< 2 Chronicles 9 >

1 Nígbà tí ayaba Ṣeba gbọ́ nípa òkìkí Solomoni, ó sì wá sí Jerusalẹmu láti dán an wò pẹ̀lú ìbéèrè tí ó le. Ó dé pẹ̀lú ẹgbẹ́ ńlá kan pẹ̀lú ìbákasẹ tí ó ru tùràrí, ọ̀pọ̀lọpọ̀ iye wúrà, àti òkúta iyebíye, ó wá sí ọ̀dọ̀ Solomoni ó sì sọ̀rọ̀ pẹ̀lú rẹ̀ nípa gbogbo ohun tí ó ní lọ́kàn rẹ̀.
Siba sogega uda hina bagade da Soloumane ea gasa bagade hou nababeba: le, e da Yelusaleme moilai bai bagadega ema gasa bagadewane adoba: musa: misi. E da ea fidisu dunu amola uda bagohame oule misi. Amola ga: mele amo da: iya da hedama: ne fodole nasu amola nina: hamomusa: noga: idafa igi amola gouli bagadedafa, amo e da oule misi. E da Soloumanema gousa: beba: le, e da ea asigi dawa: su defele, Soloumanema bagadewane adole ba: i.
2 Solomoni sì dá a lóhùn gbogbo ìbéèrè rẹ̀; kò sì sí èyíkéyìí tí kò lè ṣe àlàyé fún.
Soloumane da amo adole ba: su huluane defele bu adole i. Adole ba: su afadafa e bu adole imunu hamedei da hamedafa galu.
3 Nígbà tí ayaba Ṣeba rí ọgbọ́n Solomoni àti pẹ̀lú ilé tí ó ti kọ́,
Siba sogega uda hina bagade da Soloumane ea bagade dawa: su nabi. E da hina bagade diasu ea gagui liligi, amo ba: i dagoi.
4 oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì rẹ̀, àti ìjókòó àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀, àti dídúró àwọn ìránṣẹ́ nínú aṣọ wọn, àti àwọn agbọ́tí nínú aṣọ wọn àti ẹbọ sísun tí ó ṣe ní ilé Olúwa, ó sì dá a lágara fún ìyàlẹ́nu.
E da ha: i manu amo hina bagade diasu ea esalebe dunu ilia da nasu amola Soloumane ea eagene ouligisu dunu ilia diasu amola ea hawa: hamosu dunu ilia hamobe amola ilia afaididi salasu abula amola hawa: hamosu dunu amo da ea lolo nabe ganodini e fidi amola gobele salasu hou e da Debolo Diasuga hamoi, amo huluane ba: beba: le, Siba uda hina da baligili fofogadigili, dogo gulugului ba: i.
5 Ó sì wí fún ọba pé, “Ìròyìn tí mo gbọ́ ní ìlú mi nípa iṣẹ́ rẹ àti ọgbọ́n rẹ, òtítọ́ ni.
E da hina bagade Soloumanema amane sia: i, “Na sogega esaloba, na da dia hou amola bagade dawa: su hou nabi dagoi. Na da wali ba: sa - amo huluane da dafawanedafa.
6 Ṣùgbọ́n èmi kò gba ohun tí wọ́n sọ gbọ́ àyàfi ìgbà tí mó dé ibí tí mo sì ri pẹ̀lú ojú mi. Nítòótọ́, kì í tilẹ̀ ṣe ìdájọ́ ìdajì títóbi ọgbọ́n rẹ ní a sọ fún mi: ìwọ ti tàn kọjá òkìkí tí mo gbọ́.
Be amo na da dafawaneyale hame dawa: beba: le, na da nisu amo ba: musa: , guiguda: misunusa: dawa: i. Be dia hou la: idi fonobahadi fawane na da nabi. Dia bagade dawa: su amola gaguiwane hou da nama adoi amo bagade baligisa.
7 Báwo ni inú àwọn ọkùnrin rẹ ìbá ṣe dùn tó! Báwo ní dídùn inú àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn tí n dúró nígbà gbogbo níwájú rẹ láti gbọ́ ọgbọ́n rẹ!
Dia hawa: hamosu dunu da eso huluane dili esalebeba: le amola dia bagade dawa: su sia: nabalebeba: le, ilia da hahawane bagade.
8 Ìyìn ló yẹ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó ní inú dídùn nínú rẹ tí ó sì gbé ọ ka orí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀ láti jẹ ọba fún Olúwa Ọlọ́run rẹ. Nítorí ìfẹ́ Ọlọ́run rẹ fún Israẹli láti fi ìdí wọn kalẹ̀ láéláé, ó sì ti fi ọ́ ṣe ọba lórí wọn, láti ṣe ìdájọ́ àti òtítọ́.”
Dia Hina Godema nodoma! E da Dima hahawane bagade hou amo olelema: ne, di Isala: ili fi amo ouligima: ne ilegei. E da Isala: ili fi ilima eso huluane mae fisili asigimuba: le, e da di Ea sema noga: le ouligima: ne amola Isala: ili molole ouligima: ne, ilegei dagoi.”
9 Nígbà náà ni ó sì fún ọba ní ọgọ́fà tálẹ́ǹtì wúrà. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iye tùràrí, àti òkúta iyebíye. Kò sì tí ì sí irú tùràrí yí gẹ́gẹ́ bí èyí tí ayaba Ṣeba fi fún ọba Solomoni.
Siba sogega uda hina bagade da hina bagade Soloumanema iasu liligi e da gaguli misi, amo ema i. Amo da gouli defei danese biyaduyale gadenei amola hedama: ne fodole nasu amola nina: hamosu noga: idafa igi bagohame. Hedama: ne fodole nasu amo e da ema i da, eno dunu musa: ema iasu amo bagadewane baligi.
10 Àwọn ènìyàn Hiramu àti àwọn ọkùnrin Solomoni gbé wúrà wá láti Ofiri, wọ́n sì tún gbé igi algumu pẹ̀lú àti òkúta iyebíye wá.
(Haila: me ea dusagai gilisi da Oufe sogega gouli bagade gaguli misi. Amola ilia da amoga ‘yunibe’ ifa amola nina: hamosu igi bagohamedafa gaguli misi.
11 Ọba sì lo igi algumu náà láti fi ṣe àtẹ̀gùn fún ilé Olúwa àti fún ilé ọba àti láti fi ṣe dùùrù àti ohun èlò orin olókùn fún àwọn akọrin. Kò sì ṣí irú rẹ̀ tí a ti rí rí ní ilẹ̀ Juda.
Soloumane da amo ‘yunibe’ ifa amoga fa: gu amo Debolo Diasu amola hina bagade diasu ganodini hahamoi. Amola amoga e da sani baidama amola ‘laia’ amo gesami hea: su dunu fidima: ne hahamoi. Amo ‘yunibe’ ifa da noga: idafa. Dunu da musa: agoai liligi Isala: ili amoga hame gaguli misi. Amola fa: no, agoai liligi da Isala: ili sogega hamedafa ba: i.)
12 Ọba Solomoni fún ayaba Ṣeba ní gbogbo ohun tí ó béèrè fún àti ohun tí ó wù ú; ó sì fi fún un ju èyí tí ó mú wá fún un lọ. Nígbà náà ni ó lọ ó sì padà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sí ìlú rẹ̀.
Hina bagade Soloumane da Siba soge uda hina bagade ema ea adole ba: i liligi huluane ema i. Amola Siba sogega uda hina bagade da ema hahawane dogolegele iasu iabeba: le, amo huluane defele e da Siba hina bagade udama i. Amalalu, uda hina bagade amola ea hawa: hamosu dunu da Siba sogega buhagi.
13 Ìwọ̀n wúrà tí Solomoni gbà ní ọdún kan sì jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà tálẹ́ǹtì,
Ode huluane hina bagade Soloumane da gouli defei danese 20 agoane baligili lasu.
14 láì tí ì ka àkójọpọ̀ owó ìlú tí ó wọlé láti ọ̀dọ̀ àwọn oníṣòwò àti àwọn ọlọ́jà. Àti pẹ̀lú gbogbo àwọn ọba Arabia àti àwọn baálẹ̀ ilẹ̀ náà mu wúrà àti fàdákà wá fún Solomoni.
Amola e da bidi lasu ouligisu dunuma su (‘da: gisi’) lai. E da bidi lasu hou hamobeba: le eno baligili gale lai. Amola Ala: ibia hina bagade amola Isala: ili gilisisu soge bai ouligisu dunuma bidi afadenei ianusu lai.
15 Ọba Solomoni sì ṣe igba asà wúrà lílù; ẹgbẹ̀ta ṣékélì tí a fi òlùlù wúrà sí ọ̀kánkán asà.
Soloumane da sia: beba: le, ilia da da: igene ga: su bagade 200 agoane hahamoi. Amo afae afaega ilia da gouli defei 6gilougala: me agoane amoga dedebole legele ga: i.
16 Ó sì ti ṣe ọ̀ọ́dúnrún kékeré ṣékélì tí a fi òlùlù wúrà, pẹ̀lú ọ̀ọ́dúnrún ṣékélì wúrà nínú àpáta kọ̀ọ̀kan. Ọba sì kó wọn sínú ààfin ti ó wà ní igbó Lebanoni.
Amolawane, e da da: igene ga: su fonobahadi 300 agoane hamone, ilima gouli defei2 gilougala: me gadenene, amoga dedebole legele gaga: i. Ea sia: beba: le, ilia da amo da: igene ga: su huluane Lebanone Iwila Sesei amo ganodini sali.
17 Nígbà náà ọba sì ṣe ìtẹ́ pẹ̀lú eyín erin ńlá kan ó sì fi wúrà tó mọ́ bò ó.
Amolawane, ea hamoma: ne sia: beba: le, ilia da fisu bagadedafa hamoi. Amo fisu la: ididili da ‘aifoli’ amoga dedeboi amola eno la: idi da gouli noga: idafa amoga dedeboi.
18 Ìtẹ́ náà sì ní àtẹ̀gùn mẹ́fà, àti pẹ̀lú àpótí ìtìsẹ̀ wúrà kan ni a dè mọ́ ọn. Ní ìhà méjèèjì ibi ìjókòó ní ó ní ìgbọ́wọ́lé, pẹ̀lú kìnnìún tí ó dúró lẹ́bàá olúkúlùkù wọn.
19 Kìnnìún méjìlá dúró lórí àtẹ̀gùn mẹ́ta, ọ̀kan àti ní ìhà olúkúlùkù àtẹ̀gùn kò sì sí irú rẹ̀ tí a ti ṣe rí fún ìjọba mìíràn.
Amo fisu da: iya heda: su fofa: gui da gafeyale ba: i. Fa: gu afae afae amo ea bidiga huluane da laione wa: me agoaila dedenesisi ba: i. Amo gilisili da laione agoaila fagolisi galu ba: i. Fisu baligiadili da bulamagau gawali ea dialuma agoaila dedenesisi ba: i. Amola fisu ea lobo ligisisu aduna la: idi gadili da laione agoaila dedenesisi ba: i. Fisu amo agoai da fifi asi gala huluane amo ganodini afae hamedafa ba: i.
20 Gbogbo ohun èlò mímú ìjọba Solomoni ọba ni ó jẹ́ kìkì wúrà, àti gbogbo ohun èlò ààfin ní igbó Lebanoni ni ó jẹ́ wúrà mímọ́. Kò sì ṣí èyí tí a fi fàdákà ṣe, nítorí a kò ka fàdákà sí nǹkan kan ní gbogbo ọjọ́ Solomoni.
Soloumane ea hano nasu faigelei huluane da gouligamusu hahamoi. Amola gobele nasu liligi amola gasa: le nasu liligi huluane Lebanone Iwila Sesei amo ganodini dialu da gouligamusu hahamoi. Liligi afae da silifaga hame hahamoi. Bai Soloumane ea esalebe eso amoga, ilia da silifa bagade hame hanai galu.
21 Ọba ní ọkọ̀ tí a fi ń tajà tí àwọn ọkùnrin Hiramu ń bojútó. Ẹ̀ẹ̀kan ní ọdún mẹ́ta ni ó máa ń padà, ó ń gbé wúrà àti fàdákà àti eyín erin àti ìnàkí.
Soloumane da dusagane gagai gilisisu amo da gilisili Haila: me ea dusagane gagai gilisisu, hano wayabo bagadega ahoanu. Ode udiana gidigili, ea dusagane gagai gilisisu da gouli, silifa, ‘aifoli’ amola ‘magi’ ohe gaguiwane, ema buhagisu.
22 Ọba Solomoni sì tóbi nínú ọláńlá àti ọgbọ́n ju gbogbo àwọn ọba tí ó kù lórí ilẹ̀ ayé lọ.
Hina bagade Soloumane ea bagade dawa: su hou amola bagade gagui hou da osobo bagadega hina bagade huluane ilia hou baligi dagoi ba: i.
23 Gbogbo àwọn ọba ayé ń wá ojúrere lọ́dọ̀ Solomoni láti gbọ́n ọgbọ́n tí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn rẹ̀.
Amola fifi asi gala huluane da bagade dawa: su amo Gode da ema i, amo nabimusa: , ema misunu hanai galu.
24 Ní ọdọọdún, olúkúlùkù ẹni tí o wá mú ẹ̀bùn ohun èlò wúrà àti fàdákà àti aṣọ ìbora, ìhámọ́ra, àti tùràrí, àti ẹṣin àti ìbáaka wá.
Ode huluane mae fisili, ilia da e ba: la manoba, bidi gagulimusu masu. Ilia da silifa, gouli, abula, gegesu liligi, hedama: ne fodole nasu, hosi amola ‘miule’ amo gagaguli mafia: su.
25 Solomoni sì ní ẹgbàajì ilé fún àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́, àti ẹgbàá mẹ́fà àwọn ẹṣin, tí ó fi pamọ́ nínú ìlú kẹ̀kẹ́ àti pẹ̀lú rẹ̀ nínú Jerusalẹmu.
Soloumane da gegemusa: gini, sa: liode sesei 400 agoane amola dadi gagui dunu fila heda: ma: ne hosi 12,000 agoane gagadoi. Mogili e da Yelusaleme moilai bai bagadega dialoma: ne yolesi. Amola mogili e da moilai oda enoenoi amoga dialoma: ne yolesisi.
26 Ó sì jẹ ọba lórí gbogbo àwọn ọba láti odò Eufurate títí dé ilé àwọn ará Filistini àti títí ó fi dé agbègbè ti Ejibiti.
E da hina bagade huluane amo da soge Iufala: idisi Hanoga asili Filisidini soge amola Idibidi alaloa doaga: i, amo ouligisu, e da ili huluanema ouligisudafa esalu.
27 Ọba sì sọ fàdákà dàbí òkúta ní Jerusalẹmu, àti igi kedari ni ó sì ṣe bí igi sikamore, tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Soloumane ea ouligibi ganodini, silifa da Yelusaleme moilai bai bagade ganodini bagadewane dialebeba: le, udigili gele agoai diafulubi ba: i. Amola dolo ifa da gilisidafaba: le, ‘sigamo’ udigili ifa Yuda agolo sogega lelefulubi ilia idi defele agoai ba: i.
28 A sì mú àwọn ẹṣin Solomoni wa láti ilẹ̀ òkèrè láti Ejibiti àti láti gbogbo ìlú.
Hina bagade ea bidi lasu ouligisu dunu da Musa: li amola Silisia soge amoga hosi bidi lale, Isala: ili sogega oule misi.
29 Àti gẹ́gẹ́ bí ìyókù iṣẹ́ ìjọba Solomoni, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn Natani wòlíì, àti nínú ìsọtẹ́lẹ̀ Ahijah ará Ṣilo àti nínú ìran Iddo, wòlíì tí o so nípa Jeroboamu ọmọ Nebati?
Hou huluane amo Soloumane hamoi, ea hawa: hamosu mui amola dagosu, amo da “Balofede dunu Na: ida: ne ea Hamonanusu Meloa, amola Siailou dunu Ahaidia ea Ba: la: lusu Meloa” amola “Balofede Dunu Idou ea Esalebe Ba: i Meloa”, amo ganodini dedene legei. Amo meloa dedei ilia da amolawane da Isala: ili hina bagade Yeleboua: me ea hou olelesa.
30 Solomoni jẹ ọba ní Jerusalẹmu lórí gbogbo àwọn Israẹli fún ogójì ọdún
E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode40agoane Isala: ili fi ouligisu.
31 Solomoni sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín ní ìlú Dafidi baba rẹ̀, Rehoboamu, ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
E da bogole, Da: ibidi Moilai bai bagade amo ganodini uli dogonesali. Eagofe Lihouboua: me da e bagia Isala: ili hina bagade hamoi

< 2 Chronicles 9 >