< 2 Chronicles 34 >

1 Josiah sì jẹ́ ẹni ọdún mẹ́jọ nígbà tí ó jẹ ọba, ó sì dí ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n.
Josia ne ja-higni aboro kane obedo ruoth kendo norito pinyno kodak Jerusalem kuom higni piero adek gachiel.
2 Ó sì ṣe ohun tí ó dára ní ojú Olúwa, ó sì rìn ọ̀nà baba rẹ̀ Dafidi, kò sì yà sí ọwọ́ ọ̀tún tàbí òsì.
Timbe Josia ne longʼo e wangʼ Jehova Nyasaye kendo nowuotho e yore duto mag Daudi kwar-gi ma ok olokore kongʼiyo korachwich kata koracham.
3 Ní ọdún kẹjọ ìjọba rẹ̀, nígbà tí ó sì wà ní ọ̀dọ́mọdé, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í wá ojú Ọlọ́run baba Dafidi. Ní ọdún kejìlá. Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí fọ Juda àti Jerusalẹmu mọ́ kúrò ní ibi gíga rẹ̀, ère òrìṣà Aṣerah, àti ère yíyá àti ère dídà.
E higa mar aboro mar lochne kane pod en rawera nochako luwo Nyasach Daudi kwar mare. E hike mar apar gariyo nochako pwodho Juda kod Jerusalem koketho kuonde motingʼore gi malo mag lemo, gi sirni mag lemo mar Ashera, gi nyiseche mopa kod kido mothedhi.
4 Lábẹ́ àpẹẹrẹ àwọn pẹpẹ Baali ni a yí lulẹ̀, ó sì fọ́ àwọn ère sí wẹ́wẹ́, ó run àwọn pẹpẹ tí ó wà lórí rẹ̀, wọ́n sì fọ́ túútúú, àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà. Èyí tí ó fọ́ wọn sì lúúlúú, ó sì gbọ̀n wọ́n sí orí isà òkú àti àwọn tí ó ń rú ẹbọ sí wọn.
Kaluwore kod chik mane ogolo, kende liswa mag Baal nomuki; nomuko kende mag misango miwangʼoe ubani mane ochungʼ e wigi motoyogi matindo tindo, kendo nomuko sirni mag Ashera milamo, nyiseche manono kod kido milamo mongʼadogi matindo tindo. Magi nongʼinjo matindo tindo mokeyogi ewi liete mag jogo mane otimonegi liswa.
5 Ó sì sun àwọn egungun àwọn àlùfáà lórí pẹpẹ wọn, bẹ́ẹ̀ sì ni ó sì wẹ Juda àti Jerusalẹmu mọ́.
Nowangʼo choke jodolo e kendegi mag misango omiyo nopwodho Juda kod Jerusalem.
6 Ní ìlú Manase, Efraimu àti Simeoni, àní títí ó fi dé Naftali, àti nínú àwọn, ó tú ilé wọn yíkákiri.
Kamano bende e miech Manase gi Efraim kod Simeon nyaka chop Naftali kaachiel gi kuonde molworogi mane osekethi,
7 Ó sì wó pẹpẹ àti ère Aṣerah lulẹ̀ àti àwọn ère yíyá àti àwọn òrìṣà, ó sì gùn ó sì ti ké gbogbo àwọn ère orí pẹpẹ lulẹ̀ ní gbogbo àyíká Israẹli. Lẹ́yìn náà ó padà sí Jerusalẹmu.
nomuko kende mag misango gi sirni mag Ashera milamo kendo notoyo nyisechegi mongʼinyore ka buru kendo nongʼado matindo tindo kende miwangʼoe ubani e piny Israel duto, bangʼe noduogo Jerusalem.
8 Ní ọdún kejìdínlógún ìjọba Josiah ni a ti wẹ ilẹ̀ náà mọ́ àti ilé Olúwa, ó sì rán Ṣafani ọmọ Asalia àti Maaseiah olórí ìlú náà, pẹ̀lú Joah, ọmọ Joahasi, akọ̀wé, láti tún ilé Olúwa Ọlọ́run ṣe.
E higa mar apar gaboro mar loch Josia mondo neni opwodh piny kod hekalu nooro Shafan wuod Azalia gi Maseya jatend dala maduongʼ kaachiel gi Joa wuod Joahaz ma jachan weche mondo olos hekalu mar Jehova Nyasaye ma Nyasache.
9 Wọ́n sì lọ sí ọ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, ó sì fún un ní owó náà tí ó mú wá sí inú ilé Ọlọ́run, ti àwọn ọmọ Lefi ẹni tí ó jẹ́ aṣọ́bodè ti gbà láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn Manase Efraimu àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ìyókù Israẹli àti ọ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn Juda àti Benjamini wọ́n sì padà sí Jerusalẹmu.
Negidhi ir Hilkia jadolo maduongʼ mi gimiye pesa mane osekel e hekalu mar Nyasaye ma jo-Lawi ma jorit dhoudi nosechoko kuom jo-Manase gi jo-Efraim kod jo-Israel duto mane odongʼ gi jo-Juda gi jo-Benjamin kaachiel gi joma nodak Jerusalem.
10 Nígbà náà ni wọn sì fi le àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ilé lọ́wọ́, àwọn tí ń ṣe alábojútó iṣẹ́ ilé Olúwa. Àwọn ọkùnrin yìí sì san owó fún àwọn òṣìṣẹ́ tí ó ń túnṣe, tí wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ ní ilé Olúwa.
Negiketogi e lwet joma otelo ne gedo mar hekalu mar Jehova Nyasaye. Jogi nochulo jotich mane oloso kendo odwogo hekalu kaka ne ochalo chon.
11 Wọ́n sì tún fi owó fún àwọn oníṣọ̀nà àti àwọn olùkọ́lé láti ra òkúta gbígbẹ́ àti ìtì igi fún ìsopọ̀ àti igi rírẹ́ fún ìkọ́lé tí ọba Juda ti gbà láti túnṣe.
Jopa bepe kod jogedo bende nomi pesa mondo gingʼiewgo kite mopa kod yiend ripo kod sirni mondo gilosgo udi mane ruodhi Juda oweyo okethore.
12 Àwọn ọkùnrin náà ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú òtítọ́, láti darí wọn ní Jahati àti Obadiah, àwọn ọmọ Lefi láti Merari, àti Sekariah àti Meṣullamu, sọ̀kalẹ̀ láti Kohati àwọn ọmọ Lefi gbogbo tí ó ní ọgbọ̀n ohun èlò orin.
Jogo ne otiyo tijno gadiera. E tijno notelnigi kod jo-Lawi mane gin Jahath kod Obadia mane gin nyikwa Merari, kendo Zekaria gi Meshulam mane nyikwa Kohath. Jo-Lawi, ma gin jogo duto mane olony kuom goyo thumbe
13 Wọ́n sì ní olórí àwọn aláàárù àti àwọn alábojútó gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ láti ibi iṣẹ́ sí ibi iṣẹ́, díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Lefi sì ní akọ̀wé, olùtọ́jú àti olùṣọ́nà.
ema notelo ne jotich kendo negingʼiyo jotich mag tije mopogore opogore. Jo-Lawi moko ne jogoro gi jopuonj chike kod jorit dhoudi.
14 Nígbà tí wọ́n mú owó náà tí wọ́n mú wá sí ilé Olúwa, Hilkiah àlùfáà sì rí ìwé òfin Olúwa tí a ti fi fún un láti ọwọ́ Mose.
Kane gigolo oko pesa mane oseter e hekalu mar Jehova Nyasaye, Hilkia jadolo nonwangʼo Kitap Chik mar Jehova Nyasaye mane ochiw ne Musa.
15 Hilkiah sì wí fún Ṣafani akọ̀wé pé, “Èmi ti rí ìwé òfin nínú ilé Olúwa.” Ó sì fi fún Ṣafani.
Hilkia nowachone Shafan jagoro niya, “Aseyudo Kitap Chik ei hekalu mar Jehova Nyasaye.” Nochiwe ni Shafan.
16 Nígbà náà Ṣafani sì mú ìwé náà lọ sí ọ̀dọ̀ ọba ó sì ròyìn fún un. “Àwọn ìjòyè rẹ̀ ń ṣe gbogbo nǹkan tí a ti fi lé wọn lọ́wọ́.
Eka Shafan nokawo kitabuno motere ni ruoth mowachone niya, “Jodongi tiyo tije duto mane osemigi.
17 Wọ́n ti san owó náà tí ó wà nínú ilé Olúwa wọ́n sì ti fi lé àwọn alábojútó lọ́wọ́ àti àwọn òṣìṣẹ́.”
Gisechulo pesa mane nitiere e hekalu mar Jehova Nyasaye kendo gisechiwogi e lwet jotich kod jotend hekalu.”
18 Nígbà náà Ṣafani akọ̀wé sì sọ fún ọba, “Hilkiah àlùfáà ti fún mi ní ìwé.” Ṣafani sì kà níwájú ọba.
Bangʼe Shafan jagoro nowachone niya, “Hilkia jadolo osemiya kitabu moro.” Mi Shafan nosomo kitabuno e nyim ruoth.
19 Nígbà tí ọba sì gbọ́ ọ̀rọ̀ òfin, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya.
Kane ruoth owinjo weche mag Chik, noyiecho lepe.
20 Ó sì pa àṣẹ yìí fún Hilkiah, Ahikamu ọmọ Ṣafani, Abdoni ọmọ Mika, Ṣafani akọ̀wé àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba.
Nochiwo chikegi ne Hilkia gi Ahikam wuod Shafan gi Abdon wuod Mika gi Shafan jagoro kod Asaya jarit mar ruoth kowachonegi niya,
21 “Ẹ lọ kí ẹ lọ béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi nípa àwọn ìyókù Israẹli àti Juda nípa ohun tí wọ́n kọ sínú ìwé yìí tí a ti rí. Títóbi ni ìbínú Olúwa tí ó ti jáde sí orí wa nítorí àwọn baba wa kò ti pa ọ̀rọ̀ Olúwa mọ́, wọn kò sì tí ì ṣe gẹ́gẹ́ bí i gbogbo èyí tí a kọ sínú ìwé yìí.”
“Dhiuru upenj Jehova Nyasaye gima biro timorena, jo-Israel kod jo-Juda modongʼ kaluwore gi weche mantiere e kitabu mosenwangʼno. Mirimb Jehova Nyasaye maliel ka mach osechomowa nikech kwerewa ok oserito wach Jehova Nyasaye; kendo ok gisetimo timbe moluwore gi gik moko duto mondiki e kitabuni.”
22 Hilkiah àti àwọn ènìyàn tí ọba yàn tọ Hulda wòlíì obìnrin láti ba sọ̀rọ̀, ẹni tí ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tokhati tí a tún ń pè ní Tikfa, ọmọ Harhasi, olùtọ́jú ibi ìkáṣọsí. Ó sì ń gbé ní Jerusalẹmu, ní ìhà kejì.
Hilkia gi jogo mane ruoth ooro kaachiel kode nodhi ir Hulda janabi madhako mane chi Shalum wuod Tokhath, ma wuod Hasra jarit kar keno mar lep lemo. Nodak Jerusalem e gwengʼ mar ariyo.
23 Ó sì wí fún wọn wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ti sọ, sọ fún àwọn ọkùnrin tí ó rán ọ sí mi pé,
Hulda jadolo madhako nowachonegi niya, “Ma e gima Jehova Nyasaye, ma Nyasach jo-Israel wacho: Nyisuru ngʼatno mane oorou ira niya,
24 ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi yóò sì mú ibi wá sí ìhín yìí àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gbogbo àní ègún tí a kọ sínú ìwé tí wọ́n ti kà níwájú ọba Juda.”
‘Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: Abiro kelo masira e pinyni kendo kuom joma odakie, kaluwore gi kwongʼ duto mondikie kitabu mosesom e nyim ruodh Juda.
25 Nítorí tí wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀ wọ́n sì ti sun tùràrí sí ọlọ́run mìíràn wọ́n sì ti mú mi bínú pẹ̀lú gbogbo ohun tí wọ́n ti fi ọwọ́ wọn ṣe, ìbínú yóò tú jáde wá sórí ibí yìí, a kì yóò sì paná rẹ̀.’
Mirimba nosik kuom pinyni kendo ok norum nikech gisejwangʼa ka giwangʼo ubani ne nyiseche manono kendo ka gimiya mirima kuom lamo nyiseche mopa gi lwedo.’
26 Sọ fún ọba Juda, ẹni tí ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa ti sọ, Ọlọ́run Israẹli, sọ nípa ọ̀rọ̀ wọ́n nì tí ìwọ gbọ́.
Wachneuru ruodh Juda, mane oorou mondo upenja gima Jehova Nyasaye wacho ni, ‘Ma e gima Jehova Nyasaye ma Nyasach jo-Israel wacho kaluwore gi weche musewinjo:
27 Nítorí ọkàn rẹ̀ dúró, ìwọ sì rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa nígbà tí ó gbọ́ ohun tí ó sọ lórí ibí yìí àti ènìyàn rẹ, nítorí ìwọ rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú mi tí o sì fa aṣọ rẹ ya, tí o sì lọ níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ ni Olúwa wí.
Nikech ne uwinjo wach kendo uboloru e nyim Nyasaye kane uwinjo weche mane owacho kuom pinyni kod joma odakie, kendo nikech ne uboloru e nyima, ma uyiecho lepu kuywak e nyima, omiyo asewinjo ywaku, Jehova Nyasaye owacho.
28 Nísinsin yìí, Èmi ó kó ọ jọ pọ̀ sọ́dọ̀ àwọn baba rẹ, a ó sì sin ọ́ ní àlàáfíà. Ojú rẹ kò sì ní rí gbogbo ibi tí èmi ó mú wá sórí ibí yìí àti lórí àwọn tí ń gbé ibẹ̀.’” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n mú ìdáhùn rẹ̀ padà sí ọ̀dọ̀ ọba.
Koro anami iywe gi kwereni kendo noiki gi kwe. Ok inine masiche mabiro kelone pinyni gi joma odakie.’” Omiyo negidwoko wach ne ruoth.
29 Nígbà náà ni ọba sì pe gbogbo àwọn àgbàgbà Juda jọ àti Jerusalẹmu.
Eka ruoth noluongo jodongo duto mag Juda kod Jerusalem kaachiel.
30 Ó gòkè lọ sí ilé Olúwa pẹ̀lú àwọn ọkùnrin Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu, àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi—gbogbo àwọn ènìyàn láti ibi kéékèèké sí ńlá. Ó kà á sí etí ìgbọ́ ọ wọn, gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé májẹ̀mú, tí a ti rí nínú ilé Olúwa.
Nodhi nyaka e hekalu mar Jehova Nyasaye ka en gi jo-Juda, jo-Jerusalem, jodolo, jo-Lawi, kaachiel gi ji duto momewo kod ma jochan. Nosomonegi weche duto mane ondiki e Kitabu mar Singruok mane osenwangʼ e hekalu mar Jehova Nyasaye ka giwinjo.
31 Ọba sì dúró ní ipò rẹ̀ ó sì tún májẹ̀mú dá níwájú Olúwa, láti tẹ̀lé Olúwa àti láti pa òfin rẹ̀ mọ́, àti ẹ̀rí rẹ̀ àti àṣẹ rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ̀ àti gbogbo àyà rẹ̀ àti láti pa ọ̀rọ̀ májẹ̀mú tí a kọ sí inú ìwé yìí.
Ruoth nochungʼ e bath siro kendo noketo winjruok mane oselal obedo kare e nyim Jehova Nyasaye kosingore ni enoluw Jehova Nyasaye kendo norit chikene gi wechene kod buchene gi chunye duto kod pache duto kendo norit weche mag singruok mondiki e kitabuni.
32 Nígbà náà, ó sì mú kí gbogbo ènìyàn ní Jerusalẹmu àti Benjamini dúró nínú ẹ̀rí fún ara wọn, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ṣe èyí gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú Ọlọ́run, Ọlọ́run baba ńlá wọn.
Eka nomiyo jo-Jerusalem duto kod jo-Benjamin okwongʼore ni ginirit singruokno kendo jo-Jerusalem notimo mano kaluwore gi singruok mar Nyasaye, ma Nyasach kweregi.
33 Josiah sì kó gbogbo ohun ìríra kúrò nínú gbogbo ìlú tí ń ṣe ti àwọn tí ó wà ní Israẹli, ó sì mú kí gbogbo àwọn tí ó wà ní Israẹli sin Olúwa Ọlọ́run wọn gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe wà láyè wọn, kò yà kúrò láti máa tọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn lẹ́yìn.
Josia nogolo gik makwero mag nyiseche manono e piny jo-Israel duto kendo nomiyo ji duto modak e piny Israel otiyo ne Jehova Nyasaye, ma Nyasachgi. E ndalo duto mag ngimane ji ne ok oweyo luwo Jehova Nyasaye, ma Nyasach kweregi.

< 2 Chronicles 34 >