< 2 Kings 16 >

1 Ní ọdún kẹtàdínlógún Peka ọmọ Remaliah, Ahasi ọmọ Jotamu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ sí i jẹ ọba.
Isala: ili hina bagade Biga (Lemalaia egefe) amo ea ouligibi ode 17 amoga, A:iha: se (Youda: me egefe) da Yuda hina bagade hamoi.
2 Ẹni ogún ọdún ni Ahasi nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí jẹ ọba, ó sì jẹ ọba ọdún mẹ́rìndínlógún ní Jerusalẹmu, kò sì ṣe èyí tí ó tọ́ lójú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Dafidi baba rẹ̀.
A: iha: se da lalelegele, ode 20 agoane esalu, e da muni Yuda hina bagade hamoi, amola e da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode 16 agoanega Yuda fi ouligilalu. E da ea aowa hina bagade Da: ibidi ea molole hamosu hou defele hame hamoi. Be e da wadela: i hou hamobeba: le, Hina Gode da ema hahawane hame galu.
3 Ṣùgbọ́n ó rìn ní ọ̀nà àwọn ọba Israẹli, nítòótọ́, ó sì sun ọmọ rẹ̀ nínú iná, gẹ́gẹ́ bí ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè, tí Olúwa lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
E da Isala: ili hina bagade ilia wadela: i hou defele hamoi. E da wadela: idafa hou amo Ga: ina: ne dunu ilia hamoi (Isala: ili dunu da Ga: ina: ne soge fedele lamusa: gusuba: i mogodigisia, Hina Gode da Ga: ina: ne dunu gadili sefasi) amo ilia hou defele hamoi. Bai e da hina: egefe amo ogogosu loboga hamoi ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadomusa: , gobele sali.
4 Ó sì rú ẹbọ, ó sì sun tùràrí ní àwọn ibi gíga, àti lórí àwọn òkè kéékèèké àti lábẹ́ gbogbo igi tútù.
E da ogogosu ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu sogebi agolo da: iya galu, amola ifa huluane ilia ougiha galu amogai, A:iha: se da ohe amola gabusiga: manoma gobele salalusu.
5 Nígbà náà ni Resini ọba Siria àti Peka ọmọ Remaliah ọba Israẹli gòkè wá sí Jerusalẹmu láti jagun: wọ́n dó ti Ahasi, ṣùgbọ́n wọn kò lè borí rẹ̀.
Silia hina bagade, Lisini amola Isala: ili hina bagade Biga da Yelusaleme doagala: le, eale disi, be ilia da A: iha: se hasalimu hamedei ba: i.
6 Ní àkókò náà, Resini ọba Siria gba Elati padà fún Siria, ó sì lé àwọn ènìyàn Juda kúrò ní Elati: àwọn ará Siria sì wá sí Elati, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀ títí di òní yìí.
(Amogalu, Idome hina bagade da Ila: de moilai bu fedelai. E da Yuda fi dunu Ila: de moilai amo ganodini esalebe, amo gadili sefasi. Idome dunu da Ila: de ganodini fimusa: heda: i. Amola amoganini ilia da wali amoga esala)
7 Ahasi sì rán oníṣẹ́ sọ́dọ̀ Tiglat-Pileseri ọba Asiria wí pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ni èmi, àti ọmọ rẹ; gòkè wá, kí o sì gbà mi lọ́wọ́ ọba Siria, àti lọ́wọ́ ọba Israẹli tí ó dìde sí mi.”
A: iha: se da sia: adola ahoasu dunu ili amo Asilia hina bagade Digala: de Bilisa ema asunasi. Ilia da ema A: iha: se ea sia: da amane adosi, “Na da dia dogolegei hawa: hamosu dunu! Silia hina bagade amola Isala: ili hina bagade da nama doagala: lala! Di misini, na gaga: ma!”
8 Ahasi sì mú fàdákà àti wúrà tí a rí ní ilé Olúwa, àti nínú ìṣúra ilé ọba, ó sì rán an sí ọba Asiria ní ọrẹ.
A: iha: se da silifa amola gouli, amo da Debolo Diasua dialu, amola hina bagade diasua dialu, amo lale, Asilia hina bagadema iasi.
9 Ọba Asiria sì gbọ́ tirẹ̀: nítorí ọba Asiria gòkè wá sí Damasku, ó sì kó o, ó sì mú un ní ìgbèkùn lọ sí Kiri, ó sì pa Resini.
Digila: de Bilisa da A: iha: se ea adole ba: su nababeba: le, ea dadi gagui dunu wa: i huluane gadili mogodigili asili, Dama: saga: se moilai bai bagade doagala: i. E da moilai fedelale, hina bagade Lisini medole legele, amola dunu fi huluane Ge sogega udigili hawa: hamomusa: mugululi asi.
10 Ọba sì lọ sí Damasku láti pàdé Tiglat-Pileseri, ọba Asiria, ó sì rí pẹpẹ kan tí ó wà ní Damasku: Ahasi ọba sì rán àwòrán pẹpẹ náà, àti àpẹẹrẹ rẹ̀ sí Uriah àlùfáà, gẹ́gẹ́ bí gbogbo iṣẹ́ ọ̀nà rẹ̀.
Yuda hina bagade A: iha: se da Dama: saga: se moilai bai bagadega, Digala: de Bilisa gousa: musa: asili, e da oloda amogawi dialu amo ba: i dagoi. E da amo oloda agoaila defele, liligi huluanedafa hahamonanu, amo hamone, gobele salasu dunu Iulaiama iasi.
11 Uriah àlùfáà sì kọ́ pẹpẹ náà gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí tí Ahasi ọba fi ránṣẹ́ sí i láti Damasku; bẹ́ẹ̀ ni Uriah àlùfáà ṣe é dé ìpadàbọ̀ Ahasi ọba láti Damasku.
Amaiba: le, gobele salasu dunu Iulaia da amo Dama: saga: se oloda A: iha: se da Yelusalemema bu mae doaga: le, amo defele, eno hamoi.
12 Nígbà tí ọba sì ti Damasku dé, ọba sì rí pẹpẹ náà: ọba sì súnmọ́ pẹpẹ náà, ó sì rú ẹbọ lórí rẹ̀.
A: iha: se da Yelusaleme moilai bai bagadega buhagili, oloda hamoi dagoi ba: i.
13 Ó sì sun ẹbọ sísun rẹ̀ àti ọrẹ-jíjẹ rẹ̀, o si ta ohun mímu rẹ̀ sílẹ̀, ó sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ ọrẹ àlàáfíà rẹ̀ sí ara pẹpẹ náà.
Amaiba: le, e da amo da: iya ohe amola gala: ine iasu gobele salasu. Amola amo da: iya waini hano iasu amola olofosu gilisisu iasu maga: me soga: digi.
14 Ṣùgbọ́n ó mú pẹpẹ idẹ tí ó wà níwájú Olúwa kúrò láti iwájú ilé náà, láti àárín méjì pẹpẹ náà, àti ilé Olúwa, ó sì fi í sí apá àríwá pẹpẹ náà.
Balasega hamoi oloda amo da Hina Godema nodoma: ne ilegei da Debolo Diasu amola gaheabolo oloda amo dogoa dibiga dialebe ba: i. Amaiba: le, A:iha: se da Hina Gode Ea oloda fadegale, ea oloda ea ga (north) bega: amoga gaguli asi.
15 Ahasi ọba sì pàṣẹ fún Uriah àlùfáà, wí pé, “Lórí pẹpẹ ńlá náà ni kó o máa sun ẹbọ sísun òròwúrọ̀ àti ọrẹ-jíjẹ alaalẹ́, àti ẹbọ sísun ti ọba, àti ọrẹ-jíjẹ rẹ̀, pẹ̀lú ẹbọ sísun tí gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti ọrẹ-jíjẹ wọn, àti ọrẹ ohun mímu wọn; kí o sì wọ́n gbogbo ẹ̀jẹ̀ ẹbọ sísun náà lórí rẹ̀, àti gbogbo ẹ̀jẹ̀ ẹbọ mìíràn, ṣùgbọ́n ní ti pẹpẹ idẹ náà èmi ó máa gbèrò ohun tí èmi ó fi ṣe.”
Amalalu, e da Iulaiama amane hamoma: ne sia: i, “Na oloda bagade amo da: iya hahabe wadela: i hou dabe iasu amola daeya gala: ine iasu amola hina bagade amola dunu fi ilia wadela: i hou dabe iasu amola gala: ine iasu amola dunu fi ilia waini iasu huluane, na oloda da: iya gobele salima. Amola amogawi, gobele salasu ohe huluane ilia maga: me soga: digima. Be Hina Gode Ea oloda balasega hamoi amoga na ba: la: lusu hou hamoma: ne yolesima.”
16 Báyìí ni Uriah àlùfáà ṣe, gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí Ahasi ọba pàṣẹ.
Iulaia da hina bagade ea hamoma: ne sia: i defele hamoi.
17 Ahasi ọba sì gé igi-ìpílẹ̀ àwọn àgbédúró náà, ó ṣí agbada náà kúrò lára wọn; ó sì gbé agbada ńlá náà kalẹ̀ kúrò lára àwọn màlúù idẹ tí ń bẹ lábẹ́ rẹ̀, ó sì gbé e ka ilẹ̀ tí a fi òkúta tẹ́.
Hina bagade A: iha: se da balasega hamoi gaguli fula ahoasu gagili liligi (amoga ilia da Debolo ganodini hawa: hamosu) amo mugului amola ofodo amo da: iya dialu, amo fadegale fasi. Amola e da balasega hamoi ofodo sugi bagade amo balasega hamoi bulamagau ilia baligi da: iya dialu, amo fadegale, bu gele baiga ligisi.
18 Ibi ààbò fún ọjọ́ ìsinmi tí a kọ́ nínú ilé náà, àti ọ̀nà ìjáde sí òde ọba, ni ó yípadà kúrò ní ilé Olúwa nítorí ọba Asiria.
Amola e da Asilia hina bagade ema nodoma: ne, e da Debolo Diasuga fafai amo da: iya ilia da hina bagade fisu bugisi, amo fadegai amola hina bagade hina: Debolo Diasuga golili dasu logo holei, amo ga: si dagoi.
19 Àti ìyókù ìṣe Ahasi tí ó ṣe, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
Hina bagade A: iha: se ea hawa: hamonanu eno huluane da “Yuda hina bagade Ilia Hamonanu Meloa,” amo ganodini dedene legei.
20 Ahasi sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi: Hesekiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A: iha: se bogole, hina bagade bogoi uli dogosu sogebi Da: ibidi Moilai Bai Bagadega uli dogone sali. Egefe Hesegaia da, e bagia, Yuda fi ilia hina bagade hamoi.

< 2 Kings 16 >