< 2 Kings 14 >

1 Ní ọdún kejì tí Jehoaṣi ọmọ Joahasi ọba Israẹli, Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba.
Na rĩrĩ, mwaka-inĩ wa keerĩ wa ũthamaki wa Jehoashu mũrũ wa Jehoahazu mũthamaki wa Isiraeli, Amazia mũrũ wa Joashu mũthamaki wa Juda akĩambĩrĩria gũthamaka.
2 Ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani; ó wá láti Jerusalẹmu.
Aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtano rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ kũu Jerusalemu mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na kenda. Nake nyina eetagwo Jehoadini, na oimĩte Jerusalemu.
3 Ó ṣe ohun tí ó tọ́ ní ojú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí i Dafidi baba a rẹ̀ tí ṣe. Nínú ohun gbogbo, ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ baba a rẹ̀ Joaṣi.
Nĩekire maũndũ marĩa moonagwo magĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova, no ti ta ũrĩa ithe Daudi eekĩte. Maũndũ-inĩ mothe eekire o ta ũrĩa ithe Joashu ekaga.
4 Àwọn ibi gíga bí ó ti wù kí ó rí, a kò sí i kúrò, àwọn ènìyàn sì tẹ̀síwájú láti rú ẹbọ àti sun tùràrí níbẹ̀.
No rĩrĩ, kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru gũtieheririo; andũ maathiire o na mbere kũrutĩra magongona na gũcinĩra ũbumba kuo.
5 Lẹ́yìn tí ó ti fi ọwọ́ gbá ìjọba rẹ̀ mú gbọingbọin, ó pa àwọn oníṣẹ́ tí wọ́n ti pa baba a rẹ̀ ọba.
Thuutha wa ũthamaki gũkorwo ũrũmĩte moko-inĩ make, akĩũraga anene arĩa moragĩte ithe Joashu ũrĩa warĩ mũthamaki.
6 Síbẹ̀ kò pa ọmọ àwọn apànìyàn náà. Ní ìbámu pẹ̀lú ohun tí a kọ sínú ìwé òfin Mose níbi tí Olúwa ti paláṣẹ pé, “A kì yóò pa baba nítorí àwọn ọmọ, tàbí àwọn ọmọ nítorí àwọn baba; olúkúlùkù ni kí ó kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.”
No rĩrĩ, ndaigana kũũraga ariũ a oragani acio, kũringana na ũrĩa kwandĩkĩtwo Ibuku-inĩ rĩa Watho wa Musa harĩa Jehova aathanĩte atĩrĩ: “Maithe ma ciana matikooragwo nĩ ũndũ wa ciana, o na kana ciana ciũragwo nĩ ũndũ wa maithe mao; o mũndũ arĩkuaga nĩ ũndũ wa mehia make mwene.”
7 Òun ni ẹni tí ó ṣẹ́gun ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ará Edomu ní àfonífojì iyọ̀, ó sì fi agbára mú Sela nínú ogun, tí ó ń pè é ní Jokteeli, orúkọ tí ó ní títí di òní.
Ningĩ nĩwe wahootire 10,000 cia andũ a Edomu kũu Gĩtuamba-inĩ gĩa Cumbĩ, na agĩtunyana itũũra rĩa Sela mbaara-inĩ, akĩrĩtua Jokitheeli, rĩĩtwa rĩrĩa rĩĩtagwo nginya ũmũthĩ.
8 Nígbà náà, Amasiah rán àwọn ìránṣẹ́ sí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu ọba Israẹli pẹ̀lú ìpèníjà: “Wá, jẹ́ kí á wo ara wa ní ojú.”
Hĩndĩ ĩyo Amazia agĩtũma andũ kũrĩ Jehoashu mũrũ wa Jehoahazu mũrũ wa Jehu, mũthamaki wa Isiraeli, akĩmwĩra atĩrĩ “Ũka tũngʼethanĩre ũthiũ kwa ũthiũ.”
9 Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì sí Amasiah ọba Juda: “Òṣùṣú kan ní Lebanoni rán iṣẹ́ sí kedari ní Lebanoni, ‘Fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ní ìgbéyàwó.’ Nígbà náà ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin tinú igbó ní Lebanoni wá pẹ̀lú ó sì fi ẹsẹ̀ tẹ òṣùṣú náà mọ́lẹ̀.
No rĩrĩ, Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli agĩcookeria Amazia mũthamaki wa Juda atĩrĩ: “Mahiũ ma nyeki-inĩ ma kũu Lebanoni nĩmatũmĩire mũtarakwa ndũmĩrĩri o kũu Lebanoni makĩwĩra atĩrĩ, ‘Heana mwarĩguo ahikio nĩ mũrũ wakwa.’ Hĩndĩ ĩyo nyamũ ya gĩthaka kũu Lebanoni ĩgĩũka ĩkĩrangĩrĩria mahiũ macio ma nyeki-inĩ na makinya mayo.
10 Ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu pẹ̀lú, ṣùgbọ́n, nísinsin yìí ìwọ ṣe ìgbéraga. Ògo nínú ìṣẹ́gun rẹ, ṣùgbọ́n dúró nílé! Kí ni ó dé tí o fi ń wá wàhálà tí o sì fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀lú?”
Ti-itherũ nĩũtooretie Edomu, na rĩu nĩũtuĩkĩte mwĩtĩĩi. Wĩgaathe nĩ ũndũ wa ũhootani waku, no ikara mũciĩ! Nĩ kĩĩ gĩgũtũma wĩrehere thĩĩna, wĩniinithie we mwene, o hamwe na andũ a Juda?”
11 Bí ó ti wù kí ó rí Amasiah kò ní tẹ́tí, bẹ́ẹ̀ ni Jehoaṣi ọba Israẹli sì dojúkọ ọ́. Òun àti Amasiah ọba Juda kọjú sí ara wọn ní Beti-Ṣemeṣi ní Juda.
O na kũrĩ ũguo, Amazia ndaigana gũthikĩrĩria; nĩ ũndũ ũcio Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli akĩmũtharĩkĩra. We na Amazia mũthamaki wa Juda makĩngʼethanĩra kũu Bethi-Shemeshu thĩinĩ wa Juda.
12 A kó ipa ọ̀nà Juda nípasẹ̀ Israẹli, gbogbo àwọn ọkùnrin sì sálọ sí ilé e rẹ̀.
Andũ a Juda makĩhũũrwo nĩ andũ a Isiraeli, na o mũndũ akĩũrĩra gwake mũciĩ.
13 Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára mú Amasiah ọba Juda, ọmọ Jehoaṣi, ọmọ Ahasiah ní Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà, Jehoaṣi lọ sí Jerusalẹmu, ó sì lọ wó odi Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ìlẹ̀kùn Efraimu sí ibi igun ìlẹ̀kùn. Ìpín kan tí ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ irinwó ìgbọ̀nwọ́.
Nake Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli akĩnyiita Amazia mũthamaki wa Juda mũrũ wa Joashu mũrũ wa Ahazia, o kũu Bethi-Shemeshu. Ningĩ Jehoashu agĩthiĩ Jerusalemu na akĩmomora rũthingo rwa Jerusalemu, kuuma Kĩhingo-inĩ kĩa Efiraimu nginya Kĩhingo gĩa Koine, handũ ha buti ta magana matandatũ kũraiha.
14 Ó mú gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun tí ó rí nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa àti níbi ìfowópamọ́ sí nínú ààfin ọba. Ó mú àwọn ògo, ó sì dá wọn padà sí Samaria.
Nake akĩoya thahabu yothe na betha na indo ciothe iria ciarĩ thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova na iria ciarĩ igĩĩna-inĩ cia nyũmba ya ũthamaki. Ningĩ agĩtaha andũ na agĩcooka Samaria.
15 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Jehoaṣi, gbogbo ohun tí ó ṣe pẹ̀lú àṣeyọrí rẹ̀, pẹ̀lú ogun rẹ̀ sí Amasiah ọba Juda, ṣé a kò kọ wọ́n sí inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
Ha ũhoro wa maũndũ marĩa mangĩ makoniĩ wathani wa Jehoashu, na marĩa eekire, na marĩa aahingirie, o hamwe na mbaara yake ĩrĩa maarũire na Amazia mũthamaki wa Juda-rĩ, githĩ matiandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩa mahinda ma athamaki a Isiraeli?
16 Jehoaṣi sì sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín sí Samaria pẹ̀lú àwọn ọba Israẹli. Jeroboamu ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Jehoashu akĩhurũka hamwe na maithe make, agĩthikwo Samaria hamwe na athamaki a Isiraeli. Nake mũriũ Jeroboamu agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.
17 Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli.
Amazia mũrũ wa Joashu mũthamaki wa Juda aatũũrire muoyo mĩaka ikũmi na ĩtano thuutha wa gĩkuũ kĩa Jehoashu mũrũ wa Jehoahazu mũthamaki wa Isiraeli.
18 Fún ti ìyókù iṣẹ́ rẹ̀ nígbà ìjọba Amasiah, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda?
Ha ũhoro wa maũndũ marĩa mangĩ ma wathani wa Amazia, githĩ matiandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩa mahinda ma athamaki a Juda?
19 Wọ́n dìtẹ̀ sí i ní Jerusalẹmu, ó sì sálọ sí Lakiṣi, ṣùgbọ́n wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀lé e sí Lakiṣi, wọ́n sì pa á síbẹ̀.
Nao andũ makĩgĩa ndundu ya kũmũũkĩrĩra kũu Jerusalemu, nake Amazia akĩũrĩra Lakishi, no magĩtũma andũ mamũrũmĩrĩre kũu Lakishi, na makĩmũũragĩra kuo.
20 Wọ́n gbé e padà pẹ̀lú ẹṣin, a sì sin ín sí Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, ní ìlú ńlá ti Dafidi.
Nĩacookirio akuuĩtwo na mbarathi, agĩthikwo Jerusalemu hamwe na maithe make, itũũra-inĩ inene rĩa Daudi.
21 Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn Juda mú Asariah tí ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún. Wọ́n sì ṣe é ní ọba ní ìrọ́pò baba rẹ̀ Amasiah.
Hĩndĩ ĩyo andũ othe a Juda makĩoya Azaria arĩ na mĩaka ikũmi na ĩtandatũ, makĩmũtua mũthamaki ithenya rĩa ithe Amazia.
22 Òun ni ẹni tí ó tún Elati kọ́, ó sì dá a padà sí Juda lẹ́yìn tí Amasiah ti sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀.
Nĩwe waakire Elathu rĩngĩ, na akĩrĩcookeria Juda thuutha wa Amazia kũhurũka na maithe make.
23 Ní ọdún kẹ́ẹ̀dógún tí Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda, Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ọba Israẹli di ọba ní Samaria, ó sì jẹ ọba fún ọ̀kànlélógójì ọdún.
Mwaka-inĩ wa ikũmi na ĩtano wa wathani wa Amazia mũrũ wa Joashu mũthamaki wa Juda, Jeroboamu mũrũ wa Jehoashu, mũthamaki wa Isiraeli agĩtuĩka mũthamaki kũu Samaria, na agĩthamaka mĩaka mĩrongo ĩna na ũmwe.
24 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa kò sì yípadà kúrò nínú ọ̀kankan nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati. Èyí tí ó ti fa Israẹli láti dá.
Nĩekire maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova, na ndaatiganire na mehia o na mamwe ma Jeroboamu mũrũ wa Nebati marĩa aatũmĩte Isiraeli meehie.
25 Òun ni ẹni tí ó ti dá àwọn ààlà Israẹli padà láti Lebo-Hamati sí òkú aginjù. Ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, tí ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ Jona ọmọ Amittai, wòlíì láti Gati-Heferi.
Nĩwe wacookirie mĩhaka ya Isiraeli kuuma Lebo-Hamathu nginya Iria-inĩ rĩa Araba kũringana na kiugo kĩa Jehova Ngai wa Isiraeli kĩrĩa kĩarĩtio nĩ ndungata yake Jona mũrũ wa Amitai, ũrĩa warĩ mũnabii kuuma Gathi-Heferi.
26 Olúwa ti rí ìpọ́njú Israẹli pé, ó korò gidigidi, nítorí kò sí ẹrú tàbí òmìnira tàbí olùrànlọ́wọ́ kan fún Israẹli.
Jehova nĩonete ruo rũnene rwa andũ othe a Isiraeli, arĩa maarĩ ngombo na arĩa mataarĩ ngombo, akĩona ũrĩa maathĩĩnĩkĩte, na gũtiarĩ mũndũ o na ũmwe wa kũmateithia.
27 Láti ìgbà tí Olúwa kò ti wí pé òhun yóò bu àbùkù lu orúkọ Israẹli láti abẹ́ ọ̀run. Ó gbà wọ́n là, lọ́wọ́ Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi.
Na tondũ Jehova ndoigĩte atĩ nĩegũtharia rĩĩtwa rĩa Isiraeli gũkũ thĩ-rĩ, nĩamahonokirie na guoko kwa Jeroboamu mũrũ wa Jehoashu.
28 Fún ti ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jeroboamu, gbogbo ohun tí ó ṣe àti gbogbo àwọn agbára rẹ, bí ó ti jagun sí, àti bí ó ti gba Damasku àti Hamati, tí í ṣe ti Juda, padà fún Israẹli, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
Ha ũhoro wa maũndũ marĩa mangĩ makoniĩ wathani wa Jeroboamu, ũrĩa wothe eekire, o na mbaara iria aahootanire, o na ũrĩa aatunyanĩire Isiraeli matũũra ma Dameski na Hamathu, marĩa maarĩ ma Juda tene-rĩ, githĩ matiandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩa mahinda ma athamaki a Isiraeli?
29 Jeroboamu sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, àwọn ọba Israẹli Sekariah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Jeroboamu nĩahurũkire hamwe na maithe make, o acio maarĩ athamaki a Isiraeli. Nake mũriũ Zekaria agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩake.

< 2 Kings 14 >