ihowa, ka mea, Tena ra, patua tenei iwi kia matapo. Na patua ana ratou e ia kia matapo, pera tonu ia me ta Eriha i ki ai.
19 Eliṣa sọ fún wọn pé, “Èyí kì í ṣe ọ̀nà bẹ́ẹ̀ ni èyí kì í ṣe ìlú náà. Tẹ̀lé mi, èmi yóò mú u yín lọ sí ọ̀dọ̀ ọkùnrin tí ẹ̀yin ń wá.” Ó sì sìn wọ́n lọ sí Samaria.
Na ka mea a Eriha ki a ratou, Ehara tenei i te huarahi, ehara hoki tenei i te pa: whai mai i ahau, a maku koutou e arahi ki ta koutou tangata e rapu nei. A arahina ana ratou e ia ki Hamaria.
20 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n wọ ìlú náà, Eliṣa wí pé, “Olúwa, la ojú àwọn ọkùnrin wọ̀nyí kí wọn kí ó lè ríran.” Nígbà náà Olúwa la ojú wọn, wọ́n sì ríran, wọ́n sì wà níbẹ̀, nínú Samaria.
A, no te taenga ki Hamaria, ka mea a Eriha, E Ihowa, whakatirohia nga kanohi o enei, kia kite ai ratou. Na whakatirohia ana e Ihowa o ratou kanohi, a ka kite ratou; na, i waenganui pu ratou o Hamaria.
21 Nígbà tí ọba Israẹli rí wọn, ó béèrè lọ́wọ́ Eliṣa pé, “Ṣé kí èmi kí ó pa wọ́n, baba mi? Ṣé kí èmi kí ó pa wọ́n?”
Na ka mea te kingi o Iharaira ki a Eriha, i tona kitenga i a ratou, Kia patua e ahau, e toku papa? kia patua e ahau?
22 “Má ṣe pa wọ́n,” ó dáhùn. “Ṣé ìwọ yóò pa àwọn ọkùnrin tí ìwọ mú pẹ̀lú idà rẹ tàbí ọrun rẹ? Gbé oúnjẹ àti omi síwájú wọn kí wọn kí ó lè jẹ kí wọn sì mu, nígbà náà kí wọn padà lọ sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá wọn.”
Ano ra ko ia, Kaua e patua e koe. E patua ranei e koe au i hopu ai ki tau hoari, ki tau kopere? Whakatakotoria he taro, he wai ki o ratou aroaro, kia kai ratou, kia inu, kia hoki ki to ratou ariki.
23 Bẹ́ẹ̀ ni ó pèsè àsè ńlá fún wọn, lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n jẹ tí wọ́n mu, ó sì rán wọn lọ, wọ́n sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá wọn. Bẹ́ẹ̀ ni ẹgbẹ́ láti Aramu dáwọ́ ìgbógunti ilẹ̀ Israẹli dúró.
Na taka ana e ia he kai ma ratou, he nui: a, ka kai ratou, ka inu, ka tonoa atu ratou e ia, a haere ana ratou ki to ratou ariki. Na heoi ano haerenga mai o nga taua a nga Hiriani ki te whenua o Iharaira.
24 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ni Beni-Hadadi ọba Aramu kó gbogbo àwọn ogun rẹ̀ jọ wọ́n sì yan sókè wọ́n sì dúró ti Samaria.
Na, muri iho i tenei, ka huihuia e Peneharara kingi o Hiria tana ope katoa, a haere ana, whakapaea ana a Hamaria.
25 Ìyàn ńlá sì mú ní ìlú Samaria; wọ́n dúró tí ì tó bẹ́ẹ̀ tí a fi ń ta orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan ní ọgọ́rùn-ún ìwọ̀n fàdákà àti ìdámẹ́rin òsùwọ̀n kábù imí ẹyẹlé, fún ìwọ̀n fàdákà márùn-ún.
Na nui atu te matekai o Hamaria: na, whakapaea ana a reira e ratou, nawai a ka hokona te upoko kaihe mo nga pihi hiriwa e waru tekau, te wahi wha hoki o te kapa paru kukupa mo nga pihi hiriwa e rima.
26 Gẹ́gẹ́ bí ọba Israẹli ti ń kọjá lọ lórí odi, obìnrin kan sọkún sí i pé, “Ràn mí lọ́wọ́, olúwa ọba mi!”
Na, i te kingi o Iharaira e haere ana na runga i te taiepa, ka karanga tetahi wahine ki a ia, ka mea, Whakaorangia, e te ariki, e te kingi.
27 Ọba sì dá a lóhùn pé, “Bí Olúwa kò bá gbà ọ́, níbo ni èmi yóò gbé ti gbà ọ́? Láti inú ilẹ̀ ìpakà, tàbí láti inú ibi ìfúntí?”
Ano ra ko ia, Ka kore nei a Ihowa e whakaora i a koe, kei hea he mea maku hei whakaora i a koe? kei te tapunga witi ranei? kei te poka waina ranei?
28 Nígbà náà ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà pé, “Kí ni ó ṣẹlẹ̀?” Obìnrin náà dáhùn pé, “Obìnrin yìí wí fún mi pé, ‘Mú ọmọkùnrin rẹ wá kí àwa kí ó lè jẹ ẹ́ lónìí, ní ọ̀la àwa yóò jẹ ọmọkùnrin tèmi.’
A ka mea te kingi ki a ia, He aha tau? Ano ra ko ia, I mea mai te wahine nei ki ahau, Homai tau tama hei kai ma taua aianei, a hei apopo ka kai taua i taku tama.
29 Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe ọmọkùnrin mi a sì jẹ ẹ́. Ní ọjọ́ kejì mo wí fún un pé, ‘Mú ọmọkùnrin rẹ wá kí àwa kí ó lè jẹ,’ ṣùgbọ́n ó ti gbé e pamọ́.”
Heoi kohuatia ana e maua taku tama, kainga ana e maua: na i te aonga ake ka mea atu ahau ki a ia, Homai tau tama kia kainga e taua: na kua huna e ia tana tama.
30 Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ obìnrin náà, ó fa aṣọ rẹ̀ ya. Gẹ́gẹ́ bí ó sì ti ń kọjá lọ sí orí odi, àwọn ènìyàn wò ó níbẹ̀ ní abẹ́, ó ní aṣọ ọ̀fọ̀ ní ara rẹ̀.
Na, i te rongonga o te kingi i nga kupu a taua wahine, ka haea e ia ona kakahu; i runga hoki ia i te taiepa e haere ana; a ka titiro te iwi, na, he kakahu taratara tena kei roto, kei tona kiri.
31 Ó sì wí pé, “Kí Ọlọ́run kí ó fi ìyà jẹ mí, àti jù bẹ́ẹ̀ lọ dájúdájú, pé orí ọmọkùnrin Eliṣa ọmọ Ṣafati kì ó wà ní ọrùn rẹ̀ ní òní!”
Katahi ia ka mea, Kia meatia mai tenei ki ahau e te Atua, me tetahi atu mea, ki te u te matenga o Eriha tama a Hapata ki runga ki a ia aianei.
32 Nísinsin yìí Eliṣa jókòó ní ilé rẹ̀ àwọn àgbàgbà náà jókòó pẹ̀lú rẹ̀. Ọba sì rán oníṣẹ́ síwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n kí ó tó dé ibẹ̀, Eliṣa sọ fún àwọn àgbàgbà pé, “Ṣé ẹ̀yin kò rí bí apànìyàn ti ń rán ẹnìkan láti gé orí mi kúrò? Ẹ wò ó, nígbà tí ìránṣẹ́ náà bá dé, ẹ ti ìlẹ̀kùn kí ẹ sì dìímú ṣinṣin ní ẹnu-ọ̀nà, ìró ẹsẹ̀ olúwa rẹ̀ kò ha wà lẹ́yìn rẹ?”
Otiia i noho a Eriha i roto i tona whare, a i noho tahi ratou ko nga kaumatua; na ka unga tangata te kingi i tona aroaro: otiia kiano te karere i tae noa ki a ia, ka mea ia ki nga kaumatua, Kia kite koutou kua unga tangata mai tenei tama a te ka ikohuru ki te tango i toku upoko? Kia mohio, ina tae mai te karere, tutakina te tatau, kia u hoki te pupuri atu i te tatau ki a ia: he teka ianei kei muri i a ia te tapuwae o nga waewae o tona ariki?
33 Nígbà tí ó sì ń sọ̀rọ̀ sí wọn, ìránṣẹ́ náà sọ̀kalẹ̀ wá bá a. Ọba náà sì wí pé, “Ibi yìí láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni. Kí ni ó dé tí èmi yóò fi dúró de Olúwa sí i?”
I a ia ano e korero ana ki a ratou, na ko te karere kua tae iho ki a ia: a ka mea ia, Nana, na Ihowa tenei kino; ko te ahau taku e tatari atu ai ano i a Ihowa?

< 2 Kings 6 >