< 2 Kings 2 >

1 Nígbà tí Olúwa ń fẹ́ gbé Elijah lọ sí òkè ọ̀run nínú àjà, Elijah àti Eliṣa wà ní ọ̀nà láti Gilgali.
Sun pacl fal tuh LEUM GOD Elan usalak Elijah nu inkusrao in sie fohru.
2 Elijah wí fún Eliṣa pé, “Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ sí Beteli.” Ṣùgbọ́n Eliṣa wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti dájú pé Olúwa wà láyé àti gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ sí Beteli.
Ke eltal fahsr, Elijah el fahk nu sel Elisha, “Muta inse inge. LEUM GOD El sap ngan som nu Bethel.” Tusruktu Elisha el topuk, “Nga fulahk ke inse pwaye luk nu sin LEUM GOD moul, ac nu sum, lah nga ac fah tiana som liki kom.” Ouinge eltal tukeni som nu Bethel.
3 Àwọn ọmọ wòlíì ní Beteli jáde wá sí ọ̀dọ̀ Eliṣa wọ́n sì béèrè pé, “Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olúwa yóò gba ọ̀gá rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?” “Bẹ́ẹ̀ ni, èmi mọ̀,” Eliṣa dáhùn, “Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀.”
Sie un mwet palu su muta we elos som nu yorol Elisha ac siyuk sel, “Ku kom etu lah LEUM GOD El ac usla mwet kacto lom liki kom misenge?” Elisha el topuk, “Aok, nga etu. Tuh tari, kut tia sramsramkin.”
4 Nígbà náà Elijah sì wí fún un pé, “Dúró níbí, Eliṣa: Olúwa ti rán mi lọ sí Jeriko.” Ó sì dá a lóhùn pé, “Bí ó ti dájú pé Olúwa yè àti tí ìwọ náà yè, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Wọ́n sì jọ lọ sí Jeriko.
Na Elijah el fahk nu sel Elisha, “Muta inse inge. LEUM GOD El sap ngan som nu Jericho.” A Elisha el topuk, “Nga fulahk ke inse pwaye luk nu sin LEUM GOD moul, ac nu sum, lah nga ac fah tiana som liki kom.” Ouinge eltal tukeni som nu Jericho.
5 Àwọn ọmọ wòlíì tí ó wà ní Jeriko sì gòkè tọ Eliṣa wá wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé ìwọ mọ̀ wí pé Olúwa yóò gba ọ̀gá rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?” “Bẹ́ẹ̀ ni, èmi mọ̀,” Ó dá wọn lóhùn, “Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe sọ nípa rẹ̀.”
Sie un mwet palu su muta we elos som nu yorol Elisha ac siyuk sel, “Ku kom etu lah LEUM GOD El ac usla mwet kacto lom liki kom misenge?” Elisha el topuk, “Aok, nga etu. Tuh tari, kut tia sramsramkin.”
6 Nígbà náà Elijah wí fún un pé, “Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ sí Jordani.” Ó sì dá a lóhùn pé, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti jẹ́ wí pé, Olúwa yè àti gẹ́gẹ́ bí o ti yè, èmi kò ní fi ọ́ sílẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn méjèèjì sì jọ ń lọ.
Na Elijah el fahk nu sel Elisha, “Inge, kom muta inse. LEUM GOD El sap ngan som nu Infacl Jordan.” Tuh Elisha el topuk, “Nga fulahk ke inse pwaye luk nu sin LEUM GOD moul, ac nu sum, lah nga fah tiana som liki kom.” Ouinge eltal fahla na,
7 Àádọ́ta àwọn ọkùnrin ọmọ wòlíì sì lọ láti lọ dúró ní ọ̀nà jíjìn, wọ́n sì kọ ojú da ibi tí Elijah àti Eliṣa ti dúró ní Jordani.
ac mwet palu lumngaul fahsr tokoltal nwe ke Infacl Jordan. Elijah ac Elisha tui ke infacl ah, ac mwet palu lumngaul ah tu loes kutu lukeltal.
8 Elijah sì mú agbádá ó sì ká a sókè ó sì lu omi náà pẹ̀lú rẹ̀. Omi náà sì pín sí ọ̀tún àti sí òsì, àwọn méjèèjì sì rékọjá lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Na Elijah el sarukla nuknuk lik lal, lumla ac sang sringilya kof ah. Na kof ah fahsrelik, na el ac Elisha fahla nu lefahlo fin acn pao.
9 Nígbà tí wọ́n rékọjá, Elijah sì wí fún Eliṣa pé, “Sọ fún mi, kí ni èmi lè ṣe fún ọ kí ó tó di wí pé wọ́n gbà mí kúrò lọ́dọ̀ rẹ?” “Jẹ́ kí èmi kí ó jogún ìlọ́po méjì ẹ̀mí rẹ.” Ó dá a lóhùn.
Ke eltal sun lefahlo, Elijah el fahk nu sel Elisha, “Fahk nu sik lah mea kom lungse ngan oru nu sum meet liki utukla nga.” Elisha el topuk, “Ase nu sik ngan usrui ip luo ke ku lun ngunum, in akkalemye lah nga pa ac aol kom.”
10 “Ìwọ ti béèrè ohun tí ó ṣòro,” Elijah wí pé, “Síbẹ̀ tí ìwọ bá rí mi nígbà tí a bá gbà mí kúrò lọ́wọ́ rẹ, yóò jẹ́ tìrẹ bí bẹ́ẹ̀ kọ́ kò ní rí bẹ́ẹ̀.”
Elijah el fahk, “Siyuk se ingan upana in orekla. Tusruktu kom ac fah eis kom fin liyeyu ke pacl se utukla nga liki kom. A kom fin tia liyeyu, kom fah tia eis.”
11 Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń rìn lọ tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ pọ̀, lọ́gán kẹ̀kẹ́ iná àti ẹṣin iná yọ sí wọn ó sì ya àwọn méjèèjì nípa, Elijah sì gòkè lọ sí ọ̀run pẹ̀lú àjà.
Eltal fahsr na sramsram, ac in kitin pacl ah na, chariot e se, amakinyuk sin horse e, yuyak inmasrloltal twe eisal na Elijah, ac usalak nu inkusrao weak fohru se.
12 Eliṣa rí èyí ó sì kígbe sókè, “Baba mi! Baba mi! Kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin Israẹli!” Eliṣa kò sì rí i mọ́. Ó sì mú aṣọ ara rẹ̀ ó sì fà wọ́n ya sọ́tọ̀.
Elisha el liye ac wola nu sel Elijah ac fahk, “Papa, papa! Mwet loango kulana lun Israel, kom wanginla!” Ac el tiana sifilpa liyal Elijah. Elisha el seya nuknuk lik se lal nu ke ip luo, ke sripen asor lal.
13 Ó sì mú agbádá tí ó ti jábọ́ láti ọ̀dọ̀ Elijah ó sì padà lọ, ó sì dúró lórí bèbè Jordani.
Na el srukak nuknuk lik lal Elijah ma putatla lukel, ac folokla tu pe Infacl Jordan.
14 Ó sì mú agbádá náà tí ó jábọ́ láti ọwọ́ rẹ̀, ó sì lu omi pẹ̀lú rẹ̀. “Níbo ni Olúwa Ọlọ́run Elijah wà?” Ó béèrè. Nígbà tí ó lu omi náà, ó sì pín sí apá ọ̀tún àti sí òsì, Eliṣa sì rékọjá.
El sang nuknuk lik se lal Elijah ac sringilya kof ah, ac fahk, “El aya LEUM GOD, God lal Elijah?” Na el sifilpa sringilya kof ah, ac kof ah fahsrelik, na el fahla nu lefahl ngia.
15 Àwọn ọmọ wòlíì láti Jeriko, tí wọ́n ń wò, wí pé, “Ẹ̀mí Elijah sinmi lé Eliṣa.” Wọ́n sì lọ láti lọ bá a, wọ́n sì dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀.
Mwet palu lumngaul lun acn Jericho liyalak ac fahk, “Ku lal Elijah oan facl Elisha!” Elos som in osun nu sel, ac faksufi ye mutal,
16 “Wò ó,” wọ́n wí pé, “Àwa ìránṣẹ́ ni àádọ́ta ọkùnrin alágbára. Jẹ́ kí wọ́n lọ láti lọ wá ọ̀gá rẹ wá. Bóyá ẹ̀mí Olúwa ti gbé e sókè, ó sì gbé e kalẹ̀ lórí òkè ńlá tàbí lórí ilẹ̀.” “Rárá,” Eliṣa dá a lóhùn pé, “Má ṣe rán wọn.”
ac fahk, “Kut mwet lumngaul oasr inge, ac kut mwet na ku. Kut ku in som suk mwet kacto lom ah. Sahp ngun lun LEUM GOD usalla likilya fin eol uh ku ke infahlfal uh.” Elisha el topuk, “Mo. Nimet kowos som.”
17 Ṣùgbọ́n wọ́n rọ̀ ọ́ títí ojú fi tì í láti gbà. Ó wí pé, “Rán wọn.” Wọ́n sì rán àádọ́ta ènìyàn tí ó wá a fún ọjọ́ mẹ́ta ṣùgbọ́n wọn kò rí i.
Tuh elos kwafe nwe ke na el fuhlelosla elos som. Mwet lumngaul inge som sokol Elijah yen nukewa ke len tolu, tuh elos tiana konalak.
18 Nígbà tí wọ́n padà dé ọ̀dọ̀ Eliṣa, tí ó dúró ní Jeriko, ó wí fún wọn pé, “Ṣé èmi kò sọ fún un yín kí ẹ má lọ?”
Na elos folokla nu yorol Elisha, su muta soanelos in acn Jericho, ac el fahk nu selos, “Ya nga tia fahk mu kowos in tia som?”
19 Àwọn ọkùnrin ìlú wí fún Eliṣa, pé, “Wò ó, olúwa wa, ìtẹ̀dó ìlú yìí dára, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti rí i, ṣùgbọ́n omi náà burú, ilẹ̀ náà sì sá.”
Oasr kutu mwet Jericho som nu yorol Elisha ac fahk, “Kom liye na lah siti se inge siti na wowo se, tusruktu kof uh koluk, pwanang oasr na mutan pitutu ac musalla pitutu la.”
20 Ó sì wí pé, “Mú àwokòtò tuntun fún mi wá, kí o sì mú iyọ̀ sí inú rẹ̀.” Wọ́n sì gbé e wá fún un.
Elisha el fahk, “Sang kutu sohl an nu in sie pol sasu ac use nu sik.” Elos use sang nu sel,
21 Nígbà náà ó sì jáde lọ sí ibi orísun omi, ó sì da iyọ̀ sí inú rẹ̀, ó wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Èmi ti wo omi yìí sàn. Kò ní mú ikú wá mọ́ tàbí mú ilẹ̀ náà sá.’”
na el som nu ke unon in kof se we, ac sisang sohl ah nu in kof ah, ac fahk, “Pa inge ma LEUM GOD El fahk, ‘Nga aknasnasyela kof se inge, na ac fah tia sifilpa orala kutena mwet in misa ku kunausla pitutu lun mutan uh.’”
22 Omi náà sì ti dára ni mímu títí di òní, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí Eliṣa ti sọ.
Ac kof sac nasnasla oe in pacl sac me, oana ma Elisha el fahk uh.
23 Láti ibẹ̀ Eliṣa lọ sókè ní Beteli gẹ́gẹ́ bí ó ti ń rìn lọ lójú ọ̀nà, àwọn ọ̀dọ́ kan jáde wá láti ìlú náà wọ́n sì fi ṣe ẹlẹ́yà. “Máa lọ sókè ìwọ apárí!” Wọ́n wí pé. “Máa lọ sókè ìwọ apárí!”
Elisha el som liki acn Jericho nu Bethel. Ke el fahsr inkanek ah, kutu tulik mukul tuku liki sie siti srisrik ac aksruksrukel. Elos wowo ac fahk, “Tiok liki acn inge, kom mangsrasra!”
24 Ó sì yípadà, ó sì wò wọ́n ó sì fi wọ́n bú ní orúkọ Olúwa. Nígbà náà beari méjì sì jáde wá láti inú igbó ó sì lu méjìlélógójì lára àwọn ọ̀dọ́ náà.
Elisha el forla kororyak sueltalu, ac selngaweltal Inen LEUM GOD. Na bear mutan lukwa tuku inima uh me twe seseya monin angngaul luo sin tulik mukul inge.
25 Ó sì lọ sí orí òkè Karmeli láti ibẹ̀ ó sì padà sí Samaria.
Na Elisha el fahla na som nwe Fineol Carmel, ac tok el folokla nu Samaria.

< 2 Kings 2 >