< 2 Chronicles 36 >

1 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà mú Jehoahasi ọmọ Josiah wọn sì fi jẹ ọba ní Jerusalẹmu ni ipò baba rẹ̀.
Na rĩrĩ, andũ a bũrũri ũcio makĩoya Jehoahazu mũriũ wa Josia, makĩmũtua mũthamaki kũu Jerusalemu ithenya rĩa ithe.
2 Jehoahasi sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta.
Jehoahazu aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtatũ rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩeri ĩtatũ.
3 Ọba Ejibiti yọ kúrò lórí ìtẹ́ ní Jerusalẹmu, ó sì bù fún un lórí Juda, ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì fàdákà àti tálẹ́ǹtì wúrà kan.
Mũthamaki wa Misiri akĩmweheria ũthamaki-inĩ kũu Jerusalemu na agĩtuĩra Juda igooti rĩa taranda igana rĩmwe cia betha, na taranda ĩmwe ya thahabu.
4 Ọba Ejibiti sì mú Eliakimu, arákùnrin Joahasi, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu, ó sì yí orúkọ Eliakimu padà sí Jehoiakimu, ṣùgbọ́n Neko mú Joahasi arákùnrin Eliakimu lọ sí Ejibiti.
Mũthamaki wa Misiri agĩtua Eliakimu, mũrũ wa ithe na Jehoahazu, mũthamaki wa gũthamaka Juda na Jerusalemu, na akĩgarũra rĩĩtwa rĩa Eliakimu akĩmũtua Jehoiakimu. No Neko agĩthaamia Jehoahazu mũrũ wa ithe na Jehoiakimu akĩmũtwara Misiri.
5 Jehoiakimu sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún méjìlá. Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀.
Jehoiakimu aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtano rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka ikũmi na ũmwe. Nĩekire maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova Ngai wake.
6 Nebukadnessari ọba Babeli sì mú un, ó sì dè é pẹ̀lú ẹ̀wọ̀n láti mú un lọ sí Babeli.
Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni akĩmũtharĩkĩra, na akĩmuoha na mĩnyororo ya gĩcango akĩmũtwara Babuloni.
7 Nebukadnessari kó nínú ohun èlò ilé Olúwa lọ si Babeli pẹ̀lú, ó sì fi wọn sí ààfin rẹ̀ ní Babeli.
Nebukadinezaru ningĩ nĩatwarire indo cia hekarũ ya Jehova kũu Babuloni na agĩciiga thĩinĩ wa hekarũ yake kuo.
8 Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jehoiakimu, àwọn ohun ìríra tí ó ṣe àti gbogbo ohun tí a rí nípa rẹ̀, ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Israẹli àti Juda. Jehoiakini ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Maũndũ marĩa mangĩ makoniĩ wathani wa Jehoiakimu, na maũndũ ma magigi marĩa eekire, na maũndũ marĩa mothe oonirwo ahĩtĩtie-rĩ, maandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩa athamaki a Isiraeli na a Juda. Nake mũriũ Jehoiakini agĩthamaka ithenya rĩake.
9 Jehoiakini sì jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ́ ọba ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹ́ta àti ọjọ́ mẹ́wàá ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa.
Jehoiakini aarĩ wa mĩaka ikũmi na ĩnana rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩeri ĩtatũ na mĩthenya ikũmi. Nĩekire maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova.
10 Ní àkókò òjò, ọba Nebukadnessari ránṣẹ́ sí i ó sì mú un wá sí Babeli, pẹ̀lú ohun èlò dáradára láti ilé Olúwa, ó sì mú arákùnrin Jehoiakini, Sedekiah, jẹ ọba lórí Juda àti Jerusalẹmu.
Ihinda rĩa mahaanda-rĩ, Mũthamaki Nebukadinezaru akĩmũtũmanĩra, akĩrehwo Babuloni hamwe na indo cia goro kuuma hekarũ-inĩ ya Jehova, nake agĩtua Zedekia, ithe mũnini wa Jehoiakini, mũthamaki wa gũthamaka Juda na Jerusalemu.
11 Sedekiah jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlá.
Zedekia aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ũmwe rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka ikũmi na ũmwe.
12 Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, kò sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Jeremiah wòlíì ẹni tí ó sọ̀rọ̀ Olúwa.
Nĩekire maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova Ngai wake, na ndaigana kwĩnyiihia mbere ya Jeremia ũrĩa mũnabii, ũrĩa waaragia kiugo kĩa Jehova.
13 Ó sì tún ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Nebukadnessari pẹ̀lú, ẹni tí ó mú kí ó fi orúkọ Ọlọ́run búra. Ó sì di ọlọ́run líle, ó sì mú ọkàn rẹ̀ le láti má lè yípadà sí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
O na ningĩ nĩaremeire Mũthamaki Nebukadinezaru, o ũrĩa wamwĩhĩtithĩtie na mwĩhĩtwa akĩgwetaga rĩĩtwa rĩa Ngai. Akĩũmia kĩongo na akĩũmia ngoro yake, na ndaigana gũcookerera Jehova, Ngai wa Isiraeli.
14 Síwájú sí i gbogbo àwọn olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn sì di ẹni tí ń dẹ́ṣẹ̀ gidigidi, pẹ̀lú gbogbo ìríra àwọn orílẹ̀-èdè wọ́n sì sọ ilé Olúwa di èérí, tí ó ti yà sí mímọ́ ní Jerusalẹmu.
O na ningĩ-rĩ, atongoria othe a athĩnjĩri-Ngai na andũ nĩmathiire na mbere kwaga wĩhokeku, makĩrũmĩrĩra mĩtugo ĩrĩ magigi ya ndũrĩrĩ, na magathaahagia hekarũ ya Jehova ĩrĩa aamũrĩte kũu Jerusalemu.
15 Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn ránṣẹ́ sí wọn láti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ síwájú àti síwájú sí i, nítorí tí ó ní ìyọ́nú sí àwọn ènìyàn rẹ̀ àti sí ibùgbé rẹ̀.
Jehova, Ngai wa maithe mao, akĩmatũmĩra ndũmĩrĩri na tũnua twa atũmwo ake rĩngĩ na rĩngĩ, nĩgũkorwo nĩaiguagĩra andũ ake tha, o na gĩikaro gĩake.
16 Ṣùgbọ́n wọ́n ń kùn sí àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run, wọ́n kẹ́gàn ọ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n fi àwọn wòlíì rẹ̀ ṣẹ̀sín títí tí ìbínú Olúwa fi ru sórí wọn, sí àwọn ènìyàn rẹ̀ kò sì ṣí àtúnṣe.
No-o makĩnyũrũria andũ acio maatũmĩtwo nĩ Ngai, makĩmenereria ciugo ciake, na makĩnyarara anabii ake, o nginya marakara ma Jehova makĩarahũkĩra andũ ake na gũkĩaga kĩhonia.
17 Ó sì mú wá sórí wọn ọba àwọn ará Babeli tí wọ́n bá àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wọn jà pẹ̀lú idà ní ilẹ̀ ibi mímọ́, kò sì ní ìyọ́nú sí àgbà ọkùnrin tàbí ọ̀dọ́mọdébìnrin, wúńdíá, tàbí arúgbó. Ọlọ́run sì fi gbogbo wọn lé Nebukadnessari lọ́wọ́.
Akĩmarehithĩria mũthamaki wa andũ a Babuloni amokĩrĩre, ũrĩa woragĩire andũ ao ethĩ na rũhiũ rwa njora kũu nyũmba-inĩ ĩrĩa nyamũre, na ndaigana kũhonokia mwanake, kana mũirĩtu, kana mũndũ mũkũrũ, o na kana ũrĩa mũkũrũ akahocerera. Ngai akĩneana andũ acio othe kũrĩ Nebukadinezaru.
18 Ó sì mú gbogbo ohun èlò láti ilé Ọlọ́run lọ sí Babeli, ńlá àti kékeré àti ìṣúra ilé Olúwa àti ìṣúra ọba àti ìjòyè rẹ̀.
Agĩkuua indo kuuma hekarũ-inĩ ya Ngai, agĩcitwara Babuloni, ciothe iria nene na iria nini, na igĩĩna cia hekarũ ya Jehova, o na igĩĩna cia mũthamaki o na cia anene ake.
19 Wọ́n sì fi iná sun ilé Ọlọ́run, wọ́n sì wó gbogbo ògiri ilé Jerusalẹmu, wọ́n sì jó gbogbo ààfin wọn, wọ́n sì ba gbogbo ohun èlò ibẹ̀ jẹ́.
Ningĩ magĩcina hekarũ ya Ngai na makĩmomora rũthingo rwa Jerusalemu; magĩcina nyũmba ciothe cia ũthamaki, o na makĩananga indo ciothe cia bata iria ciarĩ kuo.
20 Ó sì kó èyí tí ó kù lọ sí Babeli àwọn tí ó rí ibi sá kúrò lẹ́nu idà wọ́n sì di ìránṣẹ́ fún un àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí tí ìjọba Persia fi gba agbára.
Matigari ma andũ arĩa maahonokire kũũragwo na rũhiũ rwa njora-rĩ, Nebukadinezaru akĩmatwara Babuloni, nao magĩtuĩka ndungata ciake na cia ariũ ake, o nginya rĩrĩa ũthamaki wa Perisia wacookire gũthamaka.
21 Ilẹ̀ náà sì gbádùn ìsinmi rẹ̀, ní gbogbo ìgbà ìdahoro, òun sì ń sinmi títí àádọ́rin ọdún fi pé ní ìmúṣẹ ọ̀rọ̀ Olúwa tí a sọ láti ẹnu Jeremiah.
Bũrũri ũgĩkĩgĩa na ũhurũko wa Thabatũ ciaguo; ũkĩhurũka hĩndĩ ĩyo yothe wakirĩte ihooru, nginya mĩaka mĩrongo mũgwanja ĩgĩthira, nĩguo kiugo kĩa Jehova kĩrĩa kĩarĩtio nĩ Jeremia kĩhiinge.
22 Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi ọba Persia, kí ọ̀rọ̀ Olúwa tí a tẹnu Jeremiah sọ bá à le ṣẹ pé, Olúwa run ẹ̀mí Kirusi ọba Persia láti ṣe ìkéde ní gbogbo ìjọba rẹ̀, ó sì kọ ọ́ sínú ìwé pẹ̀lú.
Mwaka wa mbere wa Kurusu mũthamaki wa Perisia, nĩguo kiugo kĩa Jehova kĩrĩa kĩarĩtio nĩ Jeremia kĩhiinge-rĩ, Jehova akĩarahũra ngoro ya Kurusu mũthamaki wa Perisia aanĩrĩrithie kũrĩa guothe aathamakaga, na andĩke atĩrĩ:
23 “Èyí ni ohun tí Kirusi ọba Persia sọ wí pé: “‘Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, ti fún mí ní gbogbo ìjọba ayé yìí, ó sì ti yàn mí láti kọ́ ilé Olúwa fún òun ní Jerusalẹmu ti Juda. Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yín le gòkè lọ pẹ̀lú rẹ̀; kí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ kí ó wà pẹ̀lú rẹ̀.’”
“Kurusu, mũthamaki wa Perisia, oiga ũũ, “‘Jehova, Ngai wa igũrũ, nĩaheete mothamaki mothe ma thĩ, na nĩanyamũrĩte ndĩmwakĩre hekarũ kũu Jerusalemu bũrũri wa Juda. Mũndũ wake o na ũrĩkũ ũrĩ thĩinĩ wanyu, Jehova Ngai wake aroikara hamwe nake, rĩu no aambate athiĩ kuo.’”

< 2 Chronicles 36 >