< 2 Chronicles 6 >

1 Nígbà náà ni Solomoni wí pé, “Olúwa ti sọ wí pé òun yóò máa gbé nínú òkùnkùn tí ó ṣú biribiri;
A LAILA, olelo aku la o Solomona, I mai la o Iehova, e no ho ia iloko o ka pouli nui.
2 ṣùgbọ́n èmi ti kọ́ tẹmpili dáradára fún ọ ibi tí ìwọ yóò máa gbé títí láé.”
Aka, ua kukulu au i hale noho nou, i wahi nou e noho mau loa ai.
3 Ní ìgbà tí gbogbo ìjọ Israẹli dúró níbẹ̀, ọba yíjú padà ó sì fi ìbùkún fún gbogbo wọn.
Alaila, huli ae la ko ke alii mau maka, a hoomaikai aku la ia i ka ahakanaka a pau o ka Iseraela; a ku ae la iluna ka ahakanaka a pau o ka Iseraela.
4 Nígbà náà ni ó sì wí pé: “Ògo ni fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ mú ohun tí ó fi ẹnu rẹ̀ sọ fún Dafidi baba mi ṣẹ. Nítorí tí ó wí pé,
Olelo aku la ia, E hoomaikaiia o Iehova ke Akua o ka Iseraela, ka mea nana i olelo mai me kona waha ia Davida, i ko'u makuakane, a hooko mai hoi me kona mau lima, i ka i ana mai,
5 ‘Láti ọjọ́ tí èmi ti mú àwọn ènìyàn mi jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, èmi kò yan ìlú kan nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli, láti kọ́ ilé, kí orúkọ mi kí ó lè wà níbẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò yan ẹnikẹ́ni láti jẹ́ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi.
Mai ka wa mai a'u i lawe mai ai i ko'u poe kanaka mai ka aina mai o Aigupita, aole au i wae aku i kulanakauhale noloko mai o na ohana a pau o ka Iseraela, i wahi e kukulu ai i hale e waihoia'i ko'u inoa malaila; aole hoi au i wae aku i ke kanaka e noho alii maluna o ko'u poe kanaka o ka Iseraela.
6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi ti yan Jerusalẹmu, kí orúkọ mi le è wà níbẹ̀, èmi sì ti yan Dafidi láti jẹ ọba lórí Israẹli ènìyàn mi.’
Aka, ua wae aku au ia Ierusalema i waihoia'i ko'u inoa malaila; a ua wae aku au ia Davida e noho maluna o ko'u poe kanaka, o ka Iseraela.
7 “Baba mi Dafidi ti ní-in lọ́kàn láti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, àní Ọlọ́run Israẹli.
Aia no iloko o ka naau o Davida, ko'u makua e kukulu i hale no ka inoa o Iehova ke Akua o ka Iseraela.
8 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Dafidi baba mi pé, ‘Nítorí tí ó wà ní ọkàn rẹ láti kọ́ tẹmpili yìí fún orúkọ mi, ìwọ ṣe ohun dáradára láti ní èyí ní ọkàn rẹ̀.
Olelo mai la o Iehova ia Davida, i ko'u makuakane, aia no iloko o kou naau e kukulu i hale no ko'u inoa, a ua pono ia manao iloko o kou naau.
9 Ṣùgbọ́n síbẹ̀, ìwọ kọ́ ni yóò kọ́ tẹmpili náà, bí kò ṣe ọmọ rẹ, ẹni tí o jẹ́ ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ rẹ: òun ni yóò kọ́ tẹmpili fún orúkọ mi.’
Aka hoi, aole oe e kukulu i ka hale, o kau keiki ka mea e puka mai ana mai loko mai o kou puhaka, oia ka mea nana e kukulu ka hale no ko'u inoa.
10 “Olúwa sì ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ. Èmi ti dìde ní ipò Dafidi baba mi, a sì gbé mi ka ìtẹ́ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti ṣe ìlérí, èmi sì ti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
Ua hooko mai o Iehova i ka olelo ana i olelo mai ai; no ka mea, ua ku ae au mahope o Davida ko'u makuakane, a ke noho nei au maluna o ka noho alii o ka Iseraela e like me ka olelo a Iehova, a ua kukulu au i hale no ka inoa o Iehova, ke Akua o ka Iseraela.
11 Níbẹ̀ ni èmi sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí, nínú èyí ti májẹ̀mú ti Olúwa bá àwọn Israẹli ènìyàn mi dá wà.”
A ua hookomo au ilaila i ka pahu, aia iloko ka berita o Iehova ana i hana'i me ka poe mamo a Iseraela.
12 Nígbà náà ni Solomoni dúró níwájú pẹpẹ Olúwa, ní iwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì.
Ku ae la iluna o Solomona imua o ke kuahu o Iehova, imua o ka ahakanaka a pau o ka Iseraela, a hohola ae la i kona mau lima.
13 Solomoni ṣe àga idẹ kan tí ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ní gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta ní gíga, a gbé e sí àárín àgbàlá ti òde. Ó sì dúró ní orí rẹ̀, àti pé ó kúnlẹ̀ lórí eékún rẹ̀ níwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì sí òkè ọ̀run.
No ka mea, ua hana o Solomona i awai keleawe, elima kubita ka loa, elima ka laula, a ekolu ke kiekie, a ua waiho oia ia mea mawae na konu o ka pahale; a ku oia ma luna o ia mea, kukuli ihe la ma kona kuli imua o ka ahakanaka a pau o ka Iseraela, a hohola ae la i kona mau lima i ka lani,
14 Ó wí pé: “Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, kò sí Ọlọ́run tí ó dàbí rẹ ní ọ̀run àti ní ayé: ìwọ tí o pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ mọ́ pẹ̀lú àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí ń fi tọkàntọkàn wọn rìn ní ọ̀nà rẹ.
Olelo aku la ia, E Iehova ke Akua o ka Iseraela, aohe Akua e like me oe ma ka lani, aole hoi ma ka honua, e malama ana i ka berita a me ke aloha no kau poe kauwa, no ka poe e hele ana imua ou me ko lakou naau a pau.
15 Ìwọ tí o pa ìlérí tí o ṣe pẹ̀lú ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi mọ́; nítorí ìwọ ti fi ẹnu rẹ ṣe ìlérí àti pé ìwọ ti fi ọwọ́ rẹ mú un ṣẹ; bí ó ti rí lónìí yìí.
Ua malama mai oe i ka mea au i olelo mai ai i kau kauwa ia Davida i ko'u makua. Ua olelo mai oe me kou waha, a ua hooko mai me kou lima e like me ia i keia la.
16 “Nísinsin yìí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pa ìlérí tí ó ti ṣe mọ́ fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi nígbà tí o wí pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ fẹ́ kù láti ní ọkùnrin láti jókòó níwájú mi lórí ìtẹ́ Israẹli, kìkì bí àwọn ọmọ rẹ tí wọ́n bá kíyèsi ara nínú gbogbo ohun tí wọ́n ṣe láti rìn níwájú mi gẹ́gẹ́ bí òfin mi gẹ́gẹ́ bí o sì ti ṣe.’
Ano, e Iehova ke Akua o ka Iseraela, e hooko mai no kau kauwa no Davida, no ko'u makuakane i ka mea au i olelo mai ai ia ia, i mai ana, Aole oe e nele i ke kanaka imua o'u e noho maluna o ka noho alii o ka Iseraela, ke malama kau poe mamo i ko lakou aoao e hele ma ko'u kanawai e like me kou he le ana imua o'u.
17 Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run Israẹli, jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ tí o ti ṣèlérí fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi kí ó wá sí ìmúṣẹ.
Ano, e Iehova ke Akua o ka Iseraela, e hooiaioia ka olelo au i olelo ai i kau kauwa ia Davida.
18 “Ṣùgbọ́n ṣé Ọlọ́run nítòótọ́ yóò máa bá àwọn ènìyàn gbé lórí ilẹ̀ ayé bí? Ọ̀run àti ọ̀run gíga kò le gbà ọ́. Báwo ni ó ṣe kéré tó, ilé Olúwa tí mo ti kọ́!
Aka, he mea oiaio anei, e noho ana ke Akua me kanaka ma ka honua? Aia hoi, he uuku ia oe ka lani, a me ka lani o na lani! Pehea hoi keia hale a'u i hana ai!
19 Síbẹ̀ ṣe àfiyèsí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ àti ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ fún àánú, Olúwa Ọlọ́run mi, gbọ́ ẹkún àti àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ̀ ń gbà níwájú rẹ.
E maliu mai i ka pule a kau kauwa, a i ka mea ana i noi aku ai, e Iehova, e ko'u Akua, e hoolohe i ke kahea ana'ku a me ka pule a kau kauwa e pule aku nei imua ou:
20 Kí ojú rẹ kí ó lè ṣí sí ilé Olúwa ní ọ̀sán àti lóru, ní ibí yìí tí ìwọ ti wí pé ìwọ yóò fi orúkọ rẹ síbẹ̀. Kí ìwọ kí ó gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà lórí ibí yìí.
I kaakaa kou mau maka maluna o keia hale i ke ao, a me ka po, maluna o kahi au i olelo ai e waiho mai i kou inoa malaila; e hoolohe i ka pule a kau kauwa e pule aku ai ma keia wahi.
21 Gbọ́ ẹ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ àti ti àwọn ènìyàn Israẹli nígbà tí wọ́n bá ń gbàdúrà lórí ibí yìí. Gbọ́ láti ọ̀run, ibùgbé rẹ, nígbà tí ìwọ bá sì gbọ́, dáríjì.
E hoolohe mai i ka pule a kau kauwa, a me kou poe kanaka o ka Iseraela, ka mea a lakou i noi aku ai ma keia wahi. E maliu mai oe, mai kou wahi e noho ai, mai ka lani mai, e hoolohe mai a e kala mai hoi.
22 “Nígbà tí ọkùnrin kan bá dẹ́ṣẹ̀ sí ẹnìkejì rẹ̀, tí a sì mú búra, tí ó sì búra níwájú pẹpẹ rẹ nínú ilé yìí,
Ina e hana hewa ke kanaka i kona hoalauna, a kauia maluna ona ka olelo hoohiki i mea nona e hoohiki ai, a komo ka olelo hoohiki imua o kou kuahu iloko o keia hale;
23 nígbà náà, gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dáhùn. Ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn ìránṣẹ́ rẹ, san padà fún ẹni tí ó jẹ̀bi nípa mímú padà wá sí orí òun tìkára rẹ̀ ohun tí ó ti ṣe. Ṣe ìdáláre fún olódodo, bẹ́ẹ̀ sì ni, fi fún un gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ̀.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai, a e hooponopono, a e hookolokolo i kau poe kauwa, e hoouku i ka mea hewa, e hoopai no i kona aoao maluna o kona poo iho; a e apono mai i ka mea pono, e haawi ia ia e like me kona pono iho.
24 “Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ Israẹli bá ní ìjákulẹ̀ níwájú àwọn ọ̀tá nítorí wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ àti nígbà tí wọ́n bá sì yípadà, tí wọ́n sì jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, tí wọ́n gbàdúrà, tí wọ́n sì bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ nínú ilé Olúwa yìí,
Ina e hee kou poe kanaka o ka Iseraela imua o ko lakou poe enemi, no ka lakou hana hewa ana ia oe; a huli lakou a hooia i kou inoa, a e pule aku a e noi aku imua ou iloko o keia hale;
25 nígbà náà, ni kí o gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn Israẹli jì wọ́n kí o sì mú wọn padà wá sílé tí o ti fi fún wọn àti àwọn baba wọn.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai. a e kala mai i ka hewa o kou poe kanaka o ka Iseraela, a e hoihoi ia lakou ma ka aina au i haawi mai ai ia lakou, a me ko lakou poe kupuna.
26 “Nígbà tí a bá ti ọ̀run, tí kò sì sí òjò nítorí àwọn ènìyàn rẹ ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ, nígbà tí wọ́n bá sì gbàdúrà sí ibí yìí tí wọ́n sì jẹ́wọ́ orúkọ rẹ tí wọ́n sì yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn nítorí ìwọ ti pọ́n wọn lójú,
I ka wa e paa ai ka lani, aohe ua, no ka mea, ua hana hewa lakou ia oe; a pule lakou ma keia hale, a e hooia aku i kou inoa, a e huli ae mai ko lakou hewa mai, i ka wa au e hookaumaha ai ia lakou;
27 nígbà náà gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli kọ́ wọn ní ọ̀nà tí ó tọ́ nínú èyí tí wọn ó máa rìn, kí o sì rọ òjò sórí ilẹ̀ tí o ti fi fún àwọn ènìyàn rẹ fún ìní.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai, a e kala mai i ka hewa o kau poe kauwa, a me kou poe kanaka o ka Iseraela i ka wa e ao ai oe ia lakou i ka aoao maikai kahi a lakou e hele ai; a e haawi mai oe i ka ua maluna o ka aina au i haawi ai i kou poe kanaka i mea e ili mau ana no lakou.
28 “Nígbà tí ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn bá wá sí ilẹ̀ náà, ìrẹ̀dànù tàbí ìmúwòdù, eṣú tàbí ẹlẹ́ǹgà, tàbí nígbà tí àwọn ọ̀tá wọn bá yọ wọ́n lẹ́nu nínú ọ̀kan lára àwọn ìlú wọn, ohunkóhun, ìpọ́njú tàbí ààrùn lè wá.
Ina he kau wi ma ka aina, he ahulau, he huaai malili paha, a me ka punahelu, a me na uhini, a me na peelua; ina o puni lakou i ko lakou poe enemi, ma ka aina ma ko lakou mau ipuka; o ka eha a me ke kaumaha a pau;
29 Nígbà tí àdúrà tàbí ẹ̀bẹ̀ bá sì wá láti ọ̀dọ̀ ẹnikẹ́ni àwọn ènìyàn rẹ Israẹli olúkúlùkù mọ̀ nípa ìpọ́njú rẹ̀ àti ìbànújẹ́, tí ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì sí ìhà ilé Olúwa yìí.
O ka pule a pau, a me ke noi ana'ku a pau a kela kanaka keia kanaka a kou poe kanaka a pau o ka Iseraela e pule aku ai, aia ike kela mea keia mea i kona eha a me kona kaumaha, a e hohola ia i ko na mau lima ma keia hale;
30 Nígbà náà gbọ́ láti ọ̀run ibùgbé rẹ dáríjì, kí o sì pín fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́ bí i gbogbo ohun tí ó ṣe, nígbà tí ìwọ ti mọ ọkàn rẹ̀ (nítorí ìwọ nìkan ni ó mọ ọkàn ènìyàn.)
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai, o kou wahi e noho ai, a e kala mai, a e haawi i kela kanaka keia kanaka e like me kona aoao iho, i kou ike ana i kona naau; (no ka mea, o oe wale no ka i ike i ka naau o na keiki a kanaka; )
31 Bẹ́ẹ̀ ni kí wọn kí ó lè bẹ̀rù rẹ kí wọn kí ó sì rìn ní ọ̀nà rẹ ní gbogbo ìgbà tí wọ́n ń gbé nínú ilé tí o ti fi fún àwọn baba wa.
I makau lakou ia oe, i hele ma kou aoao i na la a pau loa o ko lakou ola ana ma ka aina au i haawi mai ai i ko makou poe kupuna.
32 “Ní ti àwọn àlejò tí wọn kò sí lára àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ṣùgbọ́n tí wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn nítorí orúkọ ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ àti nínà apá rẹ, nígbà tí ó bá wá tí ó sì gbàdúrà pẹ̀lú kíkojú si ilé Olúwa yìí.
A o ka malihini, ka mea aole no kou poe kanaka o ka Iseraela, ka mea i hele mai, mai ka ai na loihi e mai, no kou inoa nui, a no kou lima ikaika, a me kou lima kakauha; a hele mai lakou e pule ma keia hale;
33 Nígbà náà, gbọ́ láti ọ̀run àní láti ibi ibùgbé rẹ, kí o sì ṣe ohun tí àwọn àlejò béèrè lọ́wọ́ rẹ. Bẹ́ẹ̀ ni kí gbogbo àwọn ènìyàn ayé kí wọn lè mọ orúkọ rẹ kí wọn sì bẹ̀rù rẹ, gẹ́gẹ́ bí Israẹli ènìyàn rẹ ti ṣe, kí wọn kí ó sì lè mọ̀ wí pé ilé yìí tí èmi ti kọ, orúkọ rẹ ni ó ń jẹ́.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai, mai kou wahi e noho ai, a e hana e like me na mea a ka malihini e kahea aku ai ia oe; i ike na kanaka a pau o ka honua i kou inoa, a i makau lakou ia oe e like me kou poe kanaka o ka Iseraela, a i ike noi lakou ua kapaia kou inoa maluna o keia hale a'u i hana ai.
34 “Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ bá lọ sójú ogun lórí àwọn ọ̀tá wọn, nígbàkígbà tí o bá rán wọn, tí wọ́n sì gbàdúrà sí ọ si ìhà ìlú yìí tí ìwọ ti yàn àti ilé Olúwa tí èmi ti kọ́ fún orúkọ rẹ.
I ka wa i hele aku ai kou poe kanaka e kaua aku i ko lakou poe enemi ma ka aoao au e hoouna aku ai lakou, a e pule lakou ma ke alo ma keia kulanakauhale au i wae mai ai, a ma ka hale a'u i hana ai no kou inoa;
35 Nígbà náà gbọ́ àdúrà wọn àti ẹ̀bẹ̀ wọn láti ọ̀run, kí o sì mú ọ̀rọ̀ wọn dúró.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai i ka lakou pule, a me ko lakou noi ana, a e hoopono mai no lakou.
36 “Nígbà tí wọ́n bá sì dẹ́ṣẹ̀ sí ọ—nítorí kò sí ènìyàn kan tí kì í dẹ́ṣẹ̀—bí o bá sì bínú sí wọn tí o bá sì fi wọ́n fún àwọn ọ̀tá, tí wọ́n kó wọn ní ìgbèkùn sí ilẹ̀ tí ó jìnnà réré tàbí nítòsí,
Ina e hana hewa lakou ia oe, (no kamea, aohe kanaka i hana he wa ole, ) a huhu mai oe ia lakou, a haawi oe ia lakou i ko lakou poe enemi, a alakai pio ua poe la ia lakou i ka aina loihi, a i ka aina kokoke paha;
37 ṣùgbọ́n, nígbà tí wọ́n bá sì yí ọkàn wọn padà ní ilẹ̀ tí wọ́n ti mú wọn ní ìgbèkùn, tí wọ́n sì ronúpìwàdà tí wọ́n sì bẹ̀bẹ̀ pẹ̀lú rẹ ní ilẹ̀ ìgbèkùn, wọn ó sì wí pé, ‘Àwa ti dẹ́ṣẹ̀, àwa sì ti ṣe ohun tí kò dára, a sì ti ṣe búburú’;
A e noonoo iho lakou ma ka aina a lakou e noho pio ai, a e huli lakou, a e pule aku ia oe ma ka ai na o ko lakou noho pio ana, me ka i ana'ku, Ua hewa makou, ua lawehala, a ua hana ino aku;
38 tí wọn bá sì yípadà sí ọ pẹ̀lú gbogbo ọkàn àti ẹ̀mí ní ilẹ̀ ìgbèkùn wọn níbi tí wọ́n ti mú wọn, tí wọ́n sì gbàdúrà wọn, kojú si ìlú tí ìwọ ti yàn àti lórí ilé Olúwa tí mo ti kọ́ fún orúkọ rẹ;
A huli lakou ia oe me ko lakou naau a pau, a me ko lakou uhane a pau, ma ka aina o ko lakou noho pio ana kahi i lawe pio ia'i lakou, a pule aku lakou me ka haliu mai o ke alo ma ko lakou aina ka mea au i haawi mai ai i ko lakou poe kupuna, a ma ke kulanakauhale au i wae mai ai, a me ka hale a'u i kukulu ai no kou inoa;
39 nígbà náà, láti ọ̀run, ibi ibùgbé rẹ, gbọ́ àdúrà wọn àti ẹ̀bẹ̀ wọn, kí o sì mú ọ̀ràn wọn dúró, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn jì wọn, tí wọn ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ.
Alaila, e hoolohe mai oe mai ka lani mai, mai kou wahi e noho ai, i ka lakou pule, a me ko lakou noi ana, a e hoopono mai no lakou, a e kala mai i kou poe kanaka i ka mea a lakou i hana hewa aku ai ia oe.
40 “Nísinsin yìí, Ọlọ́run mi, jẹ́ kí ojú rẹ kí ó ṣí kí o sì tẹ́ etí rẹ sílẹ̀ fún àdúrà sí ibí yìí.
Ano, e ko'u Akua, e weheia kou mau maka, e haliu mai hoi kou mau pepeiao i ka pule ma keia wahi.
41 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí dìde, Olúwa Ọlọ́run mi, sí ibi ìsinmi rẹ,
E ku oe, ano, e Iehova ke Akua, iloko o kou wahi e maha ai, o oe a me ka pahu o kou mana; o kou poe kahuna, e Iehova ke Akua, e hoaahuia lakou i ke ola, a o kou poe haipule, e olioli lakou i ka maikai.
42 Olúwa Ọlọ́run mi, má ṣe kọ̀ ẹni àmì òróró rẹ.
E Iehova ke Akua, mai pale ae i ka maka o kau mea i poni ai; e hoomanao oe i ke aloha no Davida, no kau kauwa.

< 2 Chronicles 6 >