< 2 John 1 >
1 Alàgbà, Sì àyànfẹ́ obìnrin ọlọ́lá àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn tí mo fẹ́ ní òtítọ́, kì í sì í ṣe èmi nìkan, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn tí ó mọ òtítọ́ pẹ̀lú;
ⲁ̅ⲡⲓ⳿ⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲛϯⲥⲱⲧⲡ ⲕⲩⲣⲓⲁ ⲛⲉⲙ ⲛⲉⲥϣⲏⲣⲓ ⲛⲏ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⳿ⲉϯⲙⲉⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧ ⲁⲛ ⲁⲗⲗⲁ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲁⲩⲥⲟⲩⲉⲛ ϯⲙⲉⲑⲙⲏⲓ.
2 nítorí òtítọ́ tí ń gbé inú wa, yóò sì bá wa gbé títí: (aiōn )
ⲃ̅ⲉⲑⲃⲉ ϯⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲉⲧϣⲟⲡ ⳿ⲛϧⲏⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙⲁⲛ ϣⲁ ⲉⲛⲉϩ. (aiōn )
3 Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò wà pẹ̀lú wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.
ⲅ̅⳿ⲡ⳿ϩⲙⲟⲧ ⳿ⲫⲛⲁⲓ ⳿ⲧϩⲓⲣⲏⲛⲏ ⲉⲩ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙⲁⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲫϯ ⳿ⲫⲓⲱⲧ ⲛⲉⲙ ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲡⲉⲛ⳪ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⳿ⲡϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲓⲱⲧ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲁⲅⲁⲡⲏ.
4 Mo yọ̀ gidigidi pé mo rí nínú àwọn ọmọ rẹ tí ń rìn nínú òtítọ́, gẹ́gẹ́ bí Baba ti pa àṣẹ fún wa.
ⲇ̅ⲁⲓⲣⲁϣⲓ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ ⳿ⲉⲧⲁⲓϫⲓⲙⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲉϣⲏⲣⲓ ⲉⲩⲙⲟϣⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲁⲛϭⲓ ⳿ⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ⳿ⲛⲧⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲱⲧ.
5 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, mo bẹ̀ ọ́, obìnrin ọlọ́lá, kì í ṣe bí ẹni pé èmi ń kọ̀wé òfin tuntun kan sí ọ, bí kò ṣe èyí ti àwa tí ní ní àtètèkọ́ṣe, pé kí àwa fẹ́ràn ara wa.
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ϯⲛⲟⲩ ϯϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟ ⲕⲩⲣⲓⲁ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ϫⲉ ⲟⲩ⳿ⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ⲁⲛ ⳿ⲉϯ⳿ⲥϧⲁⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲉ ⲁⲗⲗⲁ ⲑⲏ ⲉⲛⲁⲥ⳿ⲛⲧⲟⲧⲉⲛ ⲓⲥϫⲉⲛ ϩⲏ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲉⲣⲁⲅⲁⲡⲁⲛ ⳿ⲛⲛⲉⲛⲉⲣⲏⲟⲩ.
6 Èyí sì ni ìfẹ́, pé, kí àwa máa rin nípa òfin rẹ̀, èyí ni òfin náà, àní bí ẹ ti gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, pé, kí ẹ̀yin rìn nínú rẹ̀.
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲑⲁⲓ ⲧⲉ ϯⲁⲅⲁⲡⲏ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲙⲟϣⲓ ⲕⲁⲧⲁ ⲛⲉϥ⳿ⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲑⲁⲓ ⲧⲉ ϯ ⳿ⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ϩⲓⲛⲁ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲥⲱⲧⲉⲙ ⲓⲥϫⲉⲛ ϩⲏ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲙⲟϣⲓ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ.
7 Nítorí ẹlẹ́tàn púpọ̀ ti jáde wa sínú ayé, àwọn tí kò jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá nínú ara. Èyí ni ẹlẹ́tàn àti aṣòdì sí Kristi.
ⲍ̅ϫⲉ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲙ⳿ⲡⲗⲁⲛⲟⲥ ⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲡⲓⲕⲟⲥⲙⲟⲥ ⲛⲏⲉⲧⲉ ⳿ⲛⲥⲉⲉⲣⲟⲙⲟⲗⲟⲅⲓⲛ ⲁⲛ ⳿ⲛⲒⲏ̅ⲥ̅ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ϫⲉ ⲁϥ⳿ⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲥⲁⲣⲝ ⲫⲁⲓ ⲡⲉ ⲡⲓ⳿ⲡⲗⲁⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲁⲛⲧⲓ⳿ⲭⲣⲓⲥⲧⲟⲥ.
8 Ẹ kíyèsára yín, kí ẹ má ba à sọ iṣẹ́ tí ẹ tí ṣe nù, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin lè rí èrè kíkún gbà.
ⲏ̅ⲥⲟⲙⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉⲣⲱⲧⲉⲛ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲧⲉⲛ⳿ϣⲧⲉⲙⲧⲁⲕⲉ ⲫⲏⲉⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲉⲣϩⲱⲃ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲧⲉⲛϭⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲃⲉⲭⲉ ⲉϥϫⲏⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
9 Olúkúlùkù ẹni tí ó bá ń rú òfin tí kò si dúró nínú ẹ̀kọ́ Kristi, kò mọ Ọlọ́run. Ẹni tí ó bá dúró nínú ẹ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ.
ⲑ̅ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲑⲙⲟϣⲓ ⳿ⲉ⳿ⲧϩⲏ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥ⳿ϣⲧⲉⲙⲟϩⲓ ϧⲉⲛ ϯ⳿ⲥⲃⲱ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⲁⲩⲁⲑⲛⲛⲟⲩϯ ⲡⲉ ⲫⲏ ⲇⲉ ⲉⲑⲛⲁⲟϩⲓ ϧⲉⲛ ϯ⳿ⲥⲃⲱ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⲫⲁⲓ ⳿ⲫⲓⲱⲧ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡϣⲏⲣⲓ.
10 Bí ẹnikẹ́ni bá tọ̀ yín wá, tí kò sì mu ẹ̀kọ́ yìí wá, ẹ má ṣe gbà á sí ilé, kí ẹ má sì ṣe kí i kú ààbọ̀.
ⲓ̅ⲫⲏⲉⲑⲛⲏⲟⲩ ϩⲁⲣⲱⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲓⲛⲓ ⳿ⲛⲧⲁⲓ⳿ⲥⲃⲱ ⲁⲛ ⳿ⲙⲡⲉⲣ⳿ⲟⲗϥ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲏⲓ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ⲙⲡⲉⲣϫⲟⲥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲭⲉⲣⲉ.
11 Nítorí ẹni tí ó bá kí kú ààbọ̀, ó ní ọwọ́ nínú iṣẹ́ búburú rẹ̀.
ⲓ̅ⲁ̅ⲫⲏ ⲅⲁⲣ ⲉⲑⲛⲁϫⲟⲥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲭⲉⲣⲉ ⳿ϥⲟⲓ ⳿ⲛ⳿ϣⲫⲏⲣ ⳿ⲉⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲧϩⲱⲟⲩ.
12 Bí mo tilẹ̀ ní ohun púpọ̀ láti ṣe alábápín pẹ̀lú yín, síbẹ̀ èmi kò fẹ́ lo ìwé ìkọ̀wé àti jẹ́lú ìkọ̀wé. Ṣùgbọ́n èmi ní ìrètí láti tọ̀ yín wá àti láti bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú, kí ayọ̀ yín bá à le è kún.
ⲓ̅ⲃ̅⳿ⲉⲟⲩⲟⲛϯ ⲟⲩⲙⲏϣ ⲉⲥϧⲏⲧⲟⲩ ⲛⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲙⲡⲓⲟⲩⲱϣ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲟⲩϫⲱⲙ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲙⲉⲗⲁ ϯⲉⲣϩⲉⲗⲡⲓⲥ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲱⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲛⲣⲟ ⲟⲩⲃⲉ ⲣⲟ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉⲧⲉⲛⲣⲁϣⲓ ϣⲱⲡⲓ ⲉϥϫⲏⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
13 Àwọn ọmọ arábìnrin rẹ àyànfẹ́ kí ọ.
ⲓ̅ⲅ̅ⲥⲉϣⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲣⲟ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓϣⲏⲣⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲉⲥⲱⲛⲓ ⲑⲏ ⲉⲧⲥⲟⲧⲡ ⲓⲱⲁⲛⲛⲟⲩ ⳿ⲉⲡⲓⲥⲧⲟⲗⲏ ⲃ̅