< 2 Kings 3 >
1 Jehoramu ọmọ Ahabu sì di ọba Israẹli ní Samaria ní ọdún kejìdínlógún ti Jehoṣafati ọba Juda, ó sì jẹ ọba fún ọdún méjìlá.
Judah siangpahrang Jehosaphat siangpahrang ah ohhaih saning hatlaitazetto naah, Ahab capa Jehoram loe Samaria ah Israel siangpahrang ah oh. Anih mah Samaria to saning hatlaihnetto uk.
2 Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí ti ìyá àti baba rẹ̀ ti ṣe. Ó gbé òkúta ère ti Baali tí baba rẹ̀ ti ṣe kúrò.
Anih loe Angraeng mikhnukah kahoih ai hmuen to sak; anih loe ampa hoi amno mah sak ih kasae hmuen to sah ai; anih loe ampa mah sak ih Baal krang to phraek king.
3 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi ara mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, tí ó ti fi Israẹli bú láti dẹ́ṣẹ̀; kò sì yí kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Toe Israel kaminawk zaehaih sahsak, Nebat capa Jeroboam mah sak ih zaehaih to caehtaak ai ah, a sak toeng.
4 Nísinsin yìí Meṣa ọba Moabu ń sin àgùntàn, ó sì gbọdọ̀ fi fún ọba Israẹli pẹ̀lú ọ̀kẹ́ márùn-ún ọ̀dọ́-àgùntàn àti pẹ̀lú irun ọ̀kẹ́ márùn-ún àgbò.
Moab siangpahrang Mesha loe tuu pacah kami ah oh, anih mah Israel siangpahrang hanah tuucaa sang cumvaito, tuumui hoi tuutae sang cumvaito paek poe han oh.
5 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ikú Ahabu, ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀ lórí ọba Israẹli.
Toe Ahab duek pacoengah loe, Moab siangpahrang mah Israel siangpahrang to misa angthawk thuih.
6 Lásìkò ìgbà yìí ọba Jehoramu jáde kúrò ní Samaria ó sì yí gbogbo Israẹli ní ipò padà.
To nathuem ah Jehoram siangpahrang loe Samaria hoiah caeh moe, Israel kaminawk to kroek.
7 Ó sì ránṣẹ́ yìí sí Jehoṣafati ọba Juda pé, “Ọba Moabu sì ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀lú mi láti lọ bá Moabu jà?” Ọba Juda sì dáhùn pé, “Èmi yóò lọ pẹ̀lú rẹ. Èmi jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti wà, ènìyàn rẹ bí ènìyàn mi, ẹṣin mi bí ẹṣin rẹ.”
Judah siangpahrang Jehosaphat khaeah kami to patoeh moe, Moab siangpahrang mah kai misa angthawk thuih boeh; Moab tuk hanah nang bomh han maw? tiah a naa. Anih mah, Kang bomh han, Kai doeh nang baktiah ka oh moe, kai ih kaminawk doeh nang ih kami, kai ih hrangnawk doeh, nang ih hrang baktiah ni oh, tiah a naa.
8 “Nípa ọ̀nà wo ni àwa yóò gbà dojúkọ wọ́n?” Ó béèrè. “Lọ́nà aginjù Edomu,” ó dáhùn.
Anih mah, na bang ih loklam hoiah maw a caeh o tahang han? tiah a naa. Jehoram mah Edom praezaek bang hoiah caeh si, tiah a naa.
9 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli jáde lọ pẹ̀lú ọba Juda àti ọba Edomu. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n yíká fún ọjọ́ méje. Àwọn ọmọ-ogun wọn kò ní omi púpọ̀ fún ara wọn tàbí fún ẹranko tí ó wà pẹ̀lú wọn.
To pongah Israel siangpahrang, Judah siangpahrang hoi Edom siangpahrangnawk loe nawnto caeh o; ni sarihto caeh o pacoeng loe, misatuh kaminawk hoi a hoih o ih moinawk naek hanah tui to tawn o ai boeh.
10 “Kí ni?” ọba Israẹli kígbe sókè. “Ṣé Olúwa pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́?”
To naah Israel siangpahrang mah, Alas! Angraeng mah hae siangpahrang thumtonawk hae, Moab kaminawk ban ah paek boeh mue! tiah thuih.
11 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati sì wí pé, “Ṣé kò sí wòlíì Olúwa níbí, tí àwa ìbá ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?” Ọ̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ ọba Israẹli dáhùn pé, “Eliṣa ọmọ Ṣafati wà níbí. Ó máa sábà bu omi sí ọwọ́ Elijah.”
Toe Jehosaphat mah, Angraeng khaeah lokdueng hanah, hae ah Angraeng ih tahmaa maeto doeh om ai maw? tiah a naa. To naah Israel siangpahrang ih tamna maeto mah, Elijah ban amsaeh han tui bawhkung, Shaphat capa Elisha hae ah oh, tiah a naa.
12 Jehoṣafati wí pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati àti ọba Edomu sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ.
Jehosaphat mah, Angraeng ih lok loe anih khaeah oh, tiah thuih pae. To pongah Israel siangpahrang, Jehosaphat hoi Edom siangpahrang to anih khaeah caeh o tathuk.
13 Eliṣa wí fún ọba Israẹli pé, “Kí ni àwa ní ṣe pẹ̀lú ara wa? Lọ sọ́dọ̀ wòlíì baba rẹ àti wòlíì ti ìyá rẹ.” Ọba Israẹli dá a lóhùn, “Rárá, nítorí Olúwa ni ó pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́.”
Elisha mah Israel siangpahrang khaeah, Nang hoi timaw asaenghaih oh, nampa ih tahmaa hoi namno ih tahmaanawk khaeah caeh khae, tiah a naa. Israel siangpahrang mah, To tih na ai ni, hae siangpahrang thumtonawk loe Moab kaminawk ban ah paek hanah Angraeng mah nawnto pakhueng boeh, tiah a naa.
14 Eliṣa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà pé Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà láyé, ẹni tí mo ń sìn tí èmi kò bá ní ọ̀wọ̀ fún ojú Jehoṣafati ọba Juda, èmi kò ní wò ó tàbí èmi kì bá ti rí ọ.
Elisha mah, Tok ka sak pae ih, Misatuh Angraeng loe hing pongah, Judah siangpahrang Jehosaphat ih mikhmai ka khen ai nahaeloe, nang hae hnuk hanah ka koeh ai, khet mataeng doeh kang khen mak ai.
15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, mú wá fún mi ohun èlò orin olókùn.” Nígbà tí akọrin náà n kọrin, ọwọ́ Olúwa wá sórí Eliṣa.
Toe katoeng kruek kop kami maeto angzo o haih ah, tiah a naa. Katoeng kruek kop kami mah katoeng to kruek naah, Elisha nuiah Angraeng ih ban to oh.
16 Ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ‘Jẹ́ kí àfonífojì kún fún ọ̀gbun.’
Angraeng mah, Hae vacong hae tui ka koisak han, tiah thuih.
17 Nítorí èyí ni Olúwa wí, o kò ní í rí afẹ́fẹ́ tàbí òjò, bẹ́ẹ̀ ni àfonífojì yìí yóò kún pẹ̀lú omi, àti ìwọ àti ẹran ọ̀sìn àti pẹ̀lú àwọn ẹran yóò mu.
Angraeng mah, Takhi hoi khotui to na hnu o mak ai; toe to ih vacongnawk loe tui hoiah koi o boih tih; nangmah hoi nangmah ih moinawk mah naek o pacoengah, kalah taw ih moinawk boih mah doeh nae o tih, tiah thuih.
18 Èyí jẹ́ ohun tí kò lágbára níwájú Olúwa, yóò sì fi Moabu lé e yín lọ́wọ́ pẹ̀lú.
Hae hmuen loe Angraeng mikhnukah zoidaek hmuen ah ni oh; Moab kaminawk doeh nangcae ban ah na paek tih.
19 Ìwọ yóò sì bi gbogbo ìlú olódi àti gbogbo àgbà ìlú ṣubú. Ìwọ yóò sì gé gbogbo igi dáradára ṣubú, dá gbogbo orísun omi dúró, kí o sì pa gbogbo pápá dáradára pẹ̀lú òkúta run.”
Sipae hoi thungh ih vangpuinawk hoi kahoih koek vangpuinawk to phrae o boih ah; kahoih thingnawk to pakhruh o boih ah loe, tuikhawnawk to taet o boih ah; kahoih longnawk doeh thlung hoiah aphum oh loe, paro o boih ah, tiah a naa.
20 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ní àsìkò ẹbọ, níbẹ̀ ni omí sàn láti ọ̀kánkán Edomu! Ilé náà sì kún pẹ̀lú omi.
Khawnbang cang hoi angbawnhaih atue phak naah loe, khenah, Edom bang hoiah tui to long, prae loe tui hoiah koi.
21 Nísinsin yìí gbogbo ará Moabu gbọ́ pé àwọn ọba tí dé láti bá wọn jà. Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ènìyàn, ọmọdé àti àgbà tí ó lè ja ogun wọn pè wọ́n sókè wọ́n sì dúró ní etí ilẹ̀.
Moab kaminawk boih mah nihcae tuk hanah siangpahrang thumto angzoh o boeh, tiah thaih o naah, nihcae loe nawkta mitong tih ai, maiphaw sin thaih kaminawk boih to kawk moe, ramri ah angangsak.
22 Nígbà tí wọ́n dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, oòrùn ti tàn sí orí omi náà sí àwọn ará Moabu ní ìkọjá ọ̀nà, omi náà sì pupa bí ẹ̀jẹ̀.
Khawnbang khawnthaw angthawk o naah, ni aengh mah tui to kah, to naah Moab kaminawk mah ho bang yaeh hoiah, athii baktiah kathim tui to a hnuk o.
23 “Ẹ̀jẹ̀ ni èyí!” wọ́n wí pé, “Àwọn ọba wọ̀nyí lè ti jà kí wọn sì pa ara wọn ní ìpakúpa. Nísinsin yìí sí àwọn ìkógun Moabu!”
To naah nihcae mah, Hae loe athii boeh ni! Siangpahrangnawk loe angmacae hoi angmacae anghum o boeh; to pongah Moab kaminawk, vaihi nihcae ih hmuenmae to la o si, tiah thuih o.
24 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ará Moabu dé sí ibùdó ti Israẹli, àwọn ará Israẹli dìde, wọ́n sì kọlù wọ́n títí tí wọ́n fi sálọ. Àwọn ará Israẹli gbógun sí ilẹ̀ náà wọ́n sì pa Moabu run.
Israel kaminawk ataihaih ahmuen ah Moab kaminawk angzoh o naah, Israelnawk mah angang o moe, Moab kaminawk to takroek o; nihcae loe Israelnawk hmaa ah cawnh o; Israelnawk mah nihcae to Moab prae karoek to patom o moe, hum o.
25 Wọ́n sì wọ gbogbo ìlú náà olúkúlùkù ènìyàn, wọ́n ju òkúta sí gbogbo ohun dáradára orí pápá títí tí ó fi run. Wọ́n sì dá gbogbo orísun omi dúró wọ́n sì gé gbogbo orísun dáradára. Kiri-Hareseti nìkan ni wọ́n fi òkúta rẹ̀ sílẹ̀ ní ààyè rẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ológun pẹ̀lú kànnàkànnà yíká, wọ́n sì kọlù ìlú náà.
Vangpui boih phraek pae o, lawk kahoih ahmuennawk boih to thlung koi mongah vah pae o; tuikhawnawk to patet pae o moe, kahoih thingnawk to pakruk pae o king; Kir-Haraseth vangpui ih sipae thlungnawk khue ni caeh o taak, toe ngazai sin kaminawk mah to vangpui to takui o moe, tuk o.
26 Nígbà tí ọba Moabu rí i wí pé ogun náà le ju ti òun lọ, ó mú idà pẹ̀lú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ọkùnrin onídà láti jà pẹ̀lú ọba Edomu, ṣùgbọ́n wọn kò yege.
Moab siangpahrang mah, misa mah pazawk tih boeh, tiah panoek naah, Edom siangpahrang ataihaih ahmuen hoiah misatuk hanah, sumsen sin kami cumvai sarihtonawk to caeh haih, toe anih mah pazawk thai ai.
27 Nígbà náà ó mú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀, tí kò bá jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọba, ó sì fi rú ẹbọ sísun ní orí ògiri ìlú. Wọ́n sì bínú lórí Israẹli púpọ̀púpọ̀; wọ́n yọ́ kúrò wọ́n sì padà sí ìlú wọn.
To pacoengah angmah zuengah siangpahrang ah kaom han koi calu to lak moe, vangpui sipae nuiah angbawnhaih to a sak; to tiah sakhaih to Israelnawk hanah paroeai panuet thok hmuen ah poek o pongah, angqoi o moe, angmacae prae ah amlaem o taak.