< 2 Chronicles 7 >

1 Nígbà tí Solomoni sì ti parí àdúrà, iná sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run ó sì jó ẹbọ sísun àti ẹbọ, ògo Ọlọ́run sì kún ilé Olúwa.
Ie nihenefe’ i Selomò i filolo­fa’ey, le nidoindoiñe boak’ andikerañe eñe ty afo nampibotseke i enga oroañey naho o soroñeo vaho nandifotse i anjomba’ Iehovày ty enge’ Iehovà.
2 Àwọn àlùfáà kò sì le wo ilé Olúwa náà nítorí pé ògo Olúwa kún un.
Tsy nahafizilik’ añ’ anjomba’ Iehovà ao o mpisoroñeo amy te nañatseke i anjombay ty enge’ Iehovà.
3 Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli rí iná tí ó ń sọ̀kalẹ̀ àti ògo Olúwa lórí ilé Olúwa náà, wọ́n sì kúnlẹ̀ lórí eékún wọn pẹ̀lú ojú ni dídàbolẹ̀, wọ́n sì sin Olúwa, wọ́n sì fi ìyìn fún Olúwa wí pé, “Nítorí tí ó dára; àánú rẹ̀ sì dúró títí láéláé.”
Niisa’ o ana’ Israele iabio ty nivotraha’ i afoy naho ty enge’ Iehovà amy anjombay; le nibokok’ an-damoke eo, nidròdreke mb’an-tane, niambane naho nañandriañe Iehovà: Amy te Ie ro soa, nainai’e ty fiferenaiña’e.
4 Nígbà náà ọba àti gbogbo àwọn ènìyàn sì rú ẹbọ níwájú Olúwa.
Le songa nanao soroñe añatrefa’ Iehovà i mpanjakay naho ondatio.
5 Ọba Solomoni sì rú ẹbọ ti ẹgbẹ̀rún méjìlélógún, orí màlúù àti àgùntàn àti ọ̀kẹ́ mẹ́fà àgùntàn àti ẹranko. Bẹ́ẹ̀ ni ọba àti gbogbo àwọn ènìyàn ya ilé Ọlọ́run sí mímọ́.
Nandenta añombe ro’ale-tsi-ro’ arivo hisoroñañe t’i Selomò mpanjaka naho boak’ an-dia-raik’ ao ty rai-hetse-tsi-ro’ ale. Aa le noriza’ i mpanjakay naho ondaty iabio ty anjomban’ Añahare.
6 Àwọn àlùfáà dúró ní ààyè wọn, gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Lefi ti ṣe pẹ̀lú ohun èlò orin Olúwa, tí ọba Dafidi ti ṣe fún ìyìn Olúwa àti tí á lò nígbà tí ó dúpẹ́, wí pé, “Àánú rẹ̀ sì dúró láéláé,” níwájú àwọn ọmọ Lefi, àwọn àlùfáà sì fọn ìpè, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sì dúró.
Nijohañe eo o mpisoroñeo, songa fitoloña’e; o nte-Levio rekets’ o fititihan-tsabo am’ Iehovà niranjie’ i Davide mpanjakao, hañandriañe Iehovà, amy te nainai’e ty fiferenaiña’e, am-pandrengea’ i Davide am-pità’ iareoo; le nampipopò trompetra tandrife iareo o mpisoroñeo; vaho nijohañe iaby t’Israele.
7 Solomoni sì yà àgbàlá níwájú ilé Olúwa sọ́tọ̀, níbẹ̀ sì ni ó ti ṣe ìrúbọ ẹbọ sísun àti ọ̀rá ẹbọ àlàáfíà, nítorí pẹpẹ idẹ tí ó ti ṣe kò lè gba ẹbọ sísun, àti ọrẹ oúnjẹ, àti ọ̀rá náà.
Mbore nimasiñe’ i Selo­mò ty añivon-kiririsa aolo’ i anjomba’ Iehovày; le eo ty nañengà’e i soroñe rey naho o saboran’ engam-panintsiñañeo; amy te tsy naharambe i soroñe rey naho o engan-kaneñeo naho i saboray i kitrely torisike niranjie’ i Selomòy.
8 Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ṣe àsè ní àkókò náà fún ọjọ́ méje àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀lú rẹ̀ àti ìjọ ènìyàn ńlá, àwọn ènìyàn láti Lebo-Hamati títí dé odò Ejibiti.
Aa le nambena’ i Selomò fito andro i sabadidakey naho niharo ama’e iaby t’Israele, toe valobohòke jabajaba, sikal’ am-pimoahañ’ amy Kamate añe pak’ an-toraha’ i Mitsraime añe.
9 Ní ọjọ́ kẹjọ, wọ́n sì pe ìjọ ènìyàn jọ nítorí tí wọ́n pe àpèjẹ ìyàsímímọ́ ti orí pẹpẹ fún ọjọ́ méje àti àsè náà fún ọjọ́ méje sí i.
Le hene nivoribey amy andro fahavaloy, amy te nambena’ iereo fito andro ty fañorizañe i kitreliy vaho fito andro ka i sabadidakey.
10 Ní ọjọ́ kẹtàlélógún tí oṣù keje, ó sì rán àwọn ènìyàn padà sí ilé wọn, pẹ̀lú ayọ̀ àti ìdùnnú nínú wọn fún ohun rere tí Olúwa ti ṣe fún Dafidi àti Solomoni, àti fún àwọn ènìyàn Israẹli.
Aa ie amy andro faha roapolo-telo’ambi’ i vo­lam-pahafitoy, le nampolie’e mb’an-kivoho’e mb’eo ondatio, sambe fale naho nirebek’ an-troke ty amy hasoa naboa’ Iehovà amy Davide naho amy Selomò vaho am’ Israele ondati’eoy.
11 Nígbà tí Solomoni ti parí ilé Olúwa àti ibi ilé ọba, nígbà tí ó sì ti ṣe àṣeyọrí láti gbé jáde gbogbo ohun tí ó ní lọ́kàn láti ṣe nínú ilé Olúwa àti nínú ilé òun tìkára rẹ̀,
Aa le nifonire’ i Selomò i anjomba’ Iehovày naho i anjomba’ i mpanjakaiy; ze hene nimoak’ añ’arofo’ i Selomò le niranjie’e añ’ anjomba’ Iehovà ao naho amy anjomba’ey ho fonitse.
12 Olúwa sì farahàn Solomoni ní òru ó sì wí pé: “Èmi ti gbọ́ àdúrà rẹ mo sì ti yàn ibí yìí fún ara mi gẹ́gẹ́ bí ilé fún ẹbọ.
Niboak’ amy Selomò haleñe t’Iehovà, nanao ama’e ty hoe: Tsinanoko i halali’oy vaho jinoboko ho ahiko ho anjombam-pisoroñañe ty toetse toy.
13 “Nígbà tí mo bá sé ọ̀run kí ó ma bá à sí òjò, tàbí láti pàṣẹ fún eṣú láti jẹ ilẹ̀ náà run tàbí rán àjàkálẹ̀-ààrùn sí àárín àwọn ènìyàn mi,
Aa naho arindriko i likerañey tsy hahavia’e orañe, ke li­lieko o valalao hampibo­tseke i taney, he ampihitrifako angorosy am’ondatikoo;
14 tí àwọn ènìyàn, tí a fi orúkọ mi pè, tí wọ́n bá rẹ ara wọn sílẹ̀, tí wọ́n sì gbàdúrà, tí wọ́n sì rí ojú mi, tí wọ́n sì yí kúrò nínú ọ̀nà búburú wọn, nígbà náà, èmi yóò gbọ́ láti ọ̀run, èmi yóò sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n èmi yóò sì wo ilẹ̀ wọn sàn.
le ie hirè-batañe ondaty tokaveñe ami’­ ty añarakoo, hihalaly naho hipay ty tareheko vaho hifotetse amo fañaveloa’ iareo ratio; le hitsanoñe boak’ andin­diñe ao Raho, le hapoko o tahi’ iareoo vaho ho janganeko o tane’ iareoo.
15 Nísinsin yìí, ojú mi yóò sì là etí mi yóò sì là, sí àdúrà ọrẹ níbí yìí.
Hisokake henaneo o masokoo, le ho tsanoñe’ o sofikoo ze halaly anoeñe ami’ty toetse toy.
16 Èmi sì ti yàn, èmi sì ti ya ilé yìí sí mímọ́ bẹ́ẹ̀ ni kí orúkọ mi kí ó le wà níbẹ̀ títí láéláé.
Fa jinoboko naho nimasiñeko ty anjomba toy henane zao, soa te ho ao kitro-katroke ty añarako vaho ho ama’e nainai’e donia o masokoo naho ty troko.
17 “Ní ti bí ìwọ bá rìn níwájú mi gẹ́gẹ́ bí Dafidi baba rẹ ti ṣe, tí o sì ṣe gbogbo ohun tí mo paláṣẹ, tí ìwọ sì ṣe àkíyèsí àṣẹ mi láti ọ̀run,
Le ie hañavelo añatrefako, manahake ty fañaveloa’ i Davide rae’o, hanao o fonga nandiliako azoo, hañambeñe o fañèkoo naho o fepèkoo;
18 Èmi yóò fi ìdí ìtẹ́ ìjọba rẹ múlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe pẹ̀lú Dafidi baba rẹ nígbà tí mo bá a dá májẹ̀mú wí pé, ìwọ kò ní fẹ́ ẹnìkan kù láti ṣe alákòóso lórí Israẹli.
le horizako ty fiambesam-pifeleha’o, ty amy fañinako amy Davide rae’o, nanao ty hoe: Tsy ho po-ondaty hifehe Israele irehe.
19 “Ṣùgbọ́n tí ìwọ bá yípadà tí o sì kọ òfin mi sílẹ̀ àti àṣẹ tí mo ti fi fún yín tí ẹ sì lọ sókè láti lọ sin ọlọ́run mìíràn tí ẹ sì bọ wọ́n,
Fe naho hivìke añe irehe hamorintse­ñe o fañèkoo naho o fepèko najadoko añatrefa’ areoo vaho hia­votse hitoroñe ndrahare ila’e hitalahoa’ areo;
20 nígbà náà ni èmi yóò fa Israẹli tu kúrò láti ilẹ̀ mi, èyí tí èmi ti fi fún wọn, èmi yóò sì kọ̀ ilé náà sílẹ̀ èyí tí èmi ti yà sọ́tọ̀ fún orúkọ mi, èmi yóò sì fi ṣe ọ̀rọ̀ òwe, n ó fi ṣe ẹlẹ́yà láàrín gbogbo ènìyàn,
le hombotako reke-bahatse an-taneko natoloko iareo; le ty anjomba nimasiñeko ho ami’ty añarako toy ro hahifiko tsy ho am-pahatreavako añe, fa hanoeko razan-drehake naho fandrabioña’ ze kilakila’ ondaty.
21 àti ní gbogbo àyíká ilé yìí nísinsin yìí, bẹ́ẹ̀ ni yóò di ohun ìtànjẹ; gbogbo àwọn tí ó bá sì kọjá níbẹ̀ ni yóò jáláyà, wọn yóò sì wí pé, ‘Kí ni ó dé tí Olúwa fì ṣe irú èyí sí ilẹ̀ yí àti sí ilé yìí?’
Le ty anjomba mandigiligy toy, ro hilatsà ze fonga mpiary ama’e, hanao ty hoe; Aa vaho akore te nanoe’ Iehovà zao o tane toañeo naho i anjomba’ey?
22 Àwọn ènìyàn yóò sì dáhùn wí pé, ‘Nítorí tí wọ́n ti kọ̀ Olúwa sílẹ̀, Ọlọ́run baba wọn ẹni tí ó mú wọn jáde láti Ejibiti wá, wọ́n sì ti fi ọwọ́ gba ọlọ́run mìíràn mọ́ra, wọ́n bọ wọ́n, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń sìn wọ́n, ìdí nìyí tí ó fi mú gbogbo ìjàǹbá náà wá sórí wọn.’”
Le hoe ty havali’ iareo: Ie namorintseñe Iehovà Andrianañaharen-droae’ iareo nañavotse iareo an-tane Mitsraime añe, mbore nandrambe ndrahare ila’e naho nitalahoa’ iareo vaho nitoroña’ iareo; toly ndra naobo’e am’iereo o fonga hankàñe zao.

< 2 Chronicles 7 >