< 2 Kings 23 >

1 Nígbà náà ọba pe gbogbo àwọn àgbàgbà Juda àti Jerusalẹmu jọ.
Te vaengah manghai loh a tah dongah Judah neh Jerusalem kah a ham boeih te anih taengla tingtun uh.
2 Ó gòkè lọ sí ilé Olúwa pẹ̀lú àwọn ọkùnrin Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu, àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì—gbogbo àwọn ènìyàn láti ibi kéékèèké sí ńlá. Ó kà á sí etí ìgbọ́ ọ wọn, gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé májẹ̀mú, tí a ti rí nínú ilé Olúwa.
Manghai neh Judah hlang boeih, a taengkah Jerusalem khosa boeih, khosoih rhoek neh tonghma rhoek khaw, pilnam cungkuem tanoe lamloh kangham hil khaw BOEIPA im la cet tih BOEIPA im kah a hmuh paipi cabu dongkah ol boeih te amih hna ah a doek pah.
3 Ọba sì dúró lẹ́bàá òpó, ó sì sọ májẹ̀mú di tuntun níwájú Olúwa, láti tẹ̀lé Olúwa àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, ìlànà àti òfin pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ̀ àti gbogbo ẹ̀mí rẹ̀, àti láti ṣe ìwádìí àwọn ọ̀rọ̀ májẹ̀mú tí a kọ sínú ìwé yìí. Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn sì ṣèlérí fúnra wọn sí májẹ̀mú náà.
Te vaengah manghai te tung taengah pai tih BOEIPA hnukah pongpa ham, a olpaek neh a olphong neh, a khosing te lungbuei boeih neh hinglu boeih neh tuem ham khaw, te cabu dongah a daek paipi ol te thoh ham khaw BOEIPA mikhmuh ah paipi te a saii. Te dongah pilnam cungkuem loh paipi te a pai puei.
4 Ọba sì pàṣẹ fún Hilkiah olórí àlùfáà àti àwọn, àlùfáà tí ó tẹ̀lé e ní ipò àti àwọn olùṣọ́nà láti yọ kúrò nínú ilé Olúwa gbogbo ohun èlò tí a ṣe fún Baali àti Aṣerah àti gbogbo ẹgbẹ́ ogun ọ̀run. Ó sì sun wọ́n ní ìta Jerusalẹmu ní pápá àfonífojì Kidironi. Ó sì kó eérú wọn jọ sí Beteli.
Te phoeiah manghai loh khosoih boei Hilkiah neh hnukthoi khosoih rhoek khaw, cingkhaa aka hung rhoek khaw, Baal ham neh Asherah ham, vaan caempuei cungkuem ham a saii hnopai cungkuem te BOEIPA bawkim lamloh khoe ham a uen. Te dongah te rhoek te Jerusalem vongvoel kah Kidron lohmali ah a hoeh tih a hloi te Bethel la a phueih.
5 Ó sì kúrò pẹ̀lú àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà tí a yàn láti ọwọ́ ọba Juda láti sun tùràrí ní ibi gíga ti ìlú Juda àti àwọn tí ó yí Jerusalẹmu ká. Àwọn tí ó ń sun tùràrí sí Baali, sí oòrùn àti òṣùpá, sí àwọn àmì ìràwọ̀ àti sí gbogbo ẹgbẹ́ ogun ọ̀run.
Te vaengah Judah manghai rhoek kah a khueh mueirhol khosoih rhoek khaw, Judah khopuei rhoek kah hmuensang neh Jerusalem phai ah aka phum te khaw, Baal taengah, khomik taeng neh hla taengah, aisi taeng neh vaan caempuei cungkuem taengah aka phum rhoek te khaw a paa sak.
6 Ó mú ère òrìṣà Aṣerah láti ilé Olúwa sí àfonífojì Kidironi ní ìta Jerusalẹmu, ó sì sun wọ́n níbẹ̀. Ó lọ̀ ọ́ bí àtíkè ó sì fọ́n eruku náà sórí isà òkú àwọn ènìyàn tí ó wọ́pọ̀.
Asherah te BOEIPA im lamloh Jerusalem vongvoel kah Kidron soklong la a khuen. Te te Kidron soklong ah a hoeh tih laipi la a tip sak. Te phoeiah a hloi te pilnam paca kah phuel ah a hawk.
7 Ó sì wó ibùgbé àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà lulẹ̀. Tí ó wà nínú ilé Olúwa àti ibi tí àwọn obìnrin tí ń ṣe iṣẹ́ aṣọ híhun fún òrìṣà Aṣerah.
BOEIPA im kah hlanghalh im te khaw a palet pah. Te ah te huta rhoek loh Asherah ham im a tah uh.
8 Josiah kó gbogbo àwọn àlùfáà láti àwọn ìlú Juda ó sì ba ibi mímọ́ wọ̀n-ọn-nì jẹ́ láti Geba sí Beerṣeba, níbi tí àwọn àlùfáà ti sun tùràrí. Ó wó àwọn ojúbọ lulẹ̀ ní ẹnu ìlẹ̀kùn—ní ẹnu-ọ̀nà àbáwọlé ti Joṣua, baálẹ̀ ìlú ńlá tí ó wà ní apá òsì ẹnu ìlẹ̀kùn ìlú ńlá.
Khosoih boeih te Judah khopuei lamloh a khuen tih khosoih rhoek loh hnap a phum thil hmuensang te Geba lamloh Beersheba duela a poeih pah. Khopuei mangpa Joshua vongka thohka kah vongka hmuensang te khaw a palet. Te te khopuei vongka kah banvoei ah rhip om.
9 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, àwọn àlùfáà ibi gíga kò jọ́sìn ní ibi pẹpẹ Olúwa ní Jerusalẹmu, wọ́n jẹ nínú àkàrà aláìwú pẹ̀lú àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn.
Hmuensang khosoih rhoek te Jerusalem ah BOEIPA hmueihtuk taengla mop uh pawt sitoe cakhaw a manuca lakli ah vaidamding a caak uh.
10 Ó sì ba ohun mímọ́ Tofeti jẹ́, tí ó wà ní àfonífojì Beni-Hinnomu, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹnìkan tí ó lè lò ó fún ẹbọ rírú fún ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tàbí ọmọ rẹ̀ obìnrin nínú iná sí Moleki.
Hlang loh a capa khaw, a canu khaw hmai dong lamloh Molek taengla kat sak pawt ham kolrhawk, kolrhawk kah Topheth te khaw a poeih pah.
11 Ó sì kúrò láti ẹnu-ọ̀nà àbáwọlé sí ilé Olúwa, àwọn ẹṣin tí àwọn ọba Juda ti yà sọ́tọ̀ sí oòrùn náà. Wọ́n wà nínú ilé ẹjọ́ lẹ́bàá yàrá oníṣẹ́ tí orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Natani-Meleki. Josiah sì sun àwọn kẹ̀kẹ́ tí a yà sọ́tọ̀ fún oòrùn.
Judah manghai rhoek loh khomik taengla a nawn tih BOEIPA im kah a kun lamloh imkhoem Nathanmelek imkhan kaep kah imhlai laklo hil a khueh marhang te khaw a paa sak. Khomik leng te khaw hmai ah a hoeh.
12 Ó wó o palẹ̀ pẹpẹ tí àwọn ọba Juda ti wọ́n gbé dúró ní orí òrùlé lẹ́bàá yàrá òkè ti Ahasi pẹ̀lú àwọn pẹpẹ tí Manase ti kọ́ nínú ilé ẹjọ́ méjèèjì sí ilé Olúwa. Ó ṣí wọn kúrò níbẹ̀, ó fọ́ wọn sí wẹ́wẹ́. Ó sì da ekuru wọn sínú àfonífojì Kidironi.
Judah manghai rhoek loh a saii Ahaz imhman, imphu sokah hmueihtuk rhoek khaw, Manasseh loh BOEIPA im vongup rhoi khuiah a khueh hmueihtuk te khaw manghai loh a palet. Te phoeiah te lamloh yong tih a hloi te Kidron soklong la a voeih.
13 Ọba pẹ̀lú ba ohun mímọ́ àwọn ibi gíga jẹ́ tí ó wà ní ìhà ìlà-oòrùn Jerusalẹmu ní ìhà gúúsù ti òkè ìbàjẹ́—èyí tí Solomoni ọba Israẹli ti kọ́ fún Aṣtoreti ọlọ́run ìríra àwọn ará Sidoni, fún Kemoṣi ọlọ́run ìríra àwọn ará Moabu àti fún Moleki, ọlọ́run ìríra àwọn ènìyàn Ammoni.
Hmuensang te Jerusalem imdan kah khaw, kutcaihnah tlang kah bantang ah khaw Israel manghai Solomon loh Sidoni kah sarhingkoi Ashtoreth ham, Moab kah sarhingkoi Khemosh ham, Ammon koca rhoek kah tueilaehkoi Milkom ham a sak pah te khaw manghai loh a poeih pah.
14 Josiah fọ́ òkúta yíyà sọ́tọ̀, ó sì gé ère Aṣerah lulẹ̀. Ó sì bo ẹ̀gbẹ̀gbẹ́ ẹ rẹ̀ pẹ̀lú egungun ènìyàn.
Kaam te a phaek tih Asherah te a top pah phoeiah tah a hmuen te hlang rhuh a bae sak.
15 Àní pẹpẹ tí ó wà ní Beteli ibi gíga tí Jeroboamu ọmọ Nebati dá. Tí ó ti fa Israẹli láti ṣẹ̀, àní pẹpẹ náà àti ibi gíga tí ó fọ́ túútúú. Ó jó àwọn ibi gíga, ó sì lọ̀ ọ́ sí ẹ̀tù, ó sì sun ère Aṣerah pẹ̀lú.
Bethel kah hmueihtuk te khaw, Israel aka tholh sak Nebat capa Jeroboam loh a saii hmuensang te khaw, te kah hmueihtuk neh hmuensang te khaw a palet tih a hoeh. Hmuensang te laipi la a tip sak tih Asherah te a hoeh pah.
16 Nígbà náà, Josiah wò yíká, nígbà tí ó sì rí àwọn isà òkú tí ó wà níbẹ̀ ní ẹ̀bá òkè, ó yọ egungun kúrò lára wọn, ó sì jó wọn lórí pẹpẹ láti sọ ọ́ di èérí ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa tí a ti kéde láti ọ̀dọ̀ ènìyàn Ọlọ́run tí ó ti àwọn nǹkan wọ̀nyí tẹ́lẹ̀.
Josiah te a mael vaengah phuel te tlang ah hnap a hmuh. Te dongah hlang a tueih tih phuel lamkah a rhuh te a poh sak. Te phoeiah hmueihtuk soah a hoeh tih BOEIPA ol bangla a poeih. Pathen kah hlang loh a doek vaengah te kah ol te a doek coeng.
17 Ọba sì béèrè pé, “Kí ni ọwọ̀n isà òkú yẹn tí mo rí?” Àwọn ọkùnrin ìlú ńlá wí pé, “Ó sàmì sí isà òkú ènìyàn Ọlọ́run tí ó wá láti Juda, tí ó sì kéde ìdojúkọ pẹpẹ Beteli, ohun kan wọ̀nyí tí ìwọ ti ṣe sí wọn.”
Te vaengah, “Bang pangkae nim ka hmuh he?” a ti. Te dongah khopuei hlang rhoek loh a taengah, “Pathen hlang kah phuel ni. Anih he Judah lamkah ha pawk tih Bethel hmueihtuk ah na saii hno te a doek,” a ti na uh.
18 “Fi sílẹ̀ nìkan,” Ó wí pé. “Má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ó da àwọn egungun rẹ̀ láàmú.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n dá egungun rẹ̀ sí àti ti àwọn wòlíì tí ó wá láti Samaria.
Tedae, “Anih te om saeh, hlang loh a rhuh thaih boel saeh,” a ti nah. Te dongah Samaria lamkah aka pawk tonghma rhuh tah amah rhuh bangla a khueh.
19 Gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ní Beteli, Josiah sì kúrò, ó sì ba gbogbo ojúbọ òrìṣà ti ibi gíga jẹ́, tí àwọn ọba Israẹli ti kọ́ sí àwọn ìlú ní Samaria, tí ó ti mú Olúwa bínú.
Samaria khopuei rhoek ah BOEIPA veet hamla Israel manghai rhoek loh a sak hmuensang im boeih te khaw Josiah loh a khoe. Te rhoek te Bethel ah a saii bangla khoboe cungkuem neh a saii.
20 Josiah dúńbú gbogbo àwọn àlùfáà ibi gíga lórí pẹpẹ. Ó sì sun egungun ènìyàn lórí wọn. Nígbà náà, ó padà lọ sí Jerusalẹmu.
Hmuensang khosoih boeih te hmueihtuk dongah pahoi ngawn tih hlang rhuh te a soah a hoeh daengah Jerusalem la mael.
21 Ọba pàṣẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn pé, “Ẹ ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá sí Olúwa Ọlọ́run yín, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sí inú ìwé májẹ̀mú yìí.”
Te phoeiah manghai loh pilnam pum te a uen tih, “He paipi cabu khuiah a daek bangla na Pathen BOEIPA ham Yoom saii uh.
22 Kì í ṣe láti ọjọ́ àwọn Juda tí ó tọ́ Israẹli, ní gbogbo àwọn ọjọ́ àwọn ọba Israẹli àti àwọn ọba Juda. Ṣé wọ́n ti ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá rí.
Laitloek rhoek loh Israel lai a tloek tue lamkah te Israel manghai rhoek neh Judah manghai rhoek tue boeih ah khaw hekah Yoom bang he a saii uh moenih.
23 Ṣùgbọ́n ní ọdún kejìdínlógún tí ọba Josiah, àjọ ìrékọjá yìí ni a ṣe ìrántí sí Olúwa ní Jerusalẹmu.
Tedae manghai Josiah kah kum hlai rhet daengah ni Yoom he BOEIPA ham Jerusalem ah a saii pueng.
24 Síwájú sí, Josiah sì lé àwọn oṣó àti àwọn ẹ̀mí ní àwọn ìdílé, àti àwọn òrìṣà àti gbogbo àwọn nǹkan ìríra tí a rí ní Juda àti ní Jerusalẹmu. Èyí ni ó ṣe kí ó le è mú ọ̀rọ̀ òfin náà ṣe ní ti òfin tí a kọ sínú ìwé tí Hilkiah àlùfáà ti rí nínú ilé Olúwa.
BOEIPA im ah khosoih Hilkiah loh a hmuh cabu khuiah a daek olkhueng ol te thoh hamla Josiah loh rhaitonghma neh hnam khaw, sithui neh mueirhol khaw, Judah khohmuen khui neh Jerusalem kah a hmuh sarhingkoi cungkuem te khaw boeih a hoeh.
25 Kò sì sí ọba kankan níwájú tàbí lẹ́yìn Josiah tí ó dàbí rẹ̀, tí ó yí padà sí olúwa tinútinú àti gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe tọkàntọkàn pẹ̀lú gbogbo ẹ̀mí i rẹ̀, pẹ̀lú gbogbo agbára rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo òfin Mose.
Anih bangla BOEIPA taengah a thinko boeih, a hinglu boeih, a thadueng boeih neh aka mael manghai he anih hlan ah a om noek moenih. Anih bangla Moses kah olkhueng cungkuem dongah aka pongpa khaw anih hnukah a phoe bal moenih.
26 Bí ó ti wù kí ó rí Olúwa kò yípadà kúrò nínú ìmúná ìbínú ńlá rẹ̀ tí ó jó sí Juda, nítorí gbogbo èyí tí Manase ti ṣe láti mú un bínú.
Tedae BOEIPA kah a thintoek thinsa puei te a mael moenih. Manasseh loh anih a veet vanbangla konoinah cungkuem dongah a thintoek loh Judah a sai thil pueng.
27 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí pé, “Èmi yóò mú Juda kúrò pẹ̀lú níwájú mi, bí mo ti mú Israẹli, èmi yóò sì kó Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí mo yàn àti ilé Olúwa yìí, nípa èyí tí mo sọ, ‘Níbẹ̀ ni orúkọ mi yóò wà?’”
Te dongah BOEIPA loh, “Judah te khaw ka mikhmuh lamloh Israel ka khoe bangla ka khoe ni. Jerusalem he ka coelh tih im he khaw kamah ming la pahoi om saeh ka ti vanbangla hekah khopuei he ka hnawt ni,” a ti.
28 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Josiah, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò kọ wọ́n sí inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda?
Josiah kah ol noi neh a saii boeih te khaw Judah manghai rhoek kah khokhuen olka cabu dongah a daek uh moenih a?
29 Nígbà tí Josiah jẹ́ ọba, Farao Neko ọba Ejibiti gòkè lọ sí odò Eufurate láti lọ ran ọba Asiria lọ́wọ́. Ọba Josiah jáde lọ láti lọ bá a pàdé lójú ogun ṣùgbọ́n Neko dojúkọ ọ́, ó sì pa á ní Megido.
Anih tue vaengah Egypt manghai Pharaoh Neko te Assyria manghai taengah Perath tuiva la cet. Te dongah manghai Josiah te anih mah hamla cet dae Megiddo ah anih te a hmuh vaengah anih te a duek sak.
30 Ìránṣẹ́ Josiah gbé ara rẹ̀ wá nínú kẹ̀kẹ́ láti Megido sí Jerusalẹmu ó sì sin ín sínú isà òkú rẹ̀. Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà mú Jehoahasi ọmọ Josiah. Ó fi àmì òróró yàn án, ó sì ṣe é ní ọba ní ipò baba a rẹ̀.
Te dongah a sal rhoek loh a duek rhok te a tloeng uh tih Megiddo lamloh Jerusalem la a khuen uh. Te phoeiah anih te amah phuel ah a up uh. Te vaengah khohmuen pilnam loh Josiah capa Jehoahaz te a loh tih a koelh uh phoeiah anih te a napa yueng la a manghai sakuh.
31 Jehoahasi sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Hamutali ọmọbìnrin Jeremiah; ó wá láti Libina.
Jehoahaz he kum kul kum thum a lo ca vaegah manghai tih Jerusalem ah hla thum manghai. A manu ming tah Libnah lamkah Jeremiah canu Hamutal ni.
32 Ó ṣe búburú lójú Olúwa gẹ́gẹ́ bí baba a rẹ̀ ti ṣe.
A napa rhoek kah a cungkuem a saii bangla BOEIPA mik ah boethae a saii.
33 Farao Neko sì fi sí inú ìdè ní Ribla ní ilẹ̀ Hamati, kí ó má ba à lè jẹ ọba ní Jerusalẹmu. Ó sì tan Juda jẹ fun iye ìwọ̀n ẹgbẹ̀rin tálẹ́ǹtì wúrà kan.
Anih te Pharaoh Neko loh Khamath khohmuen kah Riblah ah a khoh. Jerusalem ah a manghai tah a manghai sak dae khohmuen kah cawn la cak talent yakhat neh sui talent khat te a thoh sak.
34 Farao Neko ṣe Eliakimu ọmọ Josiah ní ọba ní ipò baba rẹ̀ Josiah. Ó sì yí orúkọ Eliakimu padà sí Jehoiakimu. Ṣùgbọ́n ó mú Jehoahasi, ó sì gbé e lọ sí Ejibiti, níbẹ̀ ni ó sì kú.
Pharaoh Neko loh Josiah capa Eliakim te a napa Josiah yueng la a manghai sak tih a ming te Jehoiakim la a hoi pah. Tedae Jehoahaz loh a loh tih Egypt la a khuen vaengah pahoi duek.
35 Jehoiakimu sì san fún Farao Neko fàdákà àti wúrà tí ó béèrè. Láti ṣe bẹ́ẹ̀, ó bu owó òde fún ilẹ̀ náà láti san, ó fi agbára gba fàdákà àti wúrà láti ọwọ́ àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà ní ìbámu pẹ̀lú iye tí a pín.
Cak neh sui khaw Jehoiakim loh Pharaoh taengla a paek. Te phoeiah Pharaoh kah kueknah bangla cak te paek ham khohmuen te a kawt. Pharaoh Neko taengah paek hamla khohmuen pilnam kah tangka neh sui mai a phu bangla hlang taengah lai a suk.
36 Jehoiakimu jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlá orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sebida ọmọbìnrin Pedaiah ó wá láti Ruma.
Jehoiakim he kum kul kum nga a lo ca vaengah manghai tih Jerusalem ah kum hlai khat manghai. A manu ming Zebidah he khaw Rumah lamkah Pedaiah canu Zebidah ni.
37 Ó sì ṣe búburú lójú Olúwa gẹ́gẹ́ bí baba a rẹ̀ ti ṣe.
Tedae a napa rhoek kah a saii bangla BOEIPA mikhmuh ah boethae cungkuem te a saii.

< 2 Kings 23 >