< 2 Kings 22 >

1 Josiah jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jedida ọmọbìnrin Adaiah; ó wá láti Boskati.
Hanki Josaia'a 8'a kafu nehuno, Juda vahe kini efore huteno, 31ni'a kafufi Jerusalemi rankumatera kinia mani'ne. Nerera'a Adaia mofa, Jedidakino Bozkati rankumateti a' mani'ne.
2 Ó sì ṣe èyí tí ó dára lójú Olúwa, ó sì rìn ní ọ̀nà Dafidi baba a rẹ̀, kò sì yípadà sí apá ọ̀tún tàbí sí apá òsì.
Hagi Josaia'a Ra Anumzamofo avurera fatgo avu'avaza nehuno, negeho Deviti'ma Ra Anumzamofo nanekema amage'ma ante'neaza huno, avua keganti kegma osuno, Ra Anumzamofo nanekea ana maka amage ante'ne.
3 Ní ọdún kejìdínlógún tí ó fi jẹ ọba. Ọba Josiah rán akọ̀wé, Ṣafani ọmọ Asalia, ọmọ Meṣullamu, sí ilé Olúwa. Ó wí pé,
Hagi Josaia'ma Juda vahe kinima 18ni'a kafuma nemanino'a, avontafe negrea ne' Azaria nemofo, Mesulamu negeho Safanina, Ra Anumzamofo mono nontega vinogu anage huno hunte'ne,
4 “Gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, kí o sì jẹ́ kí ó ṣírò iye owó tí a mú wá sí ilé Olúwa, tí àwọn olùṣọ́nà ti gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn.
Kagra vunka ugagota pristi ne' Hilkiana ome asamigeno, Ra Anumzamofo mono no kafante'ma kvama nehaza vahe'mo'zama mono no kahanteti'ma zonegiza zagoa hamprino.
5 Ẹ sì jẹ́ kí wọn ó fi lé àwọn ọkùnrin tí a ti yàn láti bojútó iṣẹ́ náà lórí ilé Olúwa. Kí ẹ sì jẹ́ kí àwọn ọkùnrin san án fún àwọn òṣìṣẹ́ tí ó ń tún ilé Olúwa ṣe.
Hagi Hilkiana asamigeno ana zagoa erino, Ra Anumzamofo mono nonte'ma eri'zama eneriza vahete kva vahe zamino. Anama hani'ge'za ana vahe'mo'za eri'za vahera miza senezmantesage'za Ra Anumzamofo mono noma havizama hu'nenia zana eri fatgo hugahaze.
6 Àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, àwọn ọ̀mọ̀lé àti àwọn akọ́lé. Bákan náà ni wọ́n ra igi àti òkúta ọlọ́ṣọ̀ọ́ láti fi tún tẹmpili ṣe.
Hagi kamunta vahe'ene kva vahe'zamine, havereti'ma noma eri fatgoma hu'za negiza vahe'ene, havema taga hu'za noma eri fatgohu eri'zama erisaza vahera, ana zagonu mi'zana huzmantegahaze. Ana nehu'za Ra Anumzamofo mono noma eri fatgo hu'za kisaza zafane, ko'ma taga huno eri pehe hunte haveramina ana zagoretike mizasegahaze.
7 Ṣùgbọ́n wọn kò ní láti ṣe ìṣirò fún owó náà tí a fi fún wọn, nítorí wọ́n ṣe òtítọ́.”
Hagi ana zagoma zamisaza kva vahera, inankna hutma zagoa netraze hutma zamantahi onkeho. Na'ankure zamagra fatgo hu'za eri'za eri vahe mani'naze.
8 Hilkiah olórí àlùfáà sọ fún Ṣafani akọ̀wé pé, “Èmi rí ìwé òfin nílé Olúwa.” Ó fi fún Ṣafani, ẹni tí ó kà á.
Hagi anankema asamitegeno'a, ugagota pristi ne' Hilkia'a amanage huno avontafe'ma negrea ne' Safanina asami'ne, Nagra Ra Anumzamofo mono nompinti kasegema me'nea avontafera kena eri'noe, huno nehuno ana avontafera Safanina amigeno hampri'ne.
9 Nígbà náà, Ṣafani akọ̀wé lọ sí ọ̀dọ̀ ọba. Ó sì sọ fún un pé, “Àwọn ìjòyè rẹ ti san owó náà tí ó wà nínú ilé Olúwa. Èmi sì ti fi lé ọwọ́ àwọn tí ó ń ṣe iṣẹ́ náà àti àwọn alábojútó nílé Olúwa.”
Anama huteno'a avontafe'ma negrea ne' Safani'a vuno kini ne' Josaiana amanage huno ome asami'ne, Eri'za vahekamo'za ana zagoa eri vgrare'za Ra Anumzamofo mono noma eri fatgo hu erizante'ma kegava hu'naza kva vahe zamazampi ante'naze.
10 Nígbà náà Ṣafani akọ̀wé sọ fún ọba pé, “Hilkiah àlùfáà ti fún un ní ìwé kan.” Ṣafani kà lára rẹ̀ níwájú ọba.
Anage nehuno avontafe'ma negrea ne' Safani'a mago'ane kini nera amanage huno asami'ne, Pristi ne' Hilkia'a mago avontafe namige'na eri'na e'noe, nehuno ana avontafera kini ne'mofo avuga hampri'ne.
11 Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé òfin, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya.
Hagi kini ne' Josaia'ma kasege avontafepinti nanekema nentahino'a, zaza kukena'a tagato tagutu hu'ne.
12 Ó pa àṣẹ yìí fún Ahikamu àlùfáà, Hilkiah ọmọ Ṣafani, Akbori ọmọ Mikaiah, àti Ṣafani akọ̀wé àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba.
Hagi anante Pristi ne' Hilkiama, Safani nemofo Ahikamuma, Makaia nemofo Akborima, avontafe'ma negrea ne' Safanine, kini ne'mofo eri'za ne' Aisaianena kehige'za azageno hankave nanekea amanage huno huzmante'ne.
13 “Lọ, ẹ béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi àti fún àwọn ènìyàn àti fún gbogbo Juda nípa ohun tí a kọ sínú ìwé yìí tí a ti rí. Títóbi ni ìbínú Olúwa tí ó ń jó sí wa nítorí àwọn baba wa kò tẹ̀lé ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí; wọn kò ṣe ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ níbẹ̀ nípa wa.”
Ra Anumzamo'a nagri'ene ana maka Juda vahe'motagura tusi arimpa aherante'negahie. Na'ankure tagrira tagehe'za ama kasege avontafepima tagriku'ma huno krente'nea nanekea amagera onte'naze. E'ina hu'negu tamagra vutma Ra Anumzamofontega nunamu hinkeno, maka kasegemo hu'nea kante amage anteta na'a hugahumpi tasamino.
14 Hilkiah àlùfáà, Ahikamu àti Akbori Ṣafani pẹ̀lú Asaiah, lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin Hulda láti lọ bá a sọ̀rọ̀, ẹni tí ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tikfa ọmọ Harhasi alábojútó ibi ìpa aṣọ mọ́ sí. Ó ń gbé ní Jerusalẹmu ní ìdàkejì.
Hagi pristi ne' Hilkia'ma, Ahikamu'ma, Akbori'ma, Safani'ene Asaia'ma hu'za, kinimofo kukenama nentaza nonte kva nehia ne' Harhasi negeho Tikva nemofo Salumu nenaro kasnampa a' Hulda'ma mani'nerega, kenaku Jerusalemi kumamofona mago kaziga vu'naze.
15 Ó wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Sọ fún ọkùnrin tí ó rán an yín sí mi,
Anante Hulda'a amanage huno zamasami'ne, Ra Anumzana Israeli vahe'mota Anumzamo'a amanage huno hie. Tamagri'ma huramantegetama nagrite'ma e'naza nera amanage hutma ome asamiho,
16 ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Èmi yóò mú ibi wá sí ibí àti àwọn ènìyàn rẹ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú ìwé tí ọba Juda ti kà.
Ra Anumzamo'a huno, Nagra ama avontafepima kre'naza nanekema Juda kini ne'mo'ma hampri'nea nanekea, ana maka amage ante'na, amama mani'naza kuma'ene, vahe'enena tusi'a knazanteti zamazeri havizantfa hugahue.
17 Nítorí tí wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n sì tún sun tùràrí fún ọlọ́run mìíràn. Wọ́n sì mú mi bínú nípa gbogbo àwọn òrìṣà tí wọ́n ti fi ọwọ́ wọn dá. Ìbínú mi yóò ru sí ibí yìí, kì yóò sì rọlẹ̀.’
Na'ankure zamagra Juda vahe'mo'za Nagrira zamefi hunami'za, havi anumzante monora hunente'za, zamagrama zamazanteti tro hu'naza zantaminte mnanentake'za kre mna vunte'naze. Anama hazazamo nazeri narimpa hazankino, ana narimpa ahezamo'a vagaoregahie.
18 Sọ fún ọba Juda tí ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí nípa ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí ìwọ ti gbọ́.
Hagi Ra Anumzamofo antahintahigu'ma huramantegetama e'naza Juda kini nera, avontafepinti nanekema hamparizageno'ma antahi'nea zamofo kaziga, Israeli vahe Ra Anumzamo'a amanage hie hutma ome asamiho.
19 Nítorí tí ọkàn rẹ rọ̀, tí ìwọ sì ti rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa, nígbà tí ìwọ gbọ́ èyí tí mo sọ sí ibí yìí àti sí àwọn ènìyàn rẹ pé wọn yóò di ahoro àti ẹni ègún tí ìwọ sì fa aṣọ ọ̀ rẹ ya pẹ̀lú níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ, ni Olúwa wí.
Nagra amama mani'naza kuma'ene vahe'enena, knazanteti zamazeri haviza nehu'na, kazusi huntegahuema hu'noa nanekema nentahinka, Ra Anumzamo'na navure'ma kavufga anteneraminka, zaza kukenakama tagato tagutu nehunka zavi'ma ate'nana kavunura tamagerfa hu'na hago ke'noe huno Ra Anumzamo'a hu'ne.
20 Nítorí náà èmi yóò kó ọ jọ sí ọ̀dọ̀ àwọn baba à rẹ, a ó sì sin ọ́ ní àlàáfíà. Ojú rẹ kì yóò rí gbogbo àwọn ibi tí èmi yóò mú wá bá ibí yìí.’” Bẹ́ẹ̀ wọ́n mú èsì rẹ̀ padà tọ ọba wá.
E'ina hu'negu kagrira katrenugenka kafahe'zama nehazaza hunka frigahane. Anama hananke'za karimpa frune asegantesnagenka, ana knazama Juda vahe'ma zamisua knazana kagra onkegahane. Hagi ana kasnampa a'mo'ma anankema hutege'za, anankea eri'za kini nete vu'naze.

< 2 Kings 22 >