< 2 Kings 21 >
1 Manase jẹ́ ẹni ọdún méjìlá nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ìjọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún márùndínlọ́gọ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Hẹfisiba.
Ma: na: se da lalelegele, ode fagoyale esalu, ea Yuda ouligibi bai muni hamoi. E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, Yuda fi ode 55 agoanega ouligilalu.
2 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa, ó sì tẹ̀lé iṣẹ́ ìríra tí àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Ma: na: se da Hina Godema wadela: le hamoi. Ga: ina: ne sogega musa: esalebe fi da baligili gogosiasu wadela: i hou hamobeba: le, Isala: ili dunu da Ga: ina: ne soge golili sa: ili, gusuba: i ahoanoba, Hina Gode da Ga: ina: ne fi gadili sefasi. Be Ma: na: se da amo fi ilia wadela: idafa hou amoma fa: no bobogesu.
3 Ó sì tún ibi gíga tí baba rẹ̀ Hesekiah tí ó parun kọ́. Ó sì tún gbé pẹpẹ Baali dìde, ó sì ṣe ère òrìṣà Aṣerah, gẹ́gẹ́ bí Ahabu ọba Israẹli ti ṣe. Ó sì tẹríba sí gbogbo ogun ọ̀run, ó sì ń sìn wọ́n.
E da ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu sogebi, amo ea ada Hesegaia da wadela: lesi, Ma: na: se da bu buga: le gagui. E da Ba: ilema nodone sia: ne gadomusa: , oloda bagohame gagui. E da Isala: ili hina bagade A: iha: be ea hou defele, ogogosu uda ‘gode’ Asila e agoaila hahamoi. Amola Ma: na: se da gasumunima nodone sia: ne gadoi.
4 Ó sì kọ́ pẹpẹ nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa, èyí tí Olúwa ti sọ pé, “Ní Jerusalẹmu ni èmi yóò kọ orúkọ mi sí.”
E da ogogosu ‘gode’ ilia oloda Debolo Diasu ganodini gagui. Hina Gode da musa: hamoma: ne sia: i, amo da Debolo Diasu ganodini, dunu da Ema fawane nodone sia: ne gadosu hamoma: ne sia: i.
5 Ní àgbàlá méjèèjì ilé Olúwa, ó sì kọ́ pẹpẹ fún gbogbo àwọn ìrúbọ nínú ilé, ṣe iṣẹ́ àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó sì béèrè lọ́wọ́ àwọn òkú àti àwọn oṣó. Ó sì ṣe ọ̀pọ̀ búburú ní ojú Olúwa, ó sì mú un bínú.
Debolo Diasu gagoi aduna ganodini, e da oloda amo gasumunima nodone sia: ne gadomusa: gagui.
6 Ó fi àwọn ọmọ ara rẹ̀ rú ẹbọ nínú iná, ó ń ṣe àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó sì ń lo àlúpàyídà, ó sì ń bá àwọn òku àti oṣó lò. Ó ṣe ọ̀pọ̀ ohun búburú ní ojú Olúwa láti mú un bínú.
E da ogogosu ‘gode’ma egefe amo gobele sali. E da wadela: i ba: la: lusu hou hamosu. E da wamuni dawa: su hou hamosu amola gesami dasu ilia fada: i sia: nabalusu. E da Hina Godema bagadewane wadela: le hamobeba: le, Hina Gode da ougi ba: i.
7 Ó sì gbé ère fínfín òrìṣà Aṣerah tí ó ti ṣe, ó sì gbé e sínú ilé Olúwa, èyí tí Olúwa ti sọ fún Dafidi àti sí ọmọ rẹ̀ Solomoni, “Nínú ilé Olúwa yìí àti ní Jerusalẹmu, tí èmi ti yàn jáde lára gbogbo ẹ̀yà Israẹli, èmi yóò kọ orúkọ mi títí láéláé.
E da wadela: i uda ‘gode’ Asila loboga hamoi agoaila, amo Debolo Diasu ganodini ligisi. Be Hina Gode da musa: Da: ibidi amola Da: ibidi ea mano Soloumane elama amane sia: i, “Guiguda: Yelusaleme ganodini, Na da amo Debolo ganodini sogebi ilegei. Amo sogebiga fawane, Isala: ili fi fagoyale gala da Nama fawane nodone sia: ne gadoma: ne, Na da ilegei.
8 Èmi kò ní jẹ́ kí ẹsẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli yẹ̀ kúrò láti ilẹ̀ tí èmi fi fún àwọn baba ńlá wọn tí ó bá jẹ́ wí pé wọn yóò ṣe àkíyèsí láti ṣe gbogbo ohun tí èmi ti paláṣẹ fún wọn kí wọn sì pa gbogbo òfin tí ìránṣẹ́ mi Mose fi fún wọn mọ́.”
Isala: ili fi dunu da Na hamoma: ne sia: i huluane nabawane hamosea, amola sema amo Na da Na hamosu dunu Mousesegili i, amo huluane ilia nabawane hamosea, Na da ili, amo soge Na da ilia aowalalima i, amoga enoga gadili sefasima: ne, logo hamedafa doasimu.”
9 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kò tẹ́tí. Manase tàn wọ́n síwájú, bẹ́ẹ̀ ni kí wọ́n lè ṣe búburú ju gbogbo orílẹ̀-èdè tí Olúwa tí parun níwájú àwọn ọmọ Israẹli lọ.
Be Yuda fi dunu da Hina Gode Ea sia: nabawane hame hamosu. Amola Ma: na: se da ilia wadela: i hou (amo da musa: Ga: ina: ne fi da bagadewane wadela: le hamobeba: le, Isala: ili dunu da gusuba: i heda: loba, Hina Gode da Ga: ina: ne fi gadili sefasi) amo wadela: i hou baligili hamoma: ne, Ma: na: se da Yuda fi oule asi.
10 Olúwa sì wí nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì pé,
Hina Gode da ea hawa: hamosu balofede dunu ilimadili amane sia: i,
11 “Manase ọba Juda ti ṣe ẹ̀ṣẹ̀ ohun ìríra. Ó ti ṣe ohun búburú jùlọ ju àwọn ará Amori lọ ẹni tí ó ti wà ṣáájú rẹ̀ tí ó sì ti ṣáájú Juda sínú ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú àwọn ère rẹ̀.
“Hina bagade Ma: na: se da amo gogosiasu, wadela: idafa hou hamoi dagoi. E da Ga: ina: ne dunu ilia wadela: i hou bagadewane baligi. E da ogogosu ‘gode’ loboga hamoiba: le, Yuda dunu wadela: le hamoma: ne oule asi dagoi.
12 Nítorí náà èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, wí, Èmi le è lọ mú irú ibi báyìí wá sórí Jerusalẹmu àti Juda kí gbogbo etí olúkúlùkù tí ó gbọ́ nípa rẹ̀ le è hó.
Amaiba: le, Na, Isala: ili fi ilia Hina Gode, Na da Yuda fi amola Yelusaleme fi ilima gugunufinisisu bagadedafa iasimu. Amola eno fifi asi gala da amo hou nababeba: le, bagadewane fofogadigiba: le, sidimu agoai ba: mu.
13 Èmi yóò sì nà okùn ìwọ̀n kan tí a lò lórí Jerusalẹmu àti lórí Samaria àti òjé ìdiwọ̀n ti a lò lórí ilé Ahabu. Èmi yóò sì nu Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí ọkàn tí ń nu àwokòtò nù tí o ń nù un tí o sì ń dorí rẹ̀ kodò.
Na da Samelia fi amola Isala: ili hina bagade A: iha: be amola egaga fi ilima se dabe iasu, amo defele Na da Yelusaleme fi ilima se dabe imunu. Na da Yelusaleme fi dunu huluanedafa fadegale fasimu. Amola fedege agoane, Yelusaleme da yaeya amo da dodofele, doga: le dagole, delegili fasi dagoi agoai ba: mu.
14 Èmi yóò sì kọ ìyókù àwọn ìní mi sílẹ̀ èmi yóò sì kó wọn lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́. Wọn yóò sì di ìkógun àti ìjẹ fún gbogbo àwọn ọ̀tá wọn,
Na da dunu hame bogoi esalebe, amo yolesimu. Na da ili ha lai dunu, ilia gagulaligima: ne ilima imunu. Ilia ha lai da ili hasalalu, ilia liligi huluane lale, amola ilia soge wadela: lesimu.
15 nítorí pé wọ́n ti ṣe búburú ní ojú mi, wọ́n sì ti mú mi bínú láti ọjọ́ tí baba ńlá wọn ti jáde wá láti Ejibiti títí di òní yìí.”
Na fi dunu da Nama wadela: le hamoi, amola ilia aowalali da Idibidi soge fisili, gadili asili, amogainini wali eso, ilia da Na ougima: ne hamobeba: le, Na da amo se dabe ilima imunu.”
16 Pẹ̀lúpẹ̀lú, Manase pẹ̀lú ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ púpọ̀ tí ó kún Jerusalẹmu láti ìkangun dé ìkangun ní ẹ̀gbẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti mú Juda ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni, kí wọ́n lè ṣe ohun búburú ní ojú Olúwa.
Ma: na: se da molole hamosu dunu bagohame medole legeiba: le, Yelusaleme logoga maga: me da hano logoga, hano ahoabe amo defele ba: i. Amolawane, e da Yuda fi dunu loboga hamoi ‘gode’ma nodone sia: ne gadomusa: oleleiba: le, e da ili Hina Godema wadela: le hamoma: ne oule asi.
17 Ní ti iṣẹ́ ìyókù ti ìjọba Manase, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, àti fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀, ṣé wọ́n kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn àwọn ọba Juda?
Ma: na: se ea hawa: hamonanu eno amola ea wadela: i hou hamonanu eno huluane da “Yuda hina bagade Ilia Hawa: Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
18 Manase sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ wọ́n sì sin ín nínú ọgbà ààfin rẹ̀, ọgbà Ussa. Amoni ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Ma: na: se da bogole, hina bagade diasu bega: ifabi (Asaia ea ifabi) amo ganodini uli dogone sali. Egefe A: mone da e bagia, Yuda hina bagade hamoi.
19 Amoni jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó jẹ ọba. Orúkọ màmá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Meṣulemeti ọmọbìnrin Harusi: ó wá láti Jotba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún méjì.
A: mone da lalelegele, ode 22 agoane esalu, muni Yuda hina bagade hamoi. E da Yelusaleme ganodini esala, ode aduna fawane Yuda fi ouligilalu. Ea ame da Misialemede (Halase ea idiwi. E da Yodeba moilaiga misi dunu.)
20 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa àti gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ Manase ti ṣe.
A: mone da ea ada Ma: na: se defele, Hina Godema wadela: i hou hamosu.
21 Ó rìn ní gbogbo ọ̀nà baba rẹ̀: Ó sì ń sin àwọn ère tí baba rẹ̀ ń sìn, ó sì ń tẹrí rẹ̀ ba fún wọn.
E da ea ada ea hou amoma fa: no bobogele, loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ilima ea ada nodone sia: ne gadoi, e amolawane ilima nodone sia: ne gadosu.
22 Ó sì kọ Olúwa Ọlọ́run baba rẹ̀ sílẹ̀ kò sì rìn ní ọ̀nà ti Olúwa.
E da Hina Gode (ea aowalali ilia Gode) amo higale, Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i nabawane hame hamosu.
23 Àwọn ìránṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ lórí rẹ̀ wọ́n sì lu ọba pa ní àárín ilé rẹ̀.
A: mone ea eagene ouligisu dunu ilia da e medoma: ne, wamo sia: dasu. Amola ilia da hina bagade diasu ganodini, e medole legei dagoi.
24 Nígbà náà àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pa gbogbo àwọn tí ó dìtẹ̀ sí ọba Amoni, wọ́n sì fi Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ní ààyè rẹ̀.
Yuda fi dunu da A: mone fasu dunu medole legei. Amola ea mano Yousaia da e bagia hina bagade hamoi.
25 Àti gẹ́gẹ́ bí ìyókù iṣẹ́ ti ìjọba Amoni àti ohun tí ó ṣe, ṣé wọn kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn àwọn ọba Juda?
A: mone ea hawa: hamonanu eno huluane da, “Yuda hina bagade Ilia Hawa: Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
26 Wọ́n sì sin ín sínú isà òkú nínú ọgbà Ussa. Josiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A: mone da Asaia ea ifabi sogebi amo ganodini uli dogone sali ba: i. Egefe Yousaia da e bagia, Yuda hina bagade hamoi.