< 2 John 1 >

1 Alàgbà, Sì àyànfẹ́ obìnrin ọlọ́lá àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn tí mo fẹ́ ní òtítọ́, kì í sì í ṣe èmi nìkan, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn tí ó mọ òtítọ́ pẹ̀lú;
ہے اَبھِرُچِتے کُرِیے، تْواں تَوَ پُتْراںشْچَ پْرَتِ پْراچِینوہَں پَتْرَں لِکھامِ۔
2 nítorí òtítọ́ tí ń gbé inú wa, yóò sì bá wa gbé títí: (aiōn g165)
سَتْیَمَتادْ یُشْماسُ مَمَ پْریماسْتِ کیوَلَں مَمَ نَہِ کِنْتُ سَتْیَمَتَجْناناں سَرْوّیشامیوَ۔ یَتَح سَتْیَمَتَمْ اَسْماسُ تِشْٹھَتْیَنَنْتَکالَں یاوَچّاسْماسُ سْتھاسْیَتِ۔ (aiōn g165)
3 Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò wà pẹ̀lú wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.
پِتُرِیشْوَراتْ تَتْپِتُح پُتْراتْ پْرَبھو رْیِیشُکھْرِیشْٹاچَّ پْراپْیو نُگْرَہَح کرِپا شانْتِشْچَ سَتْیَتاپْریمَبھْیاں سارْدّھَں یُشْمانْ اَدھِتِشْٹھَتُ۔
4 Mo yọ̀ gidigidi pé mo rí nínú àwọn ọmọ rẹ tí ń rìn nínú òtítọ́, gẹ́gẹ́ bí Baba ti pa àṣẹ fún wa.
وَیَں پِترِتو یامْ آجْناں پْراپْتَوَنْتَسْتَدَنُسارینَ تَوَ کیچِدْ آتْمَجاح سَتْیَمَتَمْ آچَرَنْتْییتَسْیَ پْرَمانَں پْراپْیاہَں بھرِشَمْ آنَنْدِتَوانْ۔
5 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, mo bẹ̀ ọ́, obìnrin ọlọ́lá, kì í ṣe bí ẹni pé èmi ń kọ̀wé òfin tuntun kan sí ọ, bí kò ṣe èyí ti àwa tí ní ní àtètèkọ́ṣe, pé kí àwa fẹ́ràn ara wa.
سامْپْرَتَنْچَ ہے کُرِیے، نَوِیناں کانْچِدْ آجْناں نَ لِکھَنَّہَمْ آدِتو لَبْدھامْ آجْناں لِکھَنْ تْوامْ اِدَں وِنَیے یَدْ اَسْمابھِح پَرَسْپَرَں پْریمَ کَرْتَّوْیَں۔
6 Èyí sì ni ìfẹ́, pé, kí àwa máa rin nípa òfin rẹ̀, èyí ni òfin náà, àní bí ẹ ti gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, pé, kí ẹ̀yin rìn nínú rẹ̀.
اَپَرَں پْریمَیتینَ پْرَکاشَتے یَدْ وَیَں تَسْیاجْنا آچَریمَ۔ آدِتو یُشْمابھِ رْیا شْرُتا سییَمْ آجْنا سا چَ یُشْمابھِراچَرِتَوْیا۔
7 Nítorí ẹlẹ́tàn púpọ̀ ti jáde wa sínú ayé, àwọn tí kò jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá nínú ara. Èyí ni ẹlẹ́tàn àti aṣòdì sí Kristi.
یَتو بَہَوَح پْرَوَنْچَکا جَگَتْ پْرَوِشْیَ یِیشُکھْرِیشْٹو نَراوَتارو بھُوتْواگَتَ ایتَتْ نانْگِیکُرْوَّنْتِ سَ ایوَ پْرَوَنْچَکَح کھْرِیشْٹارِشْچاسْتِ۔
8 Ẹ kíyèsára yín, kí ẹ má ba à sọ iṣẹ́ tí ẹ tí ṣe nù, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin lè rí èrè kíkún gbà.
اَسْماکَں شْرَمو یَتْ پَنْڈَشْرَمو نَ بھَویتْ کِنْتُ سَمْپُورْنَں ویتَنَمَسْمابھِ رْلَبھْییتَ تَدَرْتھَں سْوانَدھِ ساوَدھانا بھَوَتَح۔
9 Olúkúlùkù ẹni tí ó bá ń rú òfin tí kò si dúró nínú ẹ̀kọ́ Kristi, kò mọ Ọlọ́run. Ẹni tí ó bá dúró nínú ẹ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ.
یَح کَشْچِدْ وِپَتھَگامِی بھُوتْوا کھْرِیشْٹَسْیَ شِکْشایاں نَ تِشْٹھَتِ سَ اِیشْوَرَں نَ دھارَیَتِ کھْرِیشْٹَسْیَ شِجْنایاں یَسْتِشْٹھَتِ سَ پِتَرَں پُتْرَنْچَ دھارَیَتِ۔
10 Bí ẹnikẹ́ni bá tọ̀ yín wá, tí kò sì mu ẹ̀kọ́ yìí wá, ẹ má ṣe gbà á sí ilé, kí ẹ má sì ṣe kí i kú ààbọ̀.
یَح کَشْچِدْ یُشْمَتْسَنِّدھِماگَچّھَنْ شِکْشامیناں نانَیَتِ سَ یُشْمابھِح سْوَویشْمَنِ نَ گرِہْیَتاں تَوَ مَنْگَلَں بھُویادِتِ واگَپِ تَسْمَے نَ کَتھْیَتاں۔
11 Nítorí ẹni tí ó bá kí kú ààbọ̀, ó ní ọwọ́ nínú iṣẹ́ búburú rẹ̀.
یَتَسْتَوَ مَنْگَلَں بھُویادِتِ واچَں یَح کَشْچِتْ تَسْمَے کَتھَیَتِ سَ تَسْیَ دُشْکَرْمَّنامْ اَںشِی بھَوَتِ۔
12 Bí mo tilẹ̀ ní ohun púpọ̀ láti ṣe alábápín pẹ̀lú yín, síbẹ̀ èmi kò fẹ́ lo ìwé ìkọ̀wé àti jẹ́lú ìkọ̀wé. Ṣùgbọ́n èmi ní ìrètí láti tọ̀ yín wá àti láti bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú, kí ayọ̀ yín bá à le è kún.
یُشْمانْ پْرَتِ مَیا بَہُونِ لیکھِتَوْیانِ کِنْتُ پَتْرَمَسِیبھْیاں تَتْ کَرْتُّں نیچّھامِ، یَتو سْماکَمْ آنَنْدو یَتھا سَمْپُورْنو بھَوِشْیَتِ تَتھا یُشْمَتْسَمِیپَمُپَسْتھایاہَں سَمُّکھِیبھُویَ یُشْمابھِح سَمْبھاشِشْیَ اِتِ پْرَتْیاشا مَماسْتے۔
13 Àwọn ọmọ arábìnrin rẹ àyànfẹ́ kí ọ.
تَوابھِرُچِتایا بھَگِنْیا بالَکاسْتْواں نَمَسْکارَں جْناپَیَنْتِ۔ آمینْ۔

< 2 John 1 >