< 2 John 1 >

1 Alàgbà, Sì àyànfẹ́ obìnrin ọlọ́lá àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn tí mo fẹ́ ní òtítọ́, kì í sì í ṣe èmi nìkan, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn tí ó mọ òtítọ́ pẹ̀lú;
Kuuma kũrĩ niĩ Mũthuuri wa Kanitha, Ndaandĩka marũa maya kũrĩ mũtumia ũrĩa mũthuure, o hamwe na ciana ciake, arĩa nyendete kũna kũna, na to niĩ nyiki, no nĩ hamwe na arĩa othe mamenyete ũhoro ũrĩa wa ma:
2 nítorí òtítọ́ tí ń gbé inú wa, yóò sì bá wa gbé títí: (aiōn g165)
makamwenda tondũ wa ũhoro ũrĩa wa ma, ũrĩa ũtũũraga thĩinĩ witũ, o na ũgũtũũra na ithuĩ nginya tene: (aiōn g165)
3 Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò wà pẹ̀lú wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.
Wega, na tha, na thayũ kuuma kũrĩ Ngai Ithe, na kuuma kũrĩ Jesũ Kristũ, o we Mũriũ wa Ithe witũ, irĩikaraga na ithuĩ thĩinĩ wa ũhoro wa ma, na wa wendo.
4 Mo yọ̀ gidigidi pé mo rí nínú àwọn ọmọ rẹ tí ń rìn nínú òtítọ́, gẹ́gẹ́ bí Baba ti pa àṣẹ fún wa.
Nĩngenete mũno nĩkuona ciana imwe ciaku igĩthiĩ na njĩra ya ũhoro ũrĩa wa ma, o ta ũrĩa Ithe witũ aatwathire.
5 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, mo bẹ̀ ọ́, obìnrin ọlọ́lá, kì í ṣe bí ẹni pé èmi ń kọ̀wé òfin tuntun kan sí ọ, bí kò ṣe èyí ti àwa tí ní ní àtètèkọ́ṣe, pé kí àwa fẹ́ràn ara wa.
Na rĩu, mũtumia ũyũ mwende, ti rĩathani rĩerũ ndĩrakwandĩkĩra, no nĩ rĩrĩa tũtũire narĩo kuuma o kĩambĩrĩria. Ngũũria atĩ twendanage mũndũ na ũrĩa ũngĩ.
6 Èyí sì ni ìfẹ́, pé, kí àwa máa rin nípa òfin rẹ̀, èyí ni òfin náà, àní bí ẹ ti gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, pé, kí ẹ̀yin rìn nínú rẹ̀.
Naguo wendani nĩ atĩrĩ: Atĩ tũthiiage na njĩra ya gwathĩkĩra maathani make. O ta ũrĩa mũiguĩte kuuma o kĩambĩrĩria, rĩathani rĩake nĩ atĩ mũthiiage mũrĩ o na wendani ũcio.
7 Nítorí ẹlẹ́tàn púpọ̀ ti jáde wa sínú ayé, àwọn tí kò jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá nínú ara. Èyí ni ẹlẹ́tàn àti aṣòdì sí Kristi.
Aheenania, aingĩ arĩa matetĩkĩtie atĩ Jesũ Kristũ ookire arĩ na mwĩrĩ, nĩmarorũũra gũkũ thĩ. Mũndũ ta ũcio nĩ mũheenania na nĩ mũmena-Kristũ.
8 Ẹ kíyèsára yín, kí ẹ má ba à sọ iṣẹ́ tí ẹ tí ṣe nù, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin lè rí èrè kíkún gbà.
Mwĩhũgagei nĩguo mũtigate kĩrĩa mũrutĩire wĩra, no mũtuĩke a gũkaaheo mũcaara wanyu ũrĩ wothe.
9 Olúkúlùkù ẹni tí ó bá ń rú òfin tí kò si dúró nínú ẹ̀kọ́ Kristi, kò mọ Ọlọ́run. Ẹni tí ó bá dúró nínú ẹ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ.
Mũndũ o wothe ũkĩraga njano akarega kũrũmĩrĩra ũrutani wa Kristũ, ũcio ndakoragwo na Ngai; no ũrĩa ũikaraga ũrutani-inĩ ũcio, we arĩ na Ithe witũ o na Mũriũ.
10 Bí ẹnikẹ́ni bá tọ̀ yín wá, tí kò sì mu ẹ̀kọ́ yìí wá, ẹ má ṣe gbà á sí ilé, kí ẹ má sì ṣe kí i kú ààbọ̀.
Mũndũ o wothe angĩũka kũrĩ inyuĩ arĩ na ũrutani ũngĩ tiga ũcio-rĩ, mũtikanamũnyiite ũgeni o na kana mũmwamũkĩre kwanyu mũciĩ.
11 Nítorí ẹni tí ó bá kí kú ààbọ̀, ó ní ọwọ́ nínú iṣẹ́ búburú rẹ̀.
Mũndũ wothe ũngĩmwamũkĩra, nĩkũgwatanĩra magwatanĩire nake ciĩko ciake cia waganu.
12 Bí mo tilẹ̀ ní ohun púpọ̀ láti ṣe alábápín pẹ̀lú yín, síbẹ̀ èmi kò fẹ́ lo ìwé ìkọ̀wé àti jẹ́lú ìkọ̀wé. Ṣùgbọ́n èmi ní ìrètí láti tọ̀ yín wá àti láti bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú, kí ayọ̀ yín bá à le è kún.
Ndĩ na maũndũ maingĩ ma kũmwandĩkĩra, no ndikwenda kũhũthĩra karatathi na rangi. Handũ ha ũguo-rĩ, ndĩrehoka kũmũceerera njaranĩrie na inyuĩ tũkĩonanaga, nĩgeetha gĩkeno giitũ kĩiganĩre.
13 Àwọn ọmọ arábìnrin rẹ àyànfẹ́ kí ọ.
Nĩmwageithio nĩ ciana cia mwarĩ wa maitũguo ũrĩa mũthuure.

< 2 John 1 >