< 2 Chronicles 36 >

1 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà mú Jehoahasi ọmọ Josiah wọn sì fi jẹ ọba ní Jerusalẹmu ni ipò baba rẹ̀.
[Yǝⱨuda] zeminidiki hǝlⱪ Yosiyaning oƣli Yǝⱨoaⱨazni tallap, Yerusalemda atisining orniƣa padixaⱨ ⱪilip tiklidi.
2 Jehoahasi sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta.
Yǝⱨoaⱨaz tǝhtkǝ qiⱪⱪan qeƣida yigirmǝ üq yaxta idi; u Yerusalemda üq ay sǝltǝnǝt ⱪildi.
3 Ọba Ejibiti yọ kúrò lórí ìtẹ́ ní Jerusalẹmu, ó sì bù fún un lórí Juda, ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì fàdákà àti tálẹ́ǹtì wúrà kan.
Misir padixaⱨi uni Yerusalemda padixaⱨliⱪtin bikar ⱪildi wǝ Yǝⱨuda zeminiƣa bir yüz talant kümüx, bir talant altun jǝrimanǝ ⱪoydi.
4 Ọba Ejibiti sì mú Eliakimu, arákùnrin Joahasi, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu, ó sì yí orúkọ Eliakimu padà sí Jehoiakimu, ṣùgbọ́n Neko mú Joahasi arákùnrin Eliakimu lọ sí Ejibiti.
Andin Misir padixaⱨi Yǝⱨoaⱨazning orniƣa uning inisi Eliakimni Yǝⱨuda bilǝn Yerusalem üstigǝ padixaⱨ ⱪilip, uning ismini Yǝⱨoakimƣa ɵzgǝrtti; andin Nǝⱪo inisi Yǝⱨoaⱨazni Misirƣa elip kǝtti.
5 Jehoiakimu sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún méjìlá. Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀.
Yǝⱨoakim tǝhtkǝ qiⱪⱪan qeƣida yigirmǝ bǝx yaxta bolup, u Yerusalemda on bir yil sǝltǝnǝt ⱪildi; u Pǝrwǝrdigar Hudasining nǝziridǝ rǝzil bolƣanni ⱪildi.
6 Nebukadnessari ọba Babeli sì mú un, ó sì dè é pẹ̀lú ẹ̀wọ̀n láti mú un lọ sí Babeli.
Babil padixaⱨi Neboⱪadnǝsar uningƣa ⱨujum ⱪilƣili qiⱪip, uni mis zǝnjir bilǝn baƣlap Babilƣa elip kǝtti.
7 Nebukadnessari kó nínú ohun èlò ilé Olúwa lọ si Babeli pẹ̀lú, ó sì fi wọn sí ààfin rẹ̀ ní Babeli.
Nebuⱪadnǝsar yǝnǝ Pǝrwǝrdigar ɵyidiki bir ⱪisim ǝswab-buyumlarni Babilƣa apirip, ɵzining Babildiki buthanisiƣa ⱪoydi.
8 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoiakimu, àwọn ohun ìríra tí ó ṣe àti gbogbo ohun tí a rí nípa rẹ̀, ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Israẹli àti Juda. Jehoiakini ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Yǝⱨoakimning ⱪalƣan ixliri, uning yirginqlik ixliri, uningdiki ǝyiblǝr bolsa mana, «Israil wǝ Yǝⱨuda padixaⱨlirining tarih-tǝzkiriliri» degǝn kitabta pütülgǝndur. Uning oƣli Yǝⱨoakin uning orniƣa padixaⱨ boldi.
9 Jehoiakini sì jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ́ ọba ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta àti ọjọ́ mẹ́wàá ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa.
Yǝⱨoakin tǝhtkǝ qiⱪⱪan qeƣida on sǝkkiz yaxta bolup, u Yerusalemda üq ay on kün sǝltǝnǝt ⱪildi; u Pǝrwǝrdigarning nǝziridǝ rǝzil bolƣanni ⱪildi.
10 Ní àkókò òjò, ọba Nebukadnessari ránṣẹ́ sí i ó sì mú un wá sí Babeli, pẹ̀lú ohun èlò dáradára láti ilé Olúwa, ó sì mú arákùnrin Jehoiakini, Sedekiah, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu.
Yengi yil ɵtkǝndǝ, Neboⱪadnǝsar adǝm ǝwǝtip Yǝⱨoakinni Pǝrwǝrdigar ɵyidiki esil buyumlar bilǝn birliktǝ Babilƣa ǝkǝldürüp, Yǝⱨoakinning taƣisi Zǝdǝkiyani Yǝⱨuda wǝ Yerusalem üstigǝ padixaⱨ ⱪilip tiklidi.
11 Sedekiah jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlá.
Zǝdǝkiya tǝhtkǝ qiⱪⱪan qeƣida yigirmǝ bir yaxta bolup, Yerusalemda on bir yil sǝltǝnǝt ⱪildi;
12 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, kò sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Jeremiah wòlíì ẹni tí ó sọ̀rọ̀ Olúwa.
u Pǝrwǝrdigarning nǝziridǝ rǝzil bolƣanni ⱪildi; Yǝrǝmiya pǝyƣǝmbǝr uningƣa Pǝrwǝrdigarning sɵzlirini yǝtküzgǝn bolsimu, u Yǝrǝmiyaning aldida ɵzini tɵwǝn ⱪilmidi;
13 Ó sì tún ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Nebukadnessari pẹ̀lú, ẹni tí ó mú kí ó fi orúkọ Ọlọ́run búra. Ó sì di ọlọ́run líle, ó sì mú ọkàn rẹ̀ le láti má lè yípadà sí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
u ɵzini Hudaning namida [beⱪinix] ⱪǝsimini iqküzgǝn Neboⱪadnǝsardin yüz ɵridi; boynini ⱪattiⱪ ⱪilip, Israilning Hudasi Pǝrwǝrdigarƣa towa ⱪilip yenixⱪa kɵnglini jaⱨil ⱪildi.
14 Síwájú sí i gbogbo àwọn olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn sì di ẹni tí ń dẹ́ṣẹ̀ gidigidi, pẹ̀lú gbogbo ìríra àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n sì sọ ilé Olúwa di èérí, tí ó ti yà sí mímọ́ ní Jerusalẹmu.
Uning üstigǝ, kaⱨinlarning barliⱪ baxliri bilǝn hǝlⱪning ⱨǝmmisi yat ǝlliklǝrning ⱨǝmmǝ yirginqlik ixlirini dorap, asiyliⱪlirini axurdi; ular Pǝrwǝrdigar Yerusalemda Ɵzigǝ atap muⱪǝddǝs ⱪilƣan ɵyni bulƣiwǝtti.
15 Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn ránṣẹ́ sí wọn láti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ síwájú àti síwájú sí i, nítorí tí ó ní ìyọ́nú sí àwọn ènìyàn rẹ̀ àti sí ibùgbé rẹ̀.
Ularning ata-bowilirining Hudasi bolƣan Pǝrwǝrdigar Ɵz hǝlⱪigǝ wǝ turalƣusiƣa iqini aƣritⱪaqⱪa, tang sǝⱨǝrdǝ ornidin turup ǝlqilirini ǝwǝtip ularni izqil agaⱨlandurup turdi.
16 Ṣùgbọ́n wọ́n ń kùn sí àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run, wọ́n kẹ́gàn ọ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n fi àwọn wòlíì rẹ̀ ṣẹ̀sín títí tí ìbínú Olúwa fi ru sórí wọn, sí àwọn ènìyàn rẹ̀ kò sì ṣí àtúnṣe.
Biraⱪ ular Hudaning ǝlqilirini mazaⱪ ⱪilip, sɵz-kalamlirini mǝnsitmǝytti, pǝyƣǝmbǝrlirini zangliⱪ ⱪilatti; ahir berip Pǝrwǝrdigarning ⱪǝⱨri ɵrlǝp, ⱪutⱪuzƣili bolmaydiƣan dǝrijidǝ hǝlⱪining üstigǝ qüxti.
17 Ó sì mú wá sórí wọn ọba àwọn ará Babeli tí wọ́n bá àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wọn jà pẹ̀lú idà ní ilẹ̀ ibi mímọ́, kò sì ní ìyọ́nú sí àgbà ọkùnrin tàbí ọ̀dọ́mọdébìnrin, wúńdíá, tàbí arúgbó. Ọlọ́run sì fi gbogbo wọn lé Nebukadnessari lọ́wọ́.
Pǝrwǝrdigar xuning bilǝn kaldiylǝrning padixaⱨini ularƣa ⱨujumƣa seliwidi, padixaⱨ ularning muⱪǝddǝs ɵyidǝ yaxlirini ⱪiliqlidi; ⱪiz-yigitlǝr, ⱪerilar, bexi aⱪarƣanlarƣa ⱨeq iq aƣritip olturmay, ⱨǝmmini ɵltürüwǝtti; [Huda] bularning ⱨǝmmisini [Kaldiyǝ] padixaⱨining ⱪoliƣa tapxurdi.
18 Ó sì mú gbogbo ohun èlò láti ilé Ọlọ́run lọ sí Babeli, ńlá àti kékeré àti ìṣúra ilé Olúwa àti ìṣúra ọba àti ìjòyè rẹ̀.
Kaldiyǝ padixaⱨi Hudaning ɵyidiki qong-kiqik demǝy, barliⱪ ⱪaqa-buyumlarni, xundaⱪla Pǝrwǝrdigar ɵyidiki hǝzinilǝrni, xuningdǝk padixaⱨning wǝ ǝmǝldarlirining hǝzinilirini ⱪoymay, Babilƣa elip kǝtti.
19 Wọ́n sì fi iná sun ilé Ọlọ́run, wọ́n sì wó gbogbo ògiri ilé Jerusalẹmu, wọ́n sì jó gbogbo ààfin wọn, wọ́n sì ba gbogbo ohun èlò ibẹ̀ jẹ́.
Kaldiylǝr Hudaning ɵyini kɵydürüwǝtti, Yerusalemning sepilini qeⱪiwǝtti, xǝⱨǝrdiki ⱨǝmmǝ orda-ⱪorƣanlarƣa ot ⱪoyup kɵydürüp, Yerusalemdiki barliⱪ ⱪimmǝtlik ⱪaqa-buyumlarni qeⱪip kukum-talⱪan ⱪildi.
20 Ó sì kó èyí tí ó kù lọ sí Babeli àwọn tí ó rí ibi sá kúrò lẹ́nu idà wọ́n sì di ìránṣẹ́ fún un àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí tí ìjọba Persia fi gba agbára.
Ⱪiliqtin aman ⱪalƣanlarning ⱨǝmmisini [Kaldiyǝ padixaⱨi] Babilƣa tutⱪun ⱪilip ǝkǝtti; ular taki Pars padixaⱨliⱪining sǝltǝnitikiqǝ Babil padixaⱨi wǝ ǝwladlirining ⱪulluⱪida bolup turdi.
21 Ilẹ̀ náà sì gbádùn ìsinmi rẹ̀, ní gbogbo ìgbà ìdahoro, òun sì ń sinmi títí àádọ́rin ọdún fi pé ní ìmúṣẹ ọ̀rọ̀ Olúwa tí a sọ láti ẹnu Jeremiah.
Bularning ⱨǝmmisi Pǝrwǝrdigarning Yǝrǝmiyaning wastisi bilǝn [aldin] eytⱪan [agaⱨ] sɵzi ixⱪa axurulux üqün boldi. Xuning bilǝn zemin ɵzigǝ tegixlik xabat künlirigǝ muyǝssǝr boldi; qünki zemin yǝtmix yil toxⱪuqǝ harabiliktǝ turup «xabat tutup» dǝm elip raⱨǝtlǝndi.
22 Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi ọba Persia, kí ọ̀rọ̀ Olúwa tí a tẹnu Jeremiah sọ bá à le ṣẹ pé, Olúwa run ẹ̀mí Kirusi ọba Persia láti ṣe ìkéde ní gbogbo ìjọba rẹ̀, ó sì kọ ọ́ sínú ìwé pẹ̀lú.
23 “Èyí ni ohun tí Kirusi ọba Persia sọ wí pé: “‘Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, ti fún mí ní gbogbo ìjọba ayé yìí, ó sì ti yàn mí láti kọ́ ilé Olúwa fún òun ní Jerusalẹmu ti Juda. Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yín le gòkè lọ pẹ̀lú rẹ̀; kí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ kí ó wà pẹ̀lú rẹ̀.’”

< 2 Chronicles 36 >