< 2 Kings 18 >

1 Ní ọdún kẹta Hosea ọmọ Ela ọba Israẹli, Hesekiah ọmọ Ahasi ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba.
Na rĩrĩ, mwaka-inĩ wa ĩtatũ wa Hoshea mũrũ wa Ela mũthamaki wa Isiraeli, nĩguo Hezekia mũrũ wa Ahazu mũthamaki wa Juda aambĩrĩirie gũthamaka.
2 Ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó ti di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Abijah ọmọbìnrin Sekariah.
Aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtano rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na kenda. Nyina eetagwo Abija mwarĩ wa Zekaria.
3 Ó sì ṣe ohun tí ó dára níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí i baba rẹ̀ Dafidi ti ṣe.
Nake agĩĩka maũndũ marĩa magĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova, o ta ũrĩa ithe Daudi eekĩte.
4 Ó mú ibi gíga náà kúrò, ó sì fọ́ àwọn ère òkúta, ó sì gé àwọn ère Aṣerah lulẹ̀, ó sì fọ́ ejò idẹ tí Mose ti ṣe náà túútúú, títí di ọjọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli ń sun tùràrí sí. (Wọ́n sì pè é ní Nehuṣitani.)
Nĩeheririe kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru, akĩhehenja mahiga marĩa maamũrĩirwo ngai cia mĩhianano, na agĩtemenga itugĩ cia Ashera. Nayo nyoka ya gĩcango ĩrĩa yathondeketwo nĩ Musa akĩmiunanga tũcunjĩ, nĩgũkorwo nginyagia ihinda rĩu andũ a Isiraeli nĩmamĩcinagĩra ũbumba. Nayo yetagwo Nehushitani.
5 Hesekiah sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run Israẹli. Kò sì ṣí ẹnìkan tí ó dàbí tirẹ̀ lára gbogbo àwọn ọba Juda, bóyá kí ó tó jẹ tàbí lẹ́yìn rẹ̀.
Nake Hezekia agĩtũũra ehokete Jehova, Ngai wa Isiraeli. Gũtiarĩ mũndũ ũngĩ take harĩ athamaki othe a Juda, mbere yake kana arĩa mookire thuutha wake.
6 Ó súnmọ́ Olúwa, kò sì dẹ́kun láti tì í lẹ́yìn: ó sì pa òfin Olúwa mọ́ tí ó ti fi fún Mose.
Nĩatũũrire arũgamĩte wega harĩ Jehova na ndaigana gũtiga kũmũrũmĩrĩra; na nĩatũũire arũmĩtie maathani ma Jehova marĩa aaheire Musa.
7 Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀; ó sì ń ṣe rere nínú gbogbo ohun tí ó dáwọ́lé. Ó ṣe ọ̀tẹ̀ sí ọba Asiria kò sì sìn ín.
Nake Jehova aarĩ hamwe nake; nake Hezekia akĩgaacĩra maũndũ-inĩ mothe marĩa ekaga. Ningĩ nĩareganire na watho wa mũthamaki wa Ashuri, na akĩrega kũmũtungata.
8 Láti ilé ìṣọ́ títí dé ìlú olódi, ó sì pa àwọn ará Filistini run, àti títí dé Gasa àti agbègbè rẹ̀.
Nĩatooririe Afilisti kuuma mũthiringo-inĩ wa arangĩri nginya itũũra-inĩ rĩrĩa rĩairigĩtwo na rũthingo rwa hinya, o nginya Gaza na matũũra makuo.
9 Ní ọdún kẹrin ọba Hesekiah, nígbà tí ó jẹ́ ọdún keje Hosea ọmọ Ela ọba Israẹli. Ṣalamaneseri ọba Asiria yàn lára Samaria ó sì tẹ̀dó tì í.
Mwaka-inĩ wa ĩna wa ũthamaki wa Hezekia, na nĩguo warĩ mwaka wa mũgwanja wa Hoshea mũrũ wa Ela mũthamaki wa Isiraeli, Shalimaneseru mũthamaki wa Ashuri nĩathiire kũrũa na itũũra rĩa Samaria na akĩrĩrigiicĩria.
10 Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta Asiria gbé e. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kó Samaria ní ọdún kẹfà Hesekiah tí ó sì jẹ́ ọdún kẹsànán Hosea ọba Israẹli.
Na thuutha wa mĩaka ĩtatũ Ashuri magĩtunyana Samaria. Nĩ ũndũ ũcio itũũra rĩa Samaria rĩgĩtahwo mwaka-inĩ wa ĩtandatũ wa ũthamaki wa Hezekia, na warĩ mwaka wa kenda wa ũthamaki wa Hoshea mũthamaki wa Isiraeli.
11 Ọba Asiria lé Israẹli kúrò ní Asiria, wọ́n sì ṣe àtìpó wọn ní Hala, ní Gosani létí odò Habori àti ní ìlú àwọn ará Media.
Nake mũthamaki wa Ashuri agĩthaamĩria andũ a Isiraeli kũu Ashuri, akĩmahe ũtũũro Hala, kũu Gozani ndwere-inĩ cia Rũũĩ rwa Haboru na matũũra-inĩ ma Amedi.
12 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí wọn kò pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wọn mọ́. Ṣùgbọ́n wọ́n ti dà májẹ̀mú rẹ̀ gbogbo èyí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ. Wọn kò fi etí wọn sílẹ̀ sí òfin wọn kò sì gbé wọn jáde.
Ũndũ ũcio wekĩkire nĩ ũndũ nĩmagĩte gwathĩkĩra Jehova Ngai wao, no magĩthũkia kĩrĩkanĩro gĩake, na ũrĩa wothe Musa ndungata ya Jehova aamaathĩte. Matiathikĩrĩirie maathani macio kana makĩmahingia.
13 Ní ọdún kẹrìnlá tí Hesekiah jẹ ọba, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo ìlú olódi ti Juda ó sì pa wọ́n run.
Mwaka-inĩ wa ikũmi na ĩna wa ũthamaki wa Hezekia, Senakeribu mũthamaki wa Ashuri agĩtharĩkĩra matũũra mothe manene ma Juda marĩa mairigĩirwo na thingo cia hinya, na akĩmatunyana.
14 Bẹ́ẹ̀ ni Hesekiah ọba Juda sì ránṣẹ́ yìí sí ọba Asiria ní Lakiṣi, wí pé, “Mo ti ṣẹ̀, padà lẹ́yìn mi: èmi yóò sì san ohunkóhun tí ìwọ bá béèrè lọ́wọ́ mi.” Ọba Asiria sì bu fún Hesekiah ọba Juda ọ̀ọ́dúnrún tálẹ́ǹtì fàdákà àti ọgbọ̀n tálẹ́ǹtì wúrà.
Nĩ ũndũ ũcio Hezekia mũthamaki wa Juda agĩtũmĩra mũthamaki wa Ashuri ũrĩa warĩ kũu Lakishi ndũmĩrĩri ĩno: “Nĩhĩtĩtie. Njeherera na nĩngũkũrĩha kĩrĩa gĩothe ũngĩnjĩtia.” Nake mũthamaki wa Ashuri agĩĩtia Hezekia mũthamaki wa Juda taranda magana matatũ cia betha, na taranda mĩrongo ĩtatũ cia thahabu kĩa hinya.
15 Hesekiah fún un ní gbogbo fàdákà tí a rí nínú ilé Olúwa àti nínú ìṣúra ilé ọba.
Nĩ ũndũ ũcio Hezekia akĩmũhe betha iria ciothe cionekire hekarũ-inĩ ya Jehova na igĩĩna-inĩ ciothe cia nyũmba ya ũthamaki.
16 Ní àkókò yìí Hesekiah ọba Juda ké wúrà tí ó wà ní ẹnu ìlẹ̀kùn ilé Olúwa, kúrò àti ti òpó tí Hesekiah ọba Juda ti gbéró ó sì fi fún ọba Asiria.
Ihinda-inĩ rĩu, Hezekia mũthamaki wa Juda akĩruta thahabu ĩrĩa yagemetie mĩrango na itugĩ cia mĩrango ya hekarũ ya Jehova na akĩmĩhe mũthamaki wa Ashuri.
17 Ọba Asiria rán alákòóso gíga jùlọ, ìjòyè pàtàkì àti àwọn adarí pápá pẹ̀lú àwọn ọmọ-ogun tí ó pọ̀, láti Lakiṣi sí ọba Hesekiah ní Jerusalẹmu. Wọ́n wá sí òkè Jerusalẹmu wọ́n sì dúró ní etí ìdarí omi àbàtà òkè, ní ojú ọ̀nà tó lọ sí òpópó pápá alágbàfọ̀.
Mũthamaki wa Ashuri agĩtũma mwathi ũrĩa mũnene wa mbũtũ ciothe cia ita, na mũrũgamĩrĩri wa anene arĩa angĩ, na mwathi wa mbũtũ cia mbaara, marĩ na mbũtũ nene ya ita kuuma Lakishi mathiĩ kũrĩ Mũthamaki Hezekia kũu Jerusalemu. Magĩkinya Jerusalemu na makĩrũgama mũtaro-inĩ wa Karia ka Rũgongo, njĩra-inĩ ya gũthiĩ Mũgũnda-inĩ wa Mũthambia Nguo.
18 Wọ́n sì pe ọba; àti Eliakimu ọmọ Hilkiah ẹni tí í ṣe ilé olùtọ́jú, Ṣebna akọ̀wé, àti Joah ọmọkùnrin Asafu tí ó jẹ́ akọ̀wé ìrántí jáde pẹ̀lú wọn.
Magĩtũmanĩra mũthamaki; nake Eliakimu mũrũ wa Hilikia mũrũgamĩrĩri wa nyũmba ya ũthamaki, na Shebina ũrĩa mwandĩki-marũa, na Joa mũrũ wa Asafu ũrĩa warĩ mwandĩki wa maũndũ ma ihinda rĩu, makiumagara mathiĩ kũrĩ o.
19 Olùdarí pápá wí fún wọn pé, “Sọ fún Hesekiah pé, “‘Èyí ni ohun tí ọba ńlá, ọba Asiria sọ: Kí ni ìgbẹ́kẹ̀lé yìí tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé?
Nake mũnene wa mbũtũ cia ita akĩmeera atĩrĩ, “Ĩrai Hezekia atĩrĩ: “‘Mũthamaki ũrĩa mũnene, o we mũthamaki wa Ashuri, ekuuga atĩrĩ: Ũrutĩte ũmĩrĩru ũcio ũrĩ naguo kũ?
20 Ìwọ wí pé ìwọ ni ìmọ̀ àti agbára láti jagun, ṣùgbọ́n ìwọ sọ̀rọ̀ òfìfo lásán. Ǹjẹ́ ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀ rẹ lé, tí ìwọ fi ń ṣe ọ̀tẹ̀ sí mi?
Wee uugaga ũrĩ na hinya wa mbũtũ cia ita, na nĩũũĩ kũrũa, no waragia o ciugo cia tũhũ. Nũũ ũcio wĩhokete atĩ nĩguo ũnemere?
21 Wò ó, nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀ rẹ lé Ejibiti, ẹ̀rún ọ̀pá pẹlẹbẹ ìyè fífọ́ yìí, èyí tí yóò wọ inú ọwọ́ ẹni tí ó sì bá fi ara tì í. Bẹ́ẹ̀ ni Farao ọba Ejibiti ṣe rí fún gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀ wọn lé e.
Atĩrĩrĩ, wee wĩhokete andũ a Misiri acio mahaana ta kamũrangi koinĩkangu, karĩa gatheecaga mũndũ guoko, gakamũguraria etiirania nako! Ũguo nĩguo Firaũni mũthamaki wa Misiri ahaana kũrĩ arĩa othe mamwĩhokaga.
22 Tí ìwọ bá sì sọ fún mi pé, “Àwa gbẹ́kẹ̀ wa lé Olúwa Ọlọ́run.” Òun ha kọ́ ní ẹnìkan náà tí ibi gíga àti àwọn pẹpẹ tí Hesekiah mú kúrò, tí ó wí fún Juda àti Jerusalẹmu pé, “O gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí ní Jerusalẹmu”?
O na ũngĩnjĩĩra atĩrĩ, “Ithuĩ twĩhokete Jehova Ngai witũ”, githĩ tiwe wehereirio kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru, na igongona iria ciarĩ kuo nĩ Hezekia, akĩĩra andũ a Juda na Jerusalemu atĩrĩ, “No nginya mũhooyagĩre mbere ya kĩgongona gĩkĩ kĩrĩ Jerusalemu?”
23 “‘Wá nísinsin yìí, ṣe àdéhùn pẹ̀lú ọ̀gá mi, ọba Asiria èmi yóò sì fún ọ ní ẹgbẹ̀rún méjì ẹṣin tí ìwọ bá lè kó àwọn tí yóò gùn ún sí orí rẹ!
“‘Rĩu-rĩ, ũka ũkeiguithanie na mwathi wakwa, mũthamaki wa Ashuri: Nĩngũkũhe mbarathi ngiri igĩrĩ angĩkorwo ũrĩ na andũ mangĩcitwarithia!
24 Báwo ni ìwọ yóò ha ti ṣe le yí ojú balógun kan tí ó kéré jùlọ padà nínú àwọn ìránṣẹ́ olúwa mi, tí ìwọ sì gbẹ́kẹ̀ rẹ lé Ejibiti fún àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin?
Wakĩhota gũtooria o na mũnene ũrĩa mũnini mũno thĩinĩ wa anene a mwathi wakwa, o na gũtuĩka wĩhokete ngaari cia ita na andũ arĩa mathiiaga mahaicĩte mbarathi a Misiri?
25 Síwájú sí i, èmi ti wá láti mú àti láti parun ibí yìí láìsí ọ̀rọ̀ láti ọ̀dọ̀ Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ sọ fún mi pé kí n yára láti yan lórí ìlú yìí, kí n sì pa á run.’”
Na ningĩ-rĩ, njũkĩte gũtharĩkĩra na kwananga kũndũ gũkũ iterĩĩtwo nĩ Jehova? Jehova we mwene nĩwe wanjĩĩrire njũke hũũre bũrũri ũyũ, na ndĩwanange.’”
26 Nígbà náà Eliakimu ọmọ Hilkiah, àti Ṣebna àti Joah sọ fún olùdarí pápá pé, “Jọ̀wọ́ sọ̀rọ̀ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ ní èdè Aramaiki, nítorí ti ó tí yé wa, má ṣe sọ̀rọ̀ fún wa pẹ̀lú èdè Heberu ní etí ìgbọ́ àwọn ènìyàn tí ń bẹ lórí odi.”
Nake Eliakimu mũrũ wa Hilikia, na Shebina, na Joa makĩĩra mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita atĩrĩ, “Twagũthaitha arĩria ndungata ciaku na rũthiomi rwa Asuriata, tondũ nĩtũrũũĩ. Tiga gũtwarĩria na rũthiomi rwa Kĩhibirania, andũ aya marĩ rũthingo-inĩ makĩiguaga.”
27 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn pé, “Ṣé fún ọ̀gá rẹ àti ìwọ nìkan ní ọ̀gá mi rán mi sí láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí kì í sì í ṣe fún àwọn ọkùnrin tí ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ bí ìwọ, ni yóò ní láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn kí wọ́n sì mu ìtọ̀ ará wọn?”
No mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita agĩcookia atĩrĩ, “Kaĩ ndatũmirwo nĩ mwathi wakwa kũrĩ mwathi wanyu na kũrĩ inyuĩ ndĩmwĩre maũndũ maya, na ti kũrĩ andũ aya maikarĩte rũthingo igũrũ, o aya makaarĩa kĩoro kĩao na manyue mathugumo mao o ene o ta ũrĩa inyuĩ mũgeeka?”
28 Nígbà náà, aláṣẹ dìde, ó sì pè jáde ní èdè Heberu pé, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria!
Ningĩ mũnene wa mbũtũ cia ita akĩrũgama, akĩanĩrĩra na rũthiomi rwa Kĩhibirania, akiuga atĩrĩ: “Thikĩrĩriai ndũmĩrĩri ya mũthamaki ũrĩa mũnene, mũthamaki wa Ashuri!
29 Èyí ni ohun tí ọba sọ, má ṣe jẹ́ kí Hesekiah tàn ọ́ jẹ kò le gbà ọ́ kúrò ní ọwọ́ mi.
Mũthamaki ekuuga ũũ: Mũtigetĩkĩrie Hezekia amũheenie. Ndangĩhota kũmũhonokia kuuma guoko-inĩ gwakwa.
30 Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah mú yín gbẹ́kẹ̀lé Olúwa nípa sísọ pé, ‘Olúwa yóò gbà wá nítòótọ́; ìlú yìí ni wọn kò ní fi lé ọba ìlú Asiria lọ́wọ́.’
Mũtigetĩkĩre Hezekia amũringĩrĩrie kwĩhoka Jehova hĩndĩ ĩrĩa ekuuga atĩrĩ, ‘Ti-itherũ Jehova nĩegũtũhonokia; itũũra rĩĩrĩ rĩtikaneanwo guoko-inĩ kwa mũthamaki wa Ashuri.’
31 “Má ṣe tẹ́tí sí Hesekiah. Èyí ni ohun tí ọba Asiria wí pé, ‘Fi ẹ̀bùn wá ojúrere mi, kí o sì jáde tọ̀ mí wá.’ Nígbà náà olúkúlùkù yín yóò jẹun láti inú àjàrà rẹ̀ àti igi ọ̀pọ̀tọ́, yóò sì mu omi láti inú àmù rẹ̀,
“Mũtigathikĩrĩrie Hezekia. Mũthamaki wa Ashuri ekuuga ũũ: Rekei tũiguane, na mũũke kũrĩ niĩ. Mweka ũguo o ũmwe wanyu nĩakarĩĩaga kuuma kũrĩ mũtĩ wake wa mũthabibũ na mũkũyũ, na anyuuage maaĩ ma gĩthima gĩake,
32 títí tí èmi yóò fi wá mú ọ lọ sí ilé gẹ́gẹ́ bí i tìrẹ, ilẹ̀ ọkà àti ọtí wáìnì, ilẹ̀ oúnjẹ àti ọgbà àjàrà, ilẹ̀ òróró olifi àti ti ilẹ̀ oyin; yàn ìyè má sì ṣe yàn ikú! “Kí ẹ má ṣe gbọ́ tí Hesekiah, nítorí ó ń tàn yín tí ó ba tí wí pé, ‘Olúwa yóò gbà wá?’
nginya rĩrĩa ngooka ndĩmũtware bũrũri ũrĩa ũhaana ta wanyu, bũrũri ũrĩ ngano na ndibei ya mũhihano, bũrũri ũrĩ irio na mĩgũnda ya mĩthabibũ, bũrũri ũrĩ mĩtĩ ya mĩtamaiyũ na ũũkĩ. Thuurai muoyo no ti gĩkuũ! “Mũtigathikĩrĩrie Hezekia, nĩgũkorwo nĩaramũhĩtithia rĩrĩa ekuuga atĩrĩ, ‘Jehova nĩegũtũhonokia.’
33 Ṣé òrìṣà àwọn orílẹ̀-èdè kankan ti gba ilé rẹ lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria?
Nĩ kũrĩ ngai ya bũrũri o na ũrĩkũ ĩrĩ yahonokia bũrũri wayo kuuma guoko-inĩ kwa mũthamaki wa Ashuri?
34 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi gbé wà? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi, Hena àti Iffa gbé wà? Wọ́n ha gba Samaria kúrò lọ́wọ́ mi bí?
Ngai cia Hamathu na Aripadi irĩ kũ? Ngai cia Sefarivaimu, na Hena na Iva irĩ kũ? Nĩihonoketie Samaria kuuma guoko-inĩ gwakwa?
35 Ta ni nínú gbogbo àwọn òrìṣà ilẹ̀ yìí tí ó ti gbìyànjú láti gba ilẹ̀ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa yóò ṣe gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?”
Nĩ ngai ĩrĩkũ harĩ ngai ciothe cia mabũrũri macio yanahonokia bũrũri wayo kuuma kũrĩ niĩ? Gwakĩhoteka atĩa Jehova ahonokie Jerusalemu kuuma guoko-inĩ gwakwa?”
36 Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ènìyàn náà dákẹ́ síbẹ̀ wọn kò sì sọ ohunkóhun, láti fi fèsì, nítorí ọba ti paláṣẹ, “Ẹ má ṣe dá a lóhùn.”
No andũ acio magĩkira ki, na matirĩ ũndũ maamũcookeirie, tondũ mũthamaki nĩamathĩte, akameera atĩrĩ, “Mũtikamũcookerie ũndũ.”
37 Nígbà náà Eliakimu ọmọ Hilkiah olùtọ́jú ààfin, Ṣebna akọ̀wé àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé ránṣẹ́ lọ sí ọ̀dọ̀ Hesekiah, pẹ̀lú aṣọ wọn yíya, ó sì wí fún un ohun tí olùdarí pápá ti sọ.
Hĩndĩ ĩyo Eliakimu mũrũ wa Hilikia ũrĩa mũrori wa maũndũ ma nyũmba ya ũthamaki, na Shebina ũrĩa mwandĩki-marũa, na Joa mũrũ wa Asafu ũrĩa mwandĩki wa maũndũ ma ihinda rĩu, magĩthiĩ kũrĩ Hezekia, matembũrangĩte nguo ciao, na makĩmwĩra ũrĩa mũnene ũcio wa mbũtũ cia ita oigĩte.

< 2 Kings 18 >