< 2 Kings 14 >
1 Ní ọdún kejì tí Jehoaṣi ọmọ Joahasi ọba Israẹli, Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba.
E higa mar ariyo mar loch Jehoash wuod Jehoahaz ruodh Israel, Amazia wuod Joash ruodh Juda nobedo ruoth.
2 Ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani; ó wá láti Jerusalẹmu.
Ne en ja-higni piero ariyo gabich kane obedo ruoth kendo norito Jerusalem kuom higni piero ariyo gochiko. Min mare ne nyinge Jehoadin, nyar Jerusalem.
3 Ó ṣe ohun tí ó tọ́ ní ojú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí i Dafidi baba a rẹ̀ tí ṣe. Nínú ohun gbogbo, ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ baba a rẹ̀ Joaṣi.
Notimo gima kare e nyim Jehova Nyasaye, to ok kaka Daudi kwar mare notimo. Noluwo tim wuon mare Joash e gik moko duto.
4 Àwọn ibi gíga bí ó ti wù kí ó rí, a kò sí i kúrò, àwọn ènìyàn sì tẹ̀síwájú láti rú ẹbọ àti sun tùràrí níbẹ̀.
Kata kamano kuonde motingʼore gi malo mag wangʼo misengini ne ok omuki, kendo ji nodhi nyime mana gi chiwo misengini kod wangʼo ubani mangʼwe ngʼar kanyo.
5 Lẹ́yìn tí ó ti fi ọwọ́ gbá ìjọba rẹ̀ mú gbọingbọin, ó pa àwọn oníṣẹ́ tí wọ́n ti pa baba a rẹ̀ ọba.
Bangʼ ka pinyruodhe nosegurore maber, nonego jotelo mane onego wuon mare mane ruoth.
6 Síbẹ̀ kò pa ọmọ àwọn apànìyàn náà. Ní ìbámu pẹ̀lú ohun tí a kọ sínú ìwé òfin Mose níbi tí Olúwa ti paláṣẹ pé, “A kì yóò pa baba nítorí àwọn ọmọ, tàbí àwọn ọmọ nítorí àwọn baba; olúkúlùkù ni kí ó kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.”
Kata kamano ne ok onego yawuot jonekgo koluwo gima ondikie Kitap Chik mar Musa mane Jehova Nyasaye oketo mawacho niya, “Wuone ok nonegi nikech ketho mag nyithindgi, bende nyithindo kik negi nikech ketho mag wuonegi; to ngʼato ka ngʼato nonegi nikech richone owuon.”
7 Òun ni ẹni tí ó ṣẹ́gun ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ará Edomu ní àfonífojì iyọ̀, ó sì fi agbára mú Sela nínú ogun, tí ó ń pè é ní Jokteeli, orúkọ tí ó ní títí di òní.
Amazia ema ne oloyo jolweny jo-Edom alufu apar e holo mar Chumbi kendo nomako Sela e lweny, moloko nyinge ni Jokthel, kendo pod iluonge kamano nyaka chil kawuono.
8 Nígbà náà, Amasiah rán àwọn ìránṣẹ́ sí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu ọba Israẹli pẹ̀lú ìpèníjà: “Wá, jẹ́ kí á wo ara wa ní ojú.”
Bangʼ mano Amazia nooro joote ir Jehoash wuod Jehoahaz, ma wuod Jehu ruodh Israel, kosieme niya, “Bi warom wangʼ gi wangʼ.”
9 Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì sí Amasiah ọba Juda: “Òṣùṣú kan ní Lebanoni rán iṣẹ́ sí kedari ní Lebanoni, ‘Fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ní ìgbéyàwó.’ Nígbà náà ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin tinú igbó ní Lebanoni wá pẹ̀lú ó sì fi ẹsẹ̀ tẹ òṣùṣú náà mọ́lẹ̀.
To Jehoash ruodh Israel nodwoko Amazia ruodh Juda gi ngero niya, “Kuth alii man Lebanon nooro wach ne yiend sida man Lebanon ni, ‘Yie ichiw nyari ne wuoda mondo okendi.’ To le moro mar bungu mowuok Lebanon nokadho kanyo monyono kuth aliino gi tiende.
10 Ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu pẹ̀lú, ṣùgbọ́n, nísinsin yìí ìwọ ṣe ìgbéraga. Ògo nínú ìṣẹ́gun rẹ, ṣùgbọ́n dúró nílé! Kí ni ó dé tí o fi ń wá wàhálà tí o sì fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀lú?”
En adier ni iseloyo jo-Edom kendo koro iwuoyo marach. Bed mamor kuom lochnino, to kik iwuogi e dala! Angʼo momiyo imanyo lweny mabiro tieki kaachiel gi jo-Juda duto?”
11 Bí ó ti wù kí ó rí Amasiah kò ní tẹ́tí, bẹ́ẹ̀ ni Jehoaṣi ọba Israẹli sì dojúkọ ọ́. Òun àti Amasiah ọba Juda kọjú sí ara wọn ní Beti-Ṣemeṣi ní Juda.
Kata kamano Amazia ne ok odewo, omiyo Jehoash ruodh Israel nomonje. Jehoash kod Amazia ruodh Juda ne joromo e lweny e dala mar Beth Shemesh man Juda.
12 A kó ipa ọ̀nà Juda nípasẹ̀ Israẹli, gbogbo àwọn ọkùnrin sì sálọ sí ilé e rẹ̀.
Jo-Israel noloyo jo-Juda kendo ngʼato ka ngʼato noringo kochomo dalane.
13 Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára mú Amasiah ọba Juda, ọmọ Jehoaṣi, ọmọ Ahasiah ní Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà, Jehoaṣi lọ sí Jerusalẹmu, ó sì lọ wó odi Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ìlẹ̀kùn Efraimu sí ibi igun ìlẹ̀kùn. Ìpín kan tí ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ irinwó ìgbọ̀nwọ́.
Jehoash ruodh Israel nomako Amazia ruodh Juda, ma wuod Joash, ma wuod Ahazia e Beth Shemesh. Bangʼe Jehoash nodhi Jerusalem kendo nomuko ohinga mar Jerusalem chakre e dhoranga Efraim nyaka kama ohinga ogomogo; bor kama ne omuko ne romo fut mia abich gi piero ochiko gachiel.
14 Ó mú gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun tí ó rí nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa àti níbi ìfowópamọ́ sí nínú ààfin ọba. Ó mú àwọn ògo, ó sì dá wọn padà sí Samaria.
Nokawo dhahabu gi fedha duto kod gik moko duto mane oyudo e hekalu mar Jehova Nyasaye kod mwandu duto mane ni e od ruoth, bende nokawo. Ji moko mano mako e lweny, bangʼe nodok e piny Samaria.
15 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Jehoaṣi, gbogbo ohun tí ó ṣe pẹ̀lú àṣeyọrí rẹ̀, pẹ̀lú ogun rẹ̀ sí Amasiah ọba Juda, ṣé a kò kọ wọ́n sí inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
To kuom gik mamoko duto mane otimore e ndalo loch Jehoash, gi gik moko duto mane otimo kod teko mane okedogi Amazia ruodh Juda, donge ondikgi e kitepe mag weche ruodhi mag Israel?
16 Jehoaṣi sì sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín sí Samaria pẹ̀lú àwọn ọba Israẹli. Jeroboamu ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Jehoash notho moyweyo gi kwerene kendo noyike Samaria gi ruodhi Israel kendo Jeroboam wuode nobedo ruoth kare.
17 Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli.
Amazia wuod Joash ruodh Juda nodak higni apar gabich bangʼ tho Jehoash wuod Jehoahaz ruodh Israel.
18 Fún ti ìyókù iṣẹ́ rẹ̀ nígbà ìjọba Amasiah, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda?
To weche mamoko mag loch Amazia, donge ondikgi e kitap weche ruodhi mag Juda?
19 Wọ́n dìtẹ̀ sí i ní Jerusalẹmu, ó sì sálọ sí Lakiṣi, ṣùgbọ́n wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀lé e sí Lakiṣi, wọ́n sì pa á síbẹ̀.
Negichikone obadho e Jerusalem mi oringo odhi Lakish, to negioro ji bangʼe Lakish ma onege kuno.
20 Wọ́n gbé e padà pẹ̀lú ẹṣin, a sì sin ín sí Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, ní ìlú ńlá ti Dafidi.
Noduog ringre kotingʼ gi faras kendo noyike Jerusalem but kwerene e Dala Maduongʼ mar Daudi.
21 Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn Juda mú Asariah tí ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún. Wọ́n sì ṣe é ní ọba ní ìrọ́pò baba rẹ̀ Amasiah.
Eka jo-Juda duto nokawo Azaria mane hike apar gi auchiel mokete ruoth kar wuon mare Amazia.
22 Òun ni ẹni tí ó tún Elati kọ́, ó sì dá a padà sí Juda lẹ́yìn tí Amasiah ti sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀.
En ema ne ogero kuonde mane omukore mag Elath, mi odwoke ne Juda bangʼ ka ruoth Amazia nosetho moike gi kwerene.
23 Ní ọdún kẹ́ẹ̀dógún tí Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda, Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ọba Israẹli di ọba ní Samaria, ó sì jẹ ọba fún ọ̀kànlélógójì ọdún.
E higa mar apar gabich mar Amazia wuod Joash ruodh Juda, Jeroboam wuod Jehoash ruodh Israel nobedo ruodh Samaria kendo nobedo ruoth kuom higni piero angʼwen gachiel.
24 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa kò sì yípadà kúrò nínú ọ̀kankan nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati. Èyí tí ó ti fa Israẹli láti dá.
Timbene ne richo e nyim Jehova Nyasaye kendo ne ok olokore weyo yore mag richo mar Jeroboam wuod Nebat, mane omiyo jo-Israel otimo.
25 Òun ni ẹni tí ó ti dá àwọn ààlà Israẹli padà láti Lebo-Hamati sí òkú aginjù. Ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, tí ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ Jona ọmọ Amittai, wòlíì láti Gati-Heferi.
En ema ne odwoko tongʼ mag Israel chakre Lebo Hamath nyaka chop Nam mar Araba, kaluwore gi wach Jehova Nyasaye, ma Nyasach Israel, mane owacho koa e dho jatichne Jona wuod Amitai, mane janabi moa Gath Hefer.
26 Olúwa ti rí ìpọ́njú Israẹli pé, ó korò gidigidi, nítorí kò sí ẹrú tàbí òmìnira tàbí olùrànlọ́wọ́ kan fún Israẹli.
Jehova Nyasaye noneno kaka joma ni Israel ne sandore malit, bedni ne gin wasumbini kata ok gin wasumbini; maonge ngʼama ne nyalo resogi.
27 Láti ìgbà tí Olúwa kò ti wí pé òhun yóò bu àbùkù lu orúkọ Israẹli láti abẹ́ ọ̀run. Ó gbà wọ́n là, lọ́wọ́ Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi.
To nikech Jehova Nyasaye ne pok owacho ni obiro golo nying jo-Israel e piny, nomiyo Jeroboam wuod Jehoash oresogi.
28 Fún ti ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jeroboamu, gbogbo ohun tí ó ṣe àti gbogbo àwọn agbára rẹ, bí ó ti jagun sí, àti bí ó ti gba Damasku àti Hamati, tí í ṣe ti Juda, padà fún Israẹli, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
To kuom gik mamoko duto mane otimore e ndalo loch Jeroboam kod lochne e lwenje duto, kaachiel gi kaka noduogo Damaski kod Hamath mane ni e lwet Juda ne Israel; donge ondikgi e kitepe mag weche ruodhi mag Israel.
29 Jeroboamu sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, àwọn ọba Israẹli Sekariah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Jeroboam notho moyweyo gi kwerene, mane ruodhi mag Israel kendo Zekaria wuode nobedo ruoth kare.