< 2 Kings 2 >

1 Nígbà tí Olúwa ń fẹ́ gbé Elijah lọ sí òkè ọ̀run nínú àjà, Elijah àti Eliṣa wà ní ọ̀nà láti Gilgali.
Kad nu Tas Kungs Eliju vētrā gribēja uzņemt debesīs, tad Elija ar Elišu gāja no Gilgalas.
2 Elijah wí fún Eliṣa pé, “Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ sí Beteli.” Ṣùgbọ́n Eliṣa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti dájú pé Olúwa wà láyé àti gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ sí Beteli.
Un Elija sacīja uz Elišu: paliec jel šeitan, jo Tas Kungs mani sūtījis uz Bēteli. Bet Eliša sacīja: tik tiešām kā Tas Kungs dzīvs un tava dvēsele dzīva, es tevi neatstāšu.
3 Àwọn ọmọ wòlíì ní Beteli jáde wá sí ọ̀dọ̀ Eliṣa wọ́n sì béèrè pé, “Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olúwa yóò gba ọ̀gá rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?” “Bẹ́ẹ̀ ni, èmi mọ̀,” Eliṣa dáhùn, “Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀.”
Un kad tie gāja uz Bēteli, tad tie praviešu bērni, kas bija Bētelē, izgāja pie Elišas un uz to sacīja: vai tu zini, ka Tas Kungs šodien tavu kungu paņems no tavas galvas? Un viņš sacīja: zinu gan, esiet tikai klusu!
4 Nígbà náà Elijah sì wí fún un pé, “Dúró níbí, Eliṣa: Olúwa ti rán mi lọ sí Jeriko.” Ó sì dá a lóhùn pé, “Bí ó ti dájú pé Olúwa yè àti tí ìwọ náà yè, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Wọ́n sì jọ lọ sí Jeriko.
Un Elija uz to sacīja: Eliša, paliec jel šeitan, jo Tas Kungs mani sūtījis uz Jēriku. Bet tas sacīja: tik tiešām kā Tas Kungs dzīvs un tava dvēsele dzīva, es tevi neatstāšu. Tā tie gāja uz Jēriku.
5 Àwọn ọmọ wòlíì tí ó wà ní Jeriko sì gòkè tọ Eliṣa wá wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé ìwọ mọ̀ wí pé Olúwa yóò gba ọ̀gá rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?” “Bẹ́ẹ̀ ni, èmi mọ̀,” Ó dá wọn lóhùn, “Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe sọ nípa rẹ̀.”
Tad tie praviešu bērni, kas bija Jērikū, piegāja pie Elišas un uz to sacīja: vai tu zini, ka Tas Kungs tavu kungu šodien paņems no tavas galvas? Un tas sacīja: zinu gan, esiet tikai klusu!
6 Nígbà náà Elijah wí fún un pé, “Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ sí Jordani.” Ó sì dá a lóhùn pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti jẹ́ wí pé, Olúwa yè àti gẹ́gẹ́ bí o ti yè, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn méjèèjì sì jọ ń lọ.
Tad Elija uz to sacīja: paliec jel šeitan, jo Tas Kungs mani sūtījis pie Jardānes. Bet tas sacīja: tik tiešām kā Tas Kungs dzīvs un tava dvēsele dzīva, es tevi neatstāšu. Tā tie gāja abi divi.
7 Àádọ́ta àwọn ọkùnrin ọmọ wòlíì sì lọ láti lọ dúró ní ọ̀nà jíjìn, wọ́n sì kọ ojú da ibi tí Elijah àti Eliṣa ti dúró ní Jordani.
Un piecdesmit vīri no praviešu bērniem gāja un nostājās iepretim no tālienes; un tie abi stāvēja pie Jardānes.
8 Elijah sì mú agbádá ó sì ká a sókè ó sì lu omi náà pẹ̀lú rẹ̀. Omi náà sì pín sí ọ̀tún àti sí òsì, àwọn méjèèjì sì rékọjá lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Tad Elija ņēma savu mēteli un to satina un sita ūdenī, un tas dalījās uz abējām pusēm, ka tie abi gāja cauri sausām kājām.
9 Nígbà tí wọ́n rékọjá, Elijah sì wí fún Eliṣa pé, “Sọ fún mi, kí ni èmi lè ṣe fún ọ kí ó tó di wí pé wọ́n gbà mí kúrò lọ́dọ̀ rẹ?” “Jẹ́ kí èmi kí ó jogún ìlọ́po méjì ẹ̀mí rẹ.” Ó dá a lóhùn.
Kad tie nu bija cauri izgājuši, tad Elija sacīja uz Elišu: lūdz, ko man tev būs darīt, pirms es topu atņemts no tevis. Un Eliša sacīja: lai jel tavs gars divkārtīgā mērā ir uz manis.
10 “Ìwọ ti béèrè ohun tí ó ṣòro,” Elijah wí pé, “Síbẹ̀ tí ìwọ bá rí mi nígbà tí a bá gbà mí kúrò lọ́wọ́ rẹ, yóò jẹ́ tìrẹ bí bẹ́ẹ̀ kọ́ kò ní rí bẹ́ẹ̀.”
Un viņš sacīja: grūtu lietu tu esi lūdzis; ja tu mani redzēsi, kad es no tevis tapšu atņemts, tad tas tev tā notiks, bet ja ne, tad tas nenotiks.
11 Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń rìn lọ tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ pọ̀, lọ́gán kẹ̀kẹ́ iná àti ẹṣin iná yọ sí wọn ó sì ya àwọn méjèèjì nípa, Elijah sì gòkè lọ sí ọ̀run pẹ̀lú àjà.
Un šiem tā ejot un runājot, redzi, ugunīgi rati un ugunīgi zirgi nāca, kas tos abus šķīra. Tā Elija aizbrauca vētrā uz debesīm.
12 Eliṣa rí èyí ó sì kígbe sókè, “Baba mi! Baba mi! Kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin Israẹli!” Eliṣa kò sì rí i mọ́. Ó sì mú aṣọ ara rẹ̀ ó sì fà wọ́n ya sọ́tọ̀.
Un Eliša to redzēja un brēca: mans tēvs, mans tēvs! Israēla rati un viņa jātnieki! Un viņš to vairs neredzēja. Un viņš sagrāba savas drēbes un tās saplēsa divos gabalos.
13 Ó sì mú agbádá tí ó ti jábọ́ láti ọ̀dọ̀ Elijah ó sì padà lọ, ó sì dúró lórí bèbè Jordani.
Un viņš pacēla Elijas mēteli, kas tam bija nokritis, un griezās atpakaļ un stāvēja Jardānes malā.
14 Ó sì mú agbádá náà tí ó jábọ́ láti ọwọ́ rẹ̀, ó sì lu omi pẹ̀lú rẹ̀. “Níbo ni Olúwa Ọlọ́run Elijah wà?” Ó béèrè. Nígbà tí ó lu omi náà, ó sì pín sí apá ọ̀tún àti sí òsì, Eliṣa sì rékọjá.
Un viņš ņēma Elijas mēteli, kas tam bija nokritis, un sita to ūdeni un sacīja: kur nu Viņš, Tas Kungs, Elijas Dievs? Un viņš sita to ūdeni, un tas dalījās uz abējām pusēm, un Eliša gāja cauri.
15 Àwọn ọmọ wòlíì láti Jeriko, tí wọ́n ń wò, wí pé, “Ẹ̀mí Elijah sinmi lé Eliṣa.” Wọ́n sì lọ láti lọ bá a, wọ́n sì dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀.
Kad nu tie praviešu bērni iepretim Jērikum viņu redzēja, tad tie sacīja: Elijas gars dus uz Elišas, un tie viņam gāja pretī un metās pie zemes viņa priekšā.
16 “Wò ó,” wọ́n wí pé, “Àwa ìránṣẹ́ ni àádọ́ta ọkùnrin alágbára. Jẹ́ kí wọ́n lọ láti lọ wá ọ̀gá rẹ wá. Bóyá ẹ̀mí Olúwa ti gbé e sókè, ó sì gbé e kalẹ̀ lórí òkè ńlá tàbí lórí ilẹ̀.” “Rárá,” Eliṣa dá a lóhùn pé, “Má ṣe rán wọn.”
Un tie uz viņu sacīja: redzi, starp taviem kalpiem ir piecdesmit spēcīgi vīri, lai tie iet un meklē tavu kungu: kad tik Tā Kunga Gars viņu nav paņēmis un nometis uz kādu kalnu vai kādā ielejā. Bet viņš sacīja: nesūtiet.
17 Ṣùgbọ́n wọ́n rọ̀ ọ́ títí ojú fi tì í láti gbà. Ó wí pé, “Rán wọn.” Wọ́n sì rán àádọ́ta ènìyàn tí ó wá a fún ọjọ́ mẹ́ta ṣùgbọ́n wọn kò rí i.
Bet tie vēl vairāk lūdza, kamēr palika vai kauns, un viņš sacīja: sūtiet. Un tie sūtīja piecdesmit vīrus un to meklēja trīs dienas un neatrada.
18 Nígbà tí wọ́n padà dé ọ̀dọ̀ Eliṣa, tí ó dúró ní Jeriko, ó wí fún wọn pé, “Ṣé èmi kò sọ fún un yín kí ẹ má lọ?”
Tad tie nāca atpakaļ pie viņa uz Jēriku, kur viņš bija palicis, un viņš uz tiem sacīja: vai es jums nesacīju: neejat?
19 Àwọn ọkùnrin ìlú wí fún Eliṣa, pé, “Wò ó, olúwa wa, ìtẹ̀dó ìlú yìí dára, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti rí i, ṣùgbọ́n omi náà burú, ilẹ̀ náà sì sá.”
Un tās pilsētas vīri sacīja uz Elišu: redzi jel, šās pilsētas vieta ir gan laba, kā mans kungs redz, bet ūdens ir nelāga un zeme neauglīga.
20 Ó sì wí pé, “Mú àwokòtò tuntun fún mi wá, kí o sì mú iyọ̀ sí inú rẹ̀.” Wọ́n sì gbé e wá fún un.
Un viņš sacīja: atnesiet man jaunu kausu un liekat sāli iekšā; un tie viņam to atnesa.
21 Nígbà náà ó sì jáde lọ sí ibi orísun omi, ó sì da iyọ̀ sí inú rẹ̀, ó wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Èmi ti wo omi yìí sàn. Kò ní mú ikú wá mọ́ tàbí mú ilẹ̀ náà sá.’”
Un viņš izgāja pie tā ūdens avota un iemeta tur to sāli iekšā un sacīja: tā saka Tas Kungs: es šo ūdeni esmu veselīgu darījis, no tejienes vairs nenāks ne nāve nedz neauglība.
22 Omi náà sì ti dára ni mímu títí di òní, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí Eliṣa ti sọ.
Tā tas ūdens palika veselīgs līdz šai dienai pēc Elišas vārda, ko viņš bija runājis.
23 Láti ibẹ̀ Eliṣa lọ sókè ní Beteli gẹ́gẹ́ bí ó ti ń rìn lọ lójú ọ̀nà, àwọn ọ̀dọ́ kan jáde wá láti ìlú náà wọ́n sì fi ṣe ẹlẹ́yà. “Máa lọ sókè ìwọ apárí!” Wọ́n wí pé. “Máa lọ sókè ìwọ apárí!”
Un viņš no turienes gāja uz Bēteli, un kad viņš pa ceļu uz augšu gāja, tad mazi puikas no pilsētas nāca ārā un to mēdīja un uz to sacīja: plikgalvi, nāc augšā, plikgalvi, nāc augšā!
24 Ó sì yípadà, ó sì wò wọ́n ó sì fi wọ́n bú ní orúkọ Olúwa. Nígbà náà beari méjì sì jáde wá láti inú igbó ó sì lu méjìlélógójì lára àwọn ọ̀dọ́ náà.
Un viņš apgriezās, un tos ieraudzījis viņš tos nolādēja Tā Kunga Vārdā. Tad divi lāči iznāca no meža un no tiem saplosīja četrdesmit un divus bērnus.
25 Ó sì lọ sí orí òkè Karmeli láti ibẹ̀ ó sì padà sí Samaria.
Un viņš no turienes gāja uz Karmeļa kalnu, un no turienes viņš griezās atpakaļ uz Samariju.

< 2 Kings 2 >