< 2 Kings 19 >
1 Nígbà tí ọba Hesekiah gbọ́ èyí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya ó sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀ ó sì lọ sí àgọ́ Olúwa
Yuda hina bagade Hesegaia da ilia sia: ne iasu nababeba: le, e da ea abula gadelale, eboboi abula salawane, Hina Gode Ea Debolo diasuga asi.
2 Ó sì rán Eliakimu olùtọ́jú ààfin, Ṣebna akọ̀wé àti olórí àlùfáà gbogbo wọn sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀, sí ọ̀dọ̀ wòlíì Isaiah ọmọ Amosi.
E da Ilaiagime (hina bagade diasu ouligisu dunu), Siebena (hina bagade diasuga esalebe fi ilia sia: dedene legesu dunu) amola asigilai gobele salasu dunu amo huluane balofede dunu Aisaia (A: imose egefe) ema asunasi. Ilia amola da eboboi abula salawene asi.
3 Wọ́n sì sọ fún ún pé, “Èyí ni ohun tí Hesekiah sọ: ọjọ́ òní yí jẹ́ ọjọ́ ìpọ́njú àti ìbáwí àti ẹ̀gàn, gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí ọmọdé wá sí ojú ìbímọ tí kò sì sí agbára láti fi bí wọn.
Hesegaia da adola ahoasu dunuma Aisaiama amane sia: sima: ne sia: i, “Wali eso da se nabasu eso bagadedafa! Ninia da se iasu naba amola gogosiasu da ninima doaga: i. Ninia da uda ilia mano lalelegemu gadenesea, gasa hameba: le, mano lamu hamedei, ninia da amo agoai ba: sa.
4 Ó lè jẹ́ wí pé Olúwa Ọlọ́run yóò gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ olùdarí pápá, ẹni tí ọ̀gá rẹ̀, ọba Asiria, ti rán láti fi Ọlọ́run alààyè ṣẹ̀sín, yóò sì bá a wí fún ọ̀rọ̀ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ ti gbọ́. Nítorí náà gbàdúrà fún ìyókù àwọn tí ó wà láààyè.”
Asilia hina bagade da ea afoha ouligisu dunu amo Hina Godema gademusa: asunasi dagoi. Dia Hina Gode da amo gadesu sia: nabalu, amo gadesu sia: su dunuma se dabe imunu da defea. Amaiba: le, ninia dunu da hame bogoi esalebe, amo fidima: ne, dia Godema sia: ne gadoma.”
5 Nígbà tí ìránṣẹ́ ọba Hesekiah lọ sí ọ̀dọ̀ Isaiah,
Aisaia da hina bagade Hesegaia ea sia: si, nababeba: le,
6 Isaiah wí fún wọn pé, “Sọ fún ọ̀gá rẹ, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa sọ pé: Ẹ má ṣe bẹ̀rù ohun tí ẹ̀yin ti gbọ́—àwọn ọ̀rọ̀ ìhàlẹ̀ pẹ̀lú èyí ti ọba Asiria ti sọ̀rọ̀-òdì sí mi.
e da ema bu dabe adole ima: ne amane sia: si, “Hina Gode da dima amane sia: sa, ‘Asilia dunu da dili beda: ma: ne, Na da dili gaga: mu da hamedei sia: sa. Be ilia gasa fili sia: beba: le, mae beda: ma!
7 Gbọ́! Èmi yóò rán ẹ̀mí kan sínú rẹ̀ nígbà tí ó bá sì gbọ́ ariwo, yóò sì padà sí ìlú rẹ̀, níbẹ̀ ni èmi yóò sì gbé gé e lulẹ̀ pẹ̀lú idà.’”
Na, Hina Gode da hamobeba: le, Asilia hina bagade da beda: ma: ne udigili sia: nababeba: le, hi sogega buhagimu. Amola Na da hamobeba: le, e da amogawi medole legei ba: mu.’”
8 Nígbà tí olùdarí pápá gbọ́ wí pé ọba Asiria ti kúrò ní Lakiṣi ó sì padà ó sì rí ọba níbi ti ó gbé ń bá Libina jà.
Asilia dadi gagui ouligisu dunu afae, da Asilia hina bagade amo La: igisi moilai bai bagade fisili, eno gadenene moilai Libina amoma doagala: musa: asi, amo nababeba: le, amogawi ema fada: i sia: sia: musa: asi.
9 Nísinsin yìí, Sennakeribu sì gbọ́ ìròyìn wí pé Tirakah, ọba Etiopia ti Ejibiti wá ó sì ń yan jáde lọ láti lọ bá a jagun. Bẹ́ẹ̀ ni ó sì tún rán oníṣẹ́ sí Hesekiah pẹ̀lú ọ̀rọ̀ yìí pé,
Amola Asilia dunu da sia: amane sia: si nabi, Idioubia hina bagade da Idibidi dadi gagui dunu wa: i amo bisili, Asilia hina bagade ema doagala: musa: mana, amane sia: be nabi. Asilia hina bagade da amo sia: nababeba: le, e da Yuda hina bagade Hesegaiama meloa amane dedene iasi,
10 “Sọ fún Hesekiah ọba Juda pé, má ṣe jẹ́ kí òrìṣà tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé kí ó tàn ó jẹ nígbà tí ó wí pé, ‘Jerusalẹmu a kò ní fi lé ọwọ́ ọba Asiria.’
“Dilia ‘gode’ amo da dilia dafawaneyale dawa: sa, dilima ogogole, na da dili hame hasalimu sia: sa. Be amo ogogosu sia: mae nabima!
11 Lóòótọ́ ìwọ ti gbọ́ gbogbo ohun tí ọba Asiria tí ó ṣe sí gbogbo àwọn ìlú, ó pa wọ́n run pátápátá. Ìwọ yóò sì gbàlà?
Dilia da sia: nabi, amo Asilia hina bagade da soge fi gugunufinisimusa: sia: sea, e da dafawane gugunufinisimu. Dilia da hobeale gaga: su ba: mu, mae dawa: ma!
12 Ṣé àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè tí a ti parun láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá mi gbà wọ́n là: òrìṣà Gosani, Harani Reṣefu àti gbogbo ènìyàn Edeni tí wọ́n wà ní Teli-Assari?
Na aowalali ilia da Gousa: ne, Halane, amola Lisefe moilai huluane gugunufinisi. Amola Bede Idini fi dunu Dila: sa moilai ganodini esala, huluane medole legei. Ilia ‘gode’ da amo huluane gaga: mu hamedei ba: i.
13 Níbo ni ọba Hamati wa, ọba Arpadi, ọba ìlú Sefarfaimi, ti Hena, tàbí ti Iffa gbé wà?”
Moilai Ha: ima: de amola Aba: de, Sefafa: ime, Hina, amola Ifai, ilia hina bagade ili da habila: ?”
14 Hesekiah gba lẹ́tà láti ọ̀dọ̀ ìránṣẹ́ ó sì kà á. Nígbà náà ó sì lọ sí òkè ilé tí a kọ́ fún Olúwa ó sì tẹ́ ẹ síwájú Olúwa.
Yuda hina bagade Hesegaia da amo meloa dedei sia: adola ahoasu dunuma lale, idi. Amalalu, e da Debolo Diasuga asili, meloa amo Hina Gode Ea midadi ligisili,
15 Hesekiah gbàdúrà sí Olúwa: “Olúwa Ọlọ́run Israẹli, tí ń gbé ní àárín àwọn kérúbù, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run lórí gbogbo ìjọba tí ó wà láyé, ìwọ ti dá ọ̀run àti ayé.
amane sia: ne gadoi, “Isala: ili fi ilia Hina Gode! Di da Dia fisu da: iya, amo ougia hamoi liligi gadodili esalebe. Disu da Godedafa amola Di da fifi asi gala huluanedafa ouligisa. Disu da osobo bagade amola mu hahamoi.
16 Dẹtí sílẹ̀, Olúwa kí o sì gbọ́; la ojú rẹ, Olúwa, kí o sì rí i, gbọ́ ọ̀rọ̀ Sennakeribu tí ó rán láti fi bú Ọlọ́run alààyè.
Wali Hina Gode! Hou da ninima doaga: i ba: ma! Sena: gelibi da Di, Esalebe Godedafa, amo Dima gadele sia: be nabima!
17 “Òtítọ́ ni, Olúwa, wí pé ọba Asiria ti pa orílẹ̀-èdè wọ̀nyí run àti ilẹ̀ wọn.
Hina Gode! Ninia huluane dawa: ! Asilia hina bagade ilia da fifi asi gala bagohame gugunufinisi dagoi, amola ilia soge wadela: lesi.
18 Wọ́n ti ju òrìṣà wọn sínú iná wọn sì ti bà wọ́n jẹ́, nítorí pé wọn kì í ṣe ọlọ́run. Ṣùgbọ́n, wọ́n jẹ́ igi àti òkúta tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ pẹ̀lú ọwọ́ ènìyàn.
Ilia da amo dunu fi ilia ‘gode’ huluane laluga ulagi. (Be amo ‘gode’ ilia da ‘gode’dafa hame - ilia da osobo bagade dunu ilia loboga ifa amola gelega hamoi liligi fawane).
19 Nísinsin yìí Olúwa Ọlọ́run wa, gbà wá kúrò lọ́wọ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn ìjọba lórí ilẹ̀ ayé le mọ̀ pé ìwọ nìkan ṣoṣo ni, Olúwa Ọlọ́run wa.”
Amaiba: le, wali ninia Hina Gode! Osobo bagade fifi asi gala huluanedafa, ilia da Di, Hina Gode da Godedafa, amo ilia dawa: ma: ne, Asilia dunu da nini mae hasalima: ne, nini gaga: ma!”
20 Nígbà náà Isaiah ọmọ Amosi rán oníṣẹ́ sí Hesekiah pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ: Mo ti gbọ́ àdúrà rẹ nípa ti Sennakeribu ọba Asiria.
Amalalu, Aisaia da hina bagade Hesegaiama, Hina Gode da ema ea sia: ne gadosu amane adole ima: ne amo sia: amane sia: si,
21 Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa ti sọ nípa rẹ̀, “‘Wúńdíá ọmọbìnrin Sioni kẹ́gàn rẹ ó sì fi ọ́ ṣe ẹlẹ́yà. Ọmọbìnrin Jerusalẹmu mi orí sí ọ gẹ́gẹ́ bí o ti sálọ.
“Hina Gode da amane sia: i dagoi, ‘Sena: galibi di! Yelusaleme moilai bai bagade da diba: le oufesega: sa.
22 Ta ni ìwọ ti bú tí o sì kẹ́gàn rẹ̀? Lórí ta ni ìwọ ti gbé ohùn rẹ sókè tí ó sì gbé ojú sókè sí ọ ní ìgbéraga? Lórí ẹni mímọ́ ti Israẹli!
Di da Na, Isala: ili ilia Hadigidafa Hina Gode, Nama mae nodone, gadele sia: beba: le, di da nowa dunula: ?
23 Nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ ìwọ ti sọ̀rọ̀ búburú sí Olúwa. Tì wọ sì wí pé, “Pẹ̀lú ọ̀pọ̀ kẹ̀kẹ́ mi ni èmi sì fi dé orí àwọn òkè ńlá, sí ibi gíga jùlọ Lebanoni. Èmi a sì ké igi kedari gíga rẹ̀ lulẹ̀, àti ààyò igi firi rẹ̀. Èmi a sì lọ sí orí òkè ìbùwọ̀ rẹ̀ sínú ibi tí ó dára jù nínú igbó rẹ̀.
Di da dia adola ahoasu dunu Nama hidale, di amola dia ‘sa: liode’ fila heda: i dunu da baligili heda: i Lebanone goumi huluane hasali dagoi, amo Nama hidale sia: musa: asunasi. Di da baligili heda: i dolo ifa amola ‘saibala: se’ ifa noga: idafa abusa: le, iwiladafa amoga doaga: i, amo Nama hidale sia: i.
24 Mo ti gbẹ́ kànga ní ilẹ̀ àjèjì, mo sì mu omi níbẹ̀. Pẹ̀lú àtẹ́lẹsẹ̀ mi, èmi ti gbẹ́ gbogbo omi odò tí ó wà ní Ejibiti.”
Di da eno hidale, amo di da hano si dogone, ga fi dunu ilia soge ganodini hano dili mai, amola dia dadi gagui dunu da osa: giba: le, Naile Hano da hafoga: i dagoi ba: i, amo huluane di hidale sia: i.
25 “‘Ṣé ìwọ kò tí ì gbọ́? Ní ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn mo yàn án. Ní ọjọ́ ogbó ni mo ṣètò rẹ̀; nísinsin yìí mo ti mú wá sí ìkọjá pé ìwọ ti yí ìlú olódi padà dí òkìtì àlàpà òkúta.
Amo hou Na da hemonega ilegei, amo di da hame nabibala: ? Amola wali Na ilegei hou Na da hamoi dagoi. Di da gagili sali moilai bagohame gugunufinisiba: le, ilia da isu ligisisu agoai ba: sa. Be amo hamoma: ne, Nisu fawane da dima gasa defele i.
26 Àwọn ènìyàn wọn ń gbẹ nípa, wọ́n ti dà á láàmú wọ́n sì ti ṣọ́ di ìtìjú. Wọ́n dàbí koríko igbó lórí pápá, gẹ́gẹ́ bí ọkà tí ó rẹ̀ dànù kí ó tó dàgbàsókè, gẹ́gẹ́ bí fífún ọkà tí ó hù jáde.
Dunu amogawi esalu da gasa hamedafa ba: i. Ilia da bagadewane beda: i amola gasa hameba: le, sidi agoai dialebe ba: i. Ilia da gisi, logo bega: o diasu da: iya gadodili lelebe, amo da gia: i bagade fo, gusudili mabe amoga fabe, amo defele ba: i.
27 “‘Ṣùgbọ́n èmi mọ ibi tí ìwọ dúró àti ìgbà tí ìwọ bá dé tàbí lọ àti bí ìwọ ṣe ìkáàánú rẹ: sí mi.
Be dia hou huluanedafa Na dawa: ! Dia hamobe amola dia habidili ahoabe, amo huluane Na dawa: Na da dia Nama nimi bagade ougi hou Na dawa:
28 Ṣùgbọ́n ìkáàánú rẹ sí mi àti ìrora rẹ dé etí mi, Èmi yóò gbé ìwọ̀ mi sí imú rẹ àti ìjánu mi sí ẹnu rẹ, èmi yóò mú ọ padà nípa wíwá rẹ.’
Na da dia ougi bagade hou amola gasa fi bagade hou amo sia: ne iasu, Na da lai dagoi. Amaiba: le, Na da wali dia mi ma: goga mi gala: mu, amola dia lafi ganodini gula misimu. Amola amoga, Na da di logo di misi amoga di buhagima: ne sesemu.”
29 “Èyí yóò jẹ́ àmì fún ọ, ìwọ Hesekiah: “Ọdún yìí ìwọ yóò jẹ ohun tí ó bá hù fún rara rẹ̀, àti ní ọdún kejì ohun tí ó bá hù jáde láti inú ìyẹn. Ṣùgbọ́n ní ọdún kẹta, gbìn kí o sì kórè, gbin ọgbà àjàrà kí o sì jẹ èso rẹ̀.
Amalalu, Aisaia da hina bagade Hesegaiama amane sia: i, “Na da dima hobea misunu hou da dafawane doaga: mu, amo dawa: digima: ne olelesu dima imunu. Wali ode amola aya ode, dilia da udigili sogega heda: i gala: ine fawane manu. Be ode aduna baligili eno amoga, dilia da gala: ine bugili, gamimu amola waini efe sagai bugili, waini fage manu.
30 Lẹ́ẹ̀kan sí i ìyókù ti ilé Juda yóò sì tún hu gbòǹgbò lábẹ́, yóò sì so èso lókè.
Yuda soge ganodini, dunu amo da hame bogoi esalebe ba: sea, ilia da bugi amo da difi osobo gududafa sa: i, amola fage noga: le legei, amo defele ba: mu.
31 Láti inú Jerusalẹmu ní àwọn ìyókù yóò ti wá àti láti orí òkè Sioni ni ọ̀pọ̀ àwọn tí ó sá àsálà. Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò ṣe èyí.
Yelusaleme moilai bai bagadega amola Saione Goumia dunu hame bogoi, esalebe ba: mu. Bai Hina Gode da amo hou doaga: ma: ne, dafawane ilegei dagoi.
32 “Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa sọ nípa ti ọba Asiria: “Kò ní wọ ìlú yìí tàbí ta ọfà síbí. Kò ní wá níwájú rẹ pẹ̀lú àpáta tàbí kó ìdọ̀tí àgbò sí ọ̀kánkán rẹ.
Amola Hina Gode da Asilia hina bagade ema misunu hou olelema: ne, amane sia: sa, ‘E da Yelusaleme hamedafa golili sa: imu. E da amoga dadi afae hamedafa gala: mu. Dadi gagui dunu da da: igene gaga: su liligi gaguiwane da, Yelusaleme gadenena hame misunu. Ilia da amoma doagala: musa: , osobo gasa: le lelegela hame heda: mu.
33 Nípa ọ̀nà tí ó gbà wá ni yóò padà; kì yóò wọ ìlú ńlá yìí, ni Olúwa wí.
Asilia hina bagade da moilai ganodini mae golili sa: ili, hi misi logoga buhagimu. Bai Na, Hina Gode da amo sia: i dagoi.
34 Èmi yóò dá ààbò bo ìlú ńlá yìí, èmi yóò sì pa á mọ́ fún èmi tìkára mi àti fún Dafidi ìránṣẹ́ mi.”
Dunu da Nama nodoma: ne amola Na da Na hawa: hamosu dunu Da: ibidima dafawane ilegele sia: beba: le, Na da amo moilai gaga: mu.”
35 Ní alẹ́ ọjọ́ náà, angẹli Olúwa jáde lọ ó sì pa ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án lé ẹgbẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ènìyàn ní ibùdó àwọn ará Asiria. Nígbà tí wọ́n sì dìde dúró ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì níbẹ̀ ni gbogbo òkú wà!
Amo gasia, Hina Gode Ea a: igele dunu da Asilia ha wa: i fisisu amoga asili, Asilia dadi gagui dunu 185,000 agoane medole legei. Golale, hahabe, ilia huluane da osoboga bogogia: i dialebe ba: i.
36 Bẹ́ẹ̀ ni Sennakeribu ọba Asiria wọ àgọ́ ó sì padà, ó sì padà sí Ninefe ó sì dúró níbẹ̀.
Amalalu, Asili hina bagade Sena: galibi da Yuda soge fi doagala: lalu yolesili, Ninife moilai bagadega buhagi.
37 Ní ọjọ́ kan, nígbà tí ó sùn nínú ilé òrìṣà Nisroki, ọmọkùnrin rẹ̀ Adrameleki àti Ṣareseri gé e lulẹ̀ pẹ̀lú idà, wọ́n sì sálọ sí ilẹ̀ Ararati Esarhadoni ọmọkùnrin rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Eso afaega, e da ea ogogosu ‘gode’ Miseloge ea debolo diasua ema nodone sia: ne gadolaloba, egefe aduna amo A: dala: melege amola Sialisa da elea gegesu gobiheiga, Sena: galibi fane legele, Elala: de sogega hobea: i. Sena: galibi egefe eno, amo Isaha: done, da e bagia Asilia hina bagade hamoi.