< 2 Kings 3 >
1 Jehoramu ọmọ Ahabu sì di ọba Israẹli ní Samaria ní ọdún kejìdínlógún ti Jehoṣafati ọba Juda, ó sì jẹ ọba fún ọdún méjìlá.
Yuda hina bagade Yihosiafa: de da ode18 ouligilalu, Youla: me (A: iha: be egefe) da Isala: ili hina bagade hamoi. E da Samelia moilai bai bagade amo ganodini esala, ode fagoyale agoane Isala: ili ouligi.
2 Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí ti ìyá àti baba rẹ̀ ti ṣe. Ó gbé òkúta ère ti Baali tí baba rẹ̀ ti ṣe kúrò.
E da Hina Godema wadela: le hamoi, be ea ada amola eme Yesebele, elea wadela: i hou hamoi amo defeledafa hame hamoi. E da Ba: ilema nodone sia: ne gadosu ‘gode’ agoaila, amo eda ea hamoi, amo mugululi sali.
3 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi ara mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, tí ó ti fi Israẹli bú láti dẹ́ṣẹ̀; kò sì yí kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Be amomane, hina bagade Yelouboua: me (Niba: de egefe) amo ea hou defele, e da Isala: ili fi wadela: le hamoma: ne oule asili, amola amo hou fisimusa: hame dawa: i.
4 Nísinsin yìí Meṣa ọba Moabu ń sin àgùntàn, ó sì gbọdọ̀ fi fún ọba Israẹli pẹ̀lú ọ̀kẹ́ márùn-ún ọ̀dọ́-àgùntàn àti pẹ̀lú irun ọ̀kẹ́ márùn-ún àgbò.
Moua: be hina bagade Misia da sibi fofole ouligi. Ode huluane, e da ea lasu su dabe iasu, 100,000 sibi mano amola 100,000 sibi ilia hinabo goloi, amo Isala: ili hina bagade ema iasu.
5 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ikú Ahabu, ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀ lórí ọba Israẹli.
Be Isala: ili hina bagade A: iha: be da bogobeba: le, Misia da Isala: ili fi ilima odoga: i.
6 Lásìkò ìgbà yìí ọba Jehoramu jáde kúrò ní Samaria ó sì yí gbogbo Israẹli ní ipò padà.
Isala: ili hina bagade da hedolowane Samelia yolesili, ea dadi gagui dunu gagadoi.
7 Ó sì ránṣẹ́ yìí sí Jehoṣafati ọba Juda pé, “Ọba Moabu sì ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀lú mi láti lọ bá Moabu jà?” Ọba Juda sì dáhùn pé, “Èmi yóò lọ pẹ̀lú rẹ. Èmi jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti wà, ènìyàn rẹ bí ènìyàn mi, ẹṣin mi bí ẹṣin rẹ.”
E da Yuda hina bagade Yihosiafa: dema sia: amane adosi, “Moua: be hina bagade da nama odoga: sa. Di da nama madelale ema gegema: bela: ?” Hina bagade Yihosiafa: de da amane bu adole i, “Ma! Amamuda! Na amola na dunu amola na fila heda: le gegesu hosi da dia hanai defele hamomu.
8 “Nípa ọ̀nà wo ni àwa yóò gbà dojúkọ wọ́n?” Ó béèrè. “Lọ́nà aginjù Edomu,” ó dáhùn.
Ninia da logo habidili asili, doagala: ma: bela: ?” Youla: me da bu adole i, “Ninia da logo sedade, Idome hafoga: i sogedili masunu!”
9 Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli jáde lọ pẹ̀lú ọba Juda àti ọba Edomu. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n yíká fún ọjọ́ méje. Àwọn ọmọ-ogun wọn kò ní omi púpọ̀ fún ara wọn tàbí fún ẹranko tí ó wà pẹ̀lú wọn.
Amaiba: le, hina bagade Youla: me amola Yuda hina bagade amola Idome hina bagade da wa: le asi. Eso fesuale agoane mogodigili ahoanoba, hano di da ebeleiba: le, dunu amola ohe da hano manu hame ba: i.
10 “Kí ni?” ọba Israẹli kígbe sókè. “Ṣé Olúwa pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́?”
Hina bagade Yelouboua: me da amane sia: i, “Waiye! Ninimone masunu hamedei! Hina Gode da hina bagade dunu udiana ninima, nini Moua: be hina bagade nini hasalasimusa: gegedolesibala: !”
11 Ṣùgbọ́n Jehoṣafati sì wí pé, “Ṣé kò sí wòlíì Olúwa níbí, tí àwa ìbá ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?” Ọ̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ ọba Israẹli dáhùn pé, “Eliṣa ọmọ Ṣafati wà níbí. Ó máa sábà bu omi sí ọwọ́ Elijah.”
Hina bagade Yihosiafa: de da amane adole ba: i, “Goegai balofede dunu afae, ea da Hina Godema adole ba: mu ganabela: ?” Hina bagade Youla: me ea dadi gagui ouligisu dunu afae da amane adole i, “Ilaisia (Sia: ifa: de egefe) da goegai lela. E da Ilaidia ea afoha hawa: hamosu dunu galu.”
12 Jehoṣafati wí pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati àti ọba Edomu sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ.
Yihosiafa: de da amane sia: i, “E da dafawane balofede dunudafa!” Amalalu, hina bagade dunu udiana da Ilaisiama afia: i.
13 Eliṣa wí fún ọba Israẹli pé, “Kí ni àwa ní ṣe pẹ̀lú ara wa? Lọ sọ́dọ̀ wòlíì baba rẹ àti wòlíì ti ìyá rẹ.” Ọba Israẹli dá a lóhùn, “Rárá, nítorí Olúwa ni ó pe àwa ọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta papọ̀ láti fi wá lé Moabu lọ́wọ́.”
Ilaisia da Isala: ili hina bagadema amane sia: i, “Abuliba: le na da di fidima: bela: ? Di da asili, dia ada amola ame ilia balofede eno ilima adole ba: i. Ilima adole ba: la masa.” Youla: me da amane adole i, “Hame mabu! Hina Gode Hi fawane da nini hina bagade udiana amo Moua: be hina bagade nini hasalasimusa: asunasi.”
14 Eliṣa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà pé Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà láyé, ẹni tí mo ń sìn tí èmi kò bá ní ọ̀wọ̀ fún ojú Jehoṣafati ọba Juda, èmi kò ní wò ó tàbí èmi kì bá ti rí ọ.
Ilaisia da bu adole i, “Na da Hina Gode Esalebe Ea hawa: hamosa. Amo Ea Dioba: le, na da amane ilegele sia: sa. Na da dia fidisu dunu, Yuda hina bagade Yihosiafa: de, ema asigiba: le fawane, di fidimu.
15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, mú wá fún mi ohun èlò orin olókùn.” Nígbà tí akọrin náà n kọrin, ọwọ́ Olúwa wá sórí Eliṣa.
Wali, sani baidama dusu dunu, nama oule misa!” Sani baidama dusu dunu da ea sani baidama dunanoba, Hina Gode da Ilaisiama Ea gasa i.
16 Ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ‘Jẹ́ kí àfonífojì kún fún ọ̀gbun.’
E amane sia: i, “Hina Gode da amane sia: sa, ‘Amo hano logo hafogai ganodini, hano ogai bagohame ogane gagama!
17 Nítorí èyí ni Olúwa wí, o kò ní í rí afẹ́fẹ́ tàbí òjò, bẹ́ẹ̀ ni àfonífojì yìí yóò kún pẹ̀lú omi, àti ìwọ àti ẹran ọ̀sìn àti pẹ̀lú àwọn ẹran yóò mu.
Dilia da gibu amola fo afae hamedafa ba: mu. Be amo hafogai hano logo da hanoga nabai ba: mu. Amola di, amola dia ohe wa: i, amola liligi gaguli ahoasu ohe, ilia da hano manu gilisi ba: mu.”
18 Èyí jẹ́ ohun tí kò lágbára níwájú Olúwa, yóò sì fi Moabu lé e yín lọ́wọ́ pẹ̀lú.
Ilaisia da eno amane sia: i, “Be amo hou hamomu da Hina Godema da asaboi gala. Amolawane, e da dilima Moua: bema hasalasisu hou imunu.
19 Ìwọ yóò sì bi gbogbo ìlú olódi àti gbogbo àgbà ìlú ṣubú. Ìwọ yóò sì gé gbogbo igi dáradára ṣubú, dá gbogbo orísun omi dúró, kí o sì pa gbogbo pápá dáradára pẹ̀lú òkúta run.”
Dilia da ilia gagili sanawene moilai noga: idafa huluane amo hasalasilalu, samogene lamu. Dilia da ilia ifa dulu faili nasu huluane abusa: le salimu. Dilia da ilia hano nasu huluane lelesimu. Amola ilia nasegagi ha: i bugili nasu soge huluane gelega dedebole, gugunufinisimu.”
20 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ní àsìkò ẹbọ, níbẹ̀ ni omí sàn láti ọ̀kánkán Edomu! Ilé náà sì kún pẹ̀lú omi.
Golale hahabe, hahabe gobele salalusu eso defele, hano da Idome sogeganini a: imisini, osobo dedeboi.
21 Nísinsin yìí gbogbo ará Moabu gbọ́ pé àwọn ọba tí dé láti bá wọn jà. Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ènìyàn, ọmọdé àti àgbà tí ó lè ja ogun wọn pè wọ́n sókè wọ́n sì dúró ní etí ilẹ̀.
Moua: be dunu da hina bagade udiana ili doagala: musa: misi dagoi nababeba: le, ilia dunu huluane amo da gegesu liligi gaguli ahoasu dawa: , amo ilima misa: ne sia: nu, Isala: ili soge alalo amoga dadalema: ne sia: i.
22 Nígbà tí wọ́n dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, oòrùn ti tàn sí orí omi náà sí àwọn ará Moabu ní ìkọjá ọ̀nà, omi náà sì pupa bí ẹ̀jẹ̀.
Ilia da hahabe galu wa: legadole, eso da hano da: iya digagala: i amo da ma: ga: me agoai ba: i.
23 “Ẹ̀jẹ̀ ni èyí!” wọ́n wí pé, “Àwọn ọba wọ̀nyí lè ti jà kí wọn sì pa ara wọn ní ìpakúpa. Nísinsin yìí sí àwọn ìkógun Moabu!”
Moua: be dunu da amane sia: i, “Amo da maga: me! Ha lai wa: i udiana ilia da ili gobele gegeiba: le, huluane medole legei ba: sa. Ninia da ilia ha wa: i fisisuga liligi samogemusa: ahoa: di!”
24 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ará Moabu dé sí ibùdó ti Israẹli, àwọn ará Israẹli dìde, wọ́n sì kọlù wọ́n títí tí wọ́n fi sálọ. Àwọn ará Israẹli gbógun sí ilẹ̀ náà wọ́n sì pa Moabu run.
Be ilia da Isala: ili ha wa: i fisisua doaga: loba, Isala: ili dunu da ilima doagala: le, ili misibudili se bobogei. Ilia da ili se bobogele, Moua: be fi dunu medole lelegele,
25 Wọ́n sì wọ gbogbo ìlú náà olúkúlùkù ènìyàn, wọ́n ju òkúta sí gbogbo ohun dáradára orí pápá títí tí ó fi run. Wọ́n sì dá gbogbo orísun omi dúró wọ́n sì gé gbogbo orísun dáradára. Kiri-Hareseti nìkan ni wọ́n fi òkúta rẹ̀ sílẹ̀ ní ààyè rẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ológun pẹ̀lú kànnàkànnà yíká, wọ́n sì kọlù ìlú náà.
amola ilia moilai gugunufinisi. Ilia da nasegagi sogebi amo baligilala, Isala: ili dunu huluane afae afae da amoga gelega gaga: lala, nasegagi ha: i manu bugili nasu soge huluane da gelega dedeboi ba: i. Amola ilia da hano bubuga: su huluane lelesisili amola ifa dulu faili nasu huluane abusa: le sali. Amalalu, fa: nodafa, Moua: be soge moilai bai bagade Ge Helese amo fawane dialebe ba: i. Isala: ili ga: muga: dadi gagui dunu da amo moilai sisiga: le, doagala: i.
26 Nígbà tí ọba Moabu rí i wí pé ogun náà le ju ti òun lọ, ó mú idà pẹ̀lú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ọkùnrin onídà láti jà pẹ̀lú ọba Edomu, ṣùgbọ́n wọn kò yege.
Moua: be hina bagade da gegesu amoga e da hasalabe ba: beba: le, e da gegesu gobihei gagui dunu 7,000 agoane oule asili, ha wa: i dadalei amodili Silia hina bagade ema hobeale masusa: dawa: i. Be hamedei ba: i.
27 Nígbà náà ó mú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀, tí kò bá jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọba, ó sì fi rú ẹbọ sísun ní orí ògiri ìlú. Wọ́n sì bínú lórí Israẹli púpọ̀púpọ̀; wọ́n yọ́ kúrò wọ́n sì padà sí ìlú wọn.
Amaiba: le, e da ea magobo mano lale (amo da e bagia hina bagade hamomu galu) amo medole legele, Moua: be ogogole ‘gode’ma, moilai gagoi da: iya gobele sali. Isala: ili dunu da amo ba: beba: le, bagade beda: igia: i. Amaiba: le, ilia da moilai fisili, ilia sogedafa buhagi.