< 2 Kings 20 >
1 Ní ayé ìgbà wọ̀n-ọn-nì Hesekiah ṣe àìsàn ó sì wà ní ojú ikú. Wòlíì Isaiah ọmọ Amosi lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ: tún ilé rẹ ṣe, ṣùgbọ́n ìwọ yóò kú; o kò ní í gbádùn.”
Amogalu, hina bagade Hesegaia da olo madelale, gadenenewane bogoi. Balofede dunu Aisaia (A: imose egefe) da e ba: la asili, ema amane sia: i, “Hina Gode da amane sia: sa, ‘Dia liligi huluane noga: le momagema. Bai di da hame uhimu. Di bogomuba: le momagema!’”
2 Hesekiah yí ojú rẹ̀ padà sí ògiri ó sì gbàdúrà sí Olúwa pé,
Hesegaia da delegili, dobea feiya ba: le ganone, amane sia: ne gadoi,
3 “Rántí, Olúwa mi, bí èmi ṣe rìn níwájú rẹ àti pẹ̀lú bí èmi ṣe jẹ́ olóòtítọ́ àti pẹ̀lú gbogbo ọkàn ìfọkànsìn mi tí èmi sì ti ṣe ohun tí ó dára níwájú rẹ.” Hesekiah sọkún kíkorò.
“Hina Gode! Dia na bu dawa: ma! Na da mae fisili, Dia hawa: molole hamonanu. Na da Dia hanai amo noga: le hamomusa: dawa: i galu.” Amalalu, e da muni ha: giwane dinanu.
4 Kí ó tó di wí pé Isaiah jáde kúrò ní àárín àgbàlá ààfin, ọ̀rọ̀ Olúwa wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé:
Aisaia da hina bagade yolesi. Be e da ahoanoba, hina bagade diasu dogoa gagoi mae baligili, Hina Gode da ema sinidigima: ne sia: i.
5 “Lọ padà kí o sì sọ fún Hesekiah, olórí àwọn ènìyàn mi pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run baba rẹ Dafidi sọ: Mo ti gbọ́ àdúrà rẹ mo sì ti rí omijé rẹ, Èmi yóò wò ọ́ sàn. Ní ọjọ́ kẹta láti ìsinsin yìí, ìwọ yóò lọ sókè ilé tí a kọ́ fún Olúwa.
Hina Gode da Aisaiama amane sia: i, “Na fi ouligisu dunu Hesegaia, ema buhagili, Na sia: ema amane sia: sima, ‘Na, Hina Gode, dia siba aowa Da: ibidi ea Gode, Na da dia sia: ne gadosu nabi amola dia dibi si hano ba: i dagoi. Na da di uhinisimu, amola eso udiana da asili, di da Debolo diasuga masunu.
6 Èmi yóò fi ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún kún ọjọ́ ayé rẹ. Èmi yóò sì gbà ọ́ àti ìlú ńlá yìí láti ọwọ́ ọba Asiria. Èmi yóò sì dáàbò bo ìlú yìí nítorí ti èmi tìkára mi àti nítorí ti Dafidi ìránṣẹ́ mi.’”
Na da di ode 15eno esaloma: ne, logo doasimu. Na da Asilia hina bagade amo di amola Yelusaleme fi amo mae hasalasima: ne hamomu. Na da Yelusaleme gaga: mu. Bai Na da osobo bagade dunu da Nama nodomu Na hanai, amola Na da musa: Na hawa: hamosu dunu Da: ibidima dafawane ilegele sia: i.”
7 Nígbà náà ni Isaiah wí pé, “Mú odidi ọ̀pọ̀tọ́.” Wọ́n sì mú un, wọ́n sì fi lé oówo náà, ara rẹ̀ sì yá.
Amalalu, Aisaia da hina bagade ea ouligisu dunu ilima, ilia da figi fage daga: i, amo ea dului da: iya legema: ne sia: i. Amalalu, e da uhi dagoi ba: mu, e sia: i.
8 Hesekiah sì béèrè lọ́wọ́ Isaiah pé, “Kí ni yóò jẹ́ àmì pé Olúwa yóò wò mí sàn àti wí pé èmi yóò lọ sókè sí ilé tí a kọ́ fún Olúwa láti ọjọ́ kẹta títí di òní?”
Hina bagade Hesegaia da amane sia: i, “Na da Hina Gode da na uhini, eso udiana asili na da Debolo diasuga masunu, amo na da dafawaneyale dawa: ma: ne, dawa: digima: ne olelesu nama olelema.”
9 Isaiah dáhùn pé, “Èyí ni àmì tí Olúwa fún ọ wí pé Olúwa yóò ṣe ohun tí ó ti ṣe ìlérí: kí òjìji lọ síwájú ìgbésẹ̀ mẹ́wàá, tàbí kí ó padà lọ ní ìgbésẹ̀ mẹ́wàá?”
Aisaia da bu adole i, “Hina Gode da di Ea ilegele sia: i amo dafawaneyale dawa: ma: ne, dima dawa: digima: ne olelesu imunu. Di da adi hanabela: ? Baba da fa: gu da: iya eso ba: su amoga fa: gu bululufai nabuane bobaligila gusu masa: bela: ? o fa: gu bubulufai nabuane amo bobaligila guma: masa: bela: ?”
10 “Ó jẹ́ ohun ìrọ̀rùn fún òjìji láti lọ síwájú ìgbésẹ̀ mẹ́wàá,” Hesekiah wí pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, jẹ́ kí ó lọ padà ní ìgbésẹ̀ mẹ́wàá.”
Hesegaia da bu adole i, “Baba da fa: gu bubulufai nabuane amo bobaligila gusu masunu da asaboi fawane. Di da amo bu bobaligila guma: masa: ne hamoma!”
11 Nígbà náà wòlíì Isaiah ké pe Olúwa, Olúwa sì ṣe òjìji padà sí ìgbésẹ̀ mẹ́wàá ó ti sọ̀kalẹ̀ ní òpópó ọ̀nà Ahasi.
Aisaia da Hina Godema sia: ne gadobeba: le, Hina Gode da hina bagade A: ihase ea hahamoi fa: gu ea baba amo da bubulufai nabuane gala, amo bobaligila bu guma: buhagima: ne hamoi dagoi.
12 Ní àkókò náà ni Merodaki-Baladani ọmọ Baladani ọba Babeli ránṣẹ́ ìwé àti ẹ̀bùn sí Hesekiah nítorí tí ó ti gbọ́ nípa àìsàn Hesekiah.
Amogalu agoane, Ba: bilone hina bagade Milouda: ge Ba: lada: ne (Ba: lada: ne egefe) da hina bagade Hesegaia ea oloi nababeba: le, ema meloa dedene amola hahawane iasu liligi ema iasi.
13 Hesekiah gba ìránṣẹ́ náà ó sì fihàn wọ́n, gbogbo ohun tí ó wà nínú ilé ìṣúra—sílífà, àti wúrà, àti tùràrí, àti òróró dáradára àti ìhámọ́ra àti gbogbo èyí tí a rí lára ìṣúra rẹ̀. Kò sí nǹkan nínú ààfin rẹ̀ tàbí nínú gbogbo ìjọba rẹ̀ tí Hesekiah kò sì fihàn wọ́n.
Hesegaia da sia: adola ahoasu dunu ili hahawane yosia: le, ea gagui liligi huluane ilima olelei. E da ea silifa amola gouli, ea ha: i fodole nasu amola gabusiga: manoma amola ea dadi gagui wa: i ilia gegesu liligi huluanedafa ea ouligibi soge amo ganodini amola liligi ligisisu diasu huluane amo ganodini modaligi, amo ilima olelei.
14 Nígbà náà Isaiah wòlíì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Hesekiah ó sì béèrè pé, “Kí ni àwọn ọkùnrin náà sọ, àti níbo ni wọ́n ti ń bọ̀ wá?” “Láti ìlú jíjìn réré,” Hesekiah dáhùn. “Wọ́n wá láti Babeli.”
Amalalu, balofede dunu Aisaia da hina bagade Hesegaiama asili, amane adole ba: i, “Amo dunu da habidili misibala: ? Amola ilia da dima adi sia: bela: ?” Hesegaia da bu adole i, “Ilia da soge sedagaga misi. Ilia da Ba: bilone sogega ninima misi.”
15 Wòlíì náà béèrè pé, “Kí ni wọ́n rí ní ààfin rẹ?” “Wọ́n rí gbogbo nǹkan ní ààfin mi,” Hesekiah wí pé. “Kò sí nǹkan kan lára àwọn ìṣúra tí èmi kò fihàn wọ́n.”
Aisaia da amane adole ba: i, “Ilia da hina bagade diasu ganodini, adi liligi ba: bela: ?” Hesegaia da ema bu adole i, “Ilia da liligi huluanedafa ba: i dagoi. Liligi huluanedafa, liligi ligisisu sesei ganodini dialebe, amo na da ilima olelei.”
16 Nígbà náà Isaiah wí fún Hesekiah pé, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa,
Amalalu, Aisaia da hina bagadema amane sia: i, “Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa,
17 àkókò náà yóò sì dé nítòótọ́ nígbà tí gbogbo ohun tí ó wà ní ààfin àti gbogbo ohun tí baba rẹ̀ ti kó pamọ́ sókè títí di ọjọ́ òní, wọn yí ó gbe lọ sí Babeli, kò sí ohun tí yóò kù, ni Olúwa wí.
‘Eso da doaga: mu, amoga liligi huluanedafa dia hina bagade diasu ganodini diala, amo liligi huluane dia siba aowa ilia ligisisi, amo huluanedafa Ba: bilone sogega gaguli asi dagoi ba: mu. Liligi guiguda: dialebe afae hame ba: mu.
18 Àti díẹ̀ nínú àwọn ìran rẹ, ẹran-ara rẹ àti ẹ̀jẹ̀, tí wọn yóò bí fún ọ, ni wọn yóò kó lọ, wọn yóò sì di ìwẹ̀fà ní ààfin ọba Babeli.”
Dia fidafa amoga fifi misi dunu mogili da mugululi gaguli asi ba: mu. Ili da gulusu danane, udigili hawa: hamosu dunu Ba: bilone hina bagade ea diasu ganodini hamonanebe ba: mu.”
19 Hesekiah wí fún Isaiah pé. “Rere ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ìwọ sọ.” Nítorí ó rò wí pé, “Kò ha dára àlàáfíà àti òtítọ́ ní ọjọ́ ayé mi?”
Hina bagade Hesegaia da amo sia: nababeba: le, e da esaleawane, olofosu amola gaga: su fawane ba: mu, amo dawa: i. Amaiba: le, e da amane adole i, “Defea! Hina Gode Ea sia: adosi di nama i, amo da noga: i!”
20 Ní ti àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tókù nípa ìjọba Hesekiah, gbogbo ohun tí ó ṣe tan àti bí ó ti ṣe adágún omi àti ọ̀nà omi náà nípa èyí tí ó gbé wá omi sínú ìlú ńlá, ṣé wọn kò kọ wọ́n sínú ìwé ìgbésẹ̀ ayé àwọn ọba àwọn Juda?
Hina bagade Hesegaia ea hamonanu eno huluane, ea nimi gesa: i hawa: hamosu, amola e da hano dialoma: ne hihiga: i amola osoboha logo amola moilai ganodini hano yogo sa: ima: ne gagui, amo huluane da “Yuda hina bagade Ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
21 Hesekiah sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀: Manase ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Hesegaia da bogoi, amola egefe Ma: na: se da e bagia Yuda hina bagade hamoi.